< Exodus 10 >

1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Lọ sí ọ̀dọ̀ Farao, mo ti ṣé àyà Farao le àti àyà àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, kí èmi kí o ba le ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu mi láàrín wọn.
BAWIPA ni Mosi, Faro koe cet nateh Kai ni hete mitnoutnaw heh ahnie hmalah patue hane lah,
2 Kí ẹ̀yin ki ó le sọ fún àwọn ọmọ yín àti àwọn ọmọ ọmọ yín; bí mo ti jẹ àwọn ará Ejibiti ní yà àti bí mo ti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu láàrín wọn. Kí ìwọ ba á le mọ̀ pé Èmi ni Olúwa.”
Izip ram dawk ka sak e hnonaw hoi Izip taminaw koe ka sak e mitnoutnaw heh, na ca catounnaw koe na dei pouh teh, Kai teh Jehovah doeh tie nangmouh ni na panue awh nahanelah thoseh, ahni hoi a sannaw e lung teh Kai ni ka pata sak telah atipouh.
3 Nígbà náà ni Mose àti Aaroni tọ Farao lọ, tiwọn sí wí fún un pé, “Èyí ni Olúwa, Ọlọ́run àwọn Heberu sọ, ‘Yóò ti pẹ́ to ti ìwọ yóò kọ̀ láti tẹrí ara rẹ ba ní iwájú mi? Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mi kí ó lọ, kí wọn kí ó sìn mi.
Mosi hoi Aron ni Faro siangpahrang koe a kâen roi teh Hebrunaw e Cathut Jehovah ni, nang ni ka hmalah na kârahnoum laipalah na sittouh maw na o han rah. Ka taminaw ni Kai na bawk na hanelah tâcawt sak leih.
4 Bí ìwọ bá kọ̀ láti jẹ́ kí wọn lọ, èmi yóò mú eṣú wa sí orílẹ̀-èdè rẹ ní ọ̀la.
Ka taminaw na tâcawt sak hoehpawiteh, khenhaw! na ram dawk tangtho samtongnaw ka patoun han.
5 Wọn yóò bo gbogbo ilẹ̀. Wọn yóò ba ohun gbogbo tí ó kù fún ọ lẹ́yìn òjò yìnyín jẹ́, tí ó fi dórí gbogbo igi tí ó ń dàgbà ni ilẹ̀ rẹ.
Talai kamnuek laipalah ahnimouh ni talai muen a ramuk awh han. Roun ni be a dêi hoeh e kaawm rae naw pueng thoseh, nangmouh hanlah talai dawk kapâw e a kung pueng thoseh a ca awh han.
6 Wọn yóò kún gbogbo ilé rẹ àti ilé àwọn ìjòyè rẹ àti ilé gbogbo àwọn ará Ejibiti. Ohun ti baba rẹ tàbí baba baba rẹ kò tí ì rí láti ìgbà tí wọ́n ti wà ní ilẹ̀ náà títí di àkókò yìí.’” Nígbà náà ni Mose pẹ̀yìndà kúrò níwájú Farao.
Na mintoenaw talai dawk khosak kamtawngnae koehoi atu totouh a hmu awh boihoeh e hah na imnaw, na sannaw e imnaw, Izipnaw e imnaw dawk akawi awh han telah a dei pouh roi hnukkhu Faro koehoi a kamlang roi teh a tâco roi.
7 Àwọn ìjòyè Farao sọ fún un, “Yóò ti pẹ́ to tí ọkùnrin yìí yóò máa jẹ́ ìkẹ́kùn fún wa? Jẹ́ kí àwọn ènìyàn yìí lọ, kí wọn kí ó le sìn Olúwa Ọlọ́run wọn. Ṣe ìwọ kò ṣe àkíyèsí síbẹ̀ pé, ilẹ̀ Ejibiti ti parun tán?”
Faro siangpahrang e a sannaw ni hai hete taminaw ni maimouh na totouh maw na tarawk awh han. Hote taminaw ni amamae Cathut Jehovah koe thueng hanelah tâcawt sak leih. Izip ram a rawk e heh na panuek hoeh rah maw telah a dei pouh navah,
8 Nígbà náà ni a mú Aaroni àti Mose padà wá sí iwájú Farao ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ lọ sìn Olúwa Ọlọ́run yín. Ṣùgbọ́n àwọn ta ni nínú yín ni yóò ha lọ.”
Mosi hoi Aron hah Faro siangpahrang koe bout a kâen sak awh teh, nangmae Cathut Jehovah thueng hanelah tâcawt awh. Hateiteh, apipi maw na ka cet awh han telah a pacei navah,
9 Mose dáhùn ó wí pé, “A ó lọ pẹ̀lú àwọn ọmọdé àti àgbà wa, pẹ̀lú àwọn ọmọ wa ọkùnrin àti ọmọ wa obìnrin pẹ̀lú agbo àgùntàn wa àti agbo màlúù wa nítorí pé a gbọdọ̀ ṣe àjọ fún Olúwa.”
