< Exodus 1 >
1 Ìwọ̀nyí ni àwọn orúkọ ọmọ Israẹli tí wọ́n bá Jakọbu lọ sí Ejibiti, ẹnìkọ̀ọ̀kan pẹ