Mosi ni, kaimouh teh camo, matawng, ka capanaw, ka canunaw, tu hoi maitonaw hoi ka cei awh han. Bangkongtetpawiteh, BAWIPA koe pawito han ao telah bout atipouh navah,
10 Farao sì wí pé, “Mo fi Olúwa búra pé èmi kí yóò jẹ́ kí ẹ lọ, pẹ̀lú àwọn obìnrin yín àti àwọn ọmọ wẹ́wẹ́, dájúdájú èrò ibi ní ń bẹ nínú yín.
Faro siangpahrang ni nangmouh hoi na canaw teh kai ni na tâco sak e patetlah BAWIPA teh nangmouh koe awm naseh. Kâhruetcuet awh. Kahawi hoeh e pouknae na tawn awh boma.
11 Rárá! Ọkùnrin yín nìkan ni kí ó lọ, láti lọ sin Olúwa, níwọ̀n ìgbà tí ó jẹ́ pé èyí ni ẹ̀yin ń béèrè fún.” Wọ́n sì lé Mose àti Aaroni kúrò ní iwájú Farao.
Hottelah mahoeh. Hmaloe na hei e patetlah tongpa dueng cet awh nateh BAWIPA Cathut bawk awh, telah atipouh teh ahnimouh teh ama koehoi a pâlei.
12 Ní ìgbà náà ni Olúwa sọ fún Mose, “Gbé ọwọ́ rẹ sókè lórí Ejibiti kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ eṣú bo gbogbo ilẹ̀, kí ó sì ba gbogbo ohun ọ̀gbìn tí ó wà ni inú oko wọn jẹ́, àní gbogbo ohun tí òjò yìnyín kò bàjẹ́ tan.”
BAWIPA ni samtongnaw hah Izip ram dawk a patoun teh roun ni a dêi nawi e talai dawk kaawm rae akungnaw pueng ca sak hanelah, Izip ram lah na kut dâw telah Mosi koe atipouh e patetlah,
13 Nígbà náà ni Mose na ọ̀pá ọwọ́ rẹ̀ sórí ilẹ̀ Ejibiti, Olúwa sì mú kí afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn fẹ́ kọjá lórí ilẹ̀ náà ni gbogbo ọ̀sán àti ni gbogbo òru ni ọjọ́ náà. Ní òwúrọ̀ afẹ́fẹ́ náà ti gbá ọ̀pọ̀lọpọ̀ eṣú wá;
Mosi ni a sonron hah Izip ram lathueng vah a dâw teh, hote kanîruirui, karum tuettuet Kanîtholah hoi BAWIPA ni kahlî a tho sak teh, amom torei teh Kanîtholae kahlî ni samtongnaw hah a thokhai.
14 wọ́n sì bo gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, wọ́n wà ní ibi gbogbo ní orí ilẹ̀ ní àìmoye, ṣáájú àkókò yìí kò sí irú ìyọnu eṣú bẹ́ẹ̀ rí, kò sì ní sí irú rẹ mọ́ lẹ́yìn èyí.
Hote samtong ni Izip ram pueng muen a ramuk teh ramrinaw pueng dawk a kâhat awh teh moiapap awh. Hote samtongnaw teh ayan hoi atu totouh awm boihoeh. Ao hnukkhu hai bout awm mahoeh.
15 Wọ́n bo gbogbo ilẹ̀ tí ilẹ̀ fi di dúdú. Wọ́n ba gbogbo ohun tókù ní orí ilẹ̀ lẹ́yìn òjò yìnyín jẹ́; gbogbo ohun ọ̀gbìn tí ó wà ní inú oko àti gbogbo èso tí ó wà lórí igi. Kò sí ewé tí ó kù lórí igi tàbí lórí ohun ọ̀gbìn ní gbogbo ilẹ̀ Ejibiti.
Talai pueng muen ka tamang lah a ramuk teh ram pueng dawk e phovai kaawm pueng, roun ni a dêi nawi e a paw kaawm e naw pueng a ca dawkvah, Izip ram pueng dawk kaawm e thingkung phokungnaw dawk kahring e banghai awm hoeh.
16 Farao yára ránṣẹ́ pe Mose àti Aaroni, ó sì sọ fún wọn pé, “Èmi ti ṣẹ̀ sí Olúwa Ọlọ́run yín àti sí i yín pẹ̀lú.
Hat toteh, Faro siangpahrang ni Mosi hoi Aron hah karanglah a kaw teh, nangmae Cathut Jehovah koe thoseh, nangmouh koe thoseh ka yon toe.
17 Nísinsin yìí ẹ dáríjì mi lẹ́ẹ̀kan sí i kí ẹ sì gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run yín kí ó lè mú ìpọ́njú yìí kúrò ní ọ̀dọ̀ mi.”
Hatdawkvah, atu vai touh ka yonnae ngaithoum ei. Nangmae BAWIPA Cathut ni het duenae lacik buet touh dueng kai koehoi takhoe hanelah na kâ pouh ei, atipouh e patetlah,
18 Nígbà náà ni Mose kúrò ní iwájú Farao ó sì gbàdúrà sí Olúwa.
Mosi ni ahni koehoi a cei teh BAWIPA koe ngaithoumnae a hei.
19 Olúwa sì yí afẹ́fẹ́ náà padà di afẹ́fẹ́ líle láti apá ìwọ̀-oòrùn wá láti gbá àwọn eṣú náà kúrò ní orí ilẹ̀ Ejibiti lọ sínú Òkun Pupa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹyọ eṣú kan kò ṣẹ́kù sí orí ilẹ̀ Ejibiti.
BAWIPA ni a tha kaawm e kanîloumlae kahlî a patoun teh, hote kahlî ni samtongnaw hah a tawm teh thipaling talî dawk a pabo. Izip ram dawk samtong buet touh boehai awm hoeh.
20 Síbẹ̀ Olúwa ṣe àyà Farao le, kò sì jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli lọ.
Hateiteh, BAWIPA ni Faro e a lung bout a pata sak dawkvah, Isarel canaw tâcawt sak laipalah bout ao.
21 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Gbé ọwọ́ rẹ sókè sí ojú ọ̀run kí òkùnkùn bá à le bo gbogbo ilẹ̀ Ejibiti; àní òkùnkùn biribiri.”
Hahoi, BAWIPA ni Izip ram dawk rumram e hmonae tho laipalah thupthup payam e hmonae o sak hanelah na kut kahlun lah dâw haw telah Mosi koe a dei pouh e patetlah,
22 Nígbà náà ni Mose gbé ọwọ́ rẹ sókè sí ojú ọ̀run, òkùnkùn biribiri sì bo gbogbo ilẹ̀ Ejibiti fún ọjọ́ mẹ́ta. Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli ní ìmọ́lẹ̀ ní ibi tí wọn ń gbé.
Mosi ni a kut kahlun lah a dâw navah Izip ram pueng dawk kingkahmawt e hmonae hnin thum touh ao sak.
23 Kò sí ẹni tí ó le è ríran rí ẹlòmíràn tàbí kí ó kúrò ní ibi tí ó wà fún ọjọ́ mẹ́ta. Síbẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli ni ìmọ́lẹ̀ ni gbogbo ibi tí wọ́n ń gbé.
Hat navah, buet touh hoi buet touh hai kahmawt awh hoeh. Hnin thum touh thung apihaiyah a onae hmuen koehoi thaw awh hoeh. Hatei, Isarelnaw teh a onae hmuen koe angnae a hmu awh.
24 Farao sì ránṣẹ́ pe Mose ó sì wí fún un pé, “Lọ sin Olúwa, kódà àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé lè lọ pẹ̀lú yín, ṣùgbọ́n kí ìwọ kí ó fi agbo àgùntàn àti agbo màlúù yín sílẹ̀.”
Hat navah, Faro siangpahrang ni Mosi hoi Aron a kaw teh BAWIPA bawk hanelah tâcawt awh leih. Hatei, camonaw hrawi awh nateh tu, maitonaw teh cettakhai awh naseh, telah atipouh.
25 Ṣùgbọ́n Mose sọ pé, “Ìwọ gbọdọ̀ fún wa láààyè láti rú ẹbọ àti ọrẹ ẹbọ sísun ní iwájú Olúwa Ọlọ́run wa.
Mosi ni hottelah boipawiteh, ka Cathut Jehovah ka thueng awh nahanelah satheinaw, hmaisawi thueng han hnopainaw hah nang ni poe hanelah a ngai han.
26 Àwọn ohun ọ̀sìn wa gbọdọ̀ lọ pẹ̀lú wa, a kì yóò fi pátákò ẹsẹ̀ ẹran sílẹ̀. A ní láti lò lára wọn fún sínsin Olúwa Ọlọ́run wa, ìgbà tí a bá sì dé ibẹ̀ ni a ó to mọ̀ ohun ti a ó lò láti fi sin Olúwa.”
Kaimouh ni saringnaw hah ka hrawi awh han. Buet touh boehai ka tat awh mahoeh. Bangkongtetpawiteh, hotnaw thung dawk hoi kaimae Cathut Jehovah thueng nahanelah ka rawi awh han. BAWIPA bangpatet e saring hoi maw ka bawk awh han tie hote hmuen koe a pha awh hoehroukrak ka panuek awh hoeh telah atipouh navah,
27 Ṣùgbọ́n Olúwa sé ọkàn Farao le, kò sì ṣetán láti jẹ́ kí wọn lọ.
BAWIPA ni Faro siangpahrang e a lung bout a pata sak dawkvah Isarelnaw tâcawt sak hoeh.
28 Farao sọ fún Mose pé, “Kúrò ní iwájú mi! Rí i dájú pé o kò wá sí iwájú mi mọ́! Ọjọ́ tí ìwọ bá rí ojú mi ni ìwọ yóò kùú.”
Mosi hanlah kai koehoi tâcawt leih. Ka minhmai bout na hmu hoeh nahanlah kâhruetcuet. Ka minhmai na hmunae hnin nah na due han atipouh.
29 Mose sì dáhùn pé, gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti wí, “Èmi kí yóò wá sí iwájú rẹ mọ́.”
Mosi ni hai na dei e teh ahawi. Na minhmai bout kahmawt mahoeh atipouh.

< Exodus 10 >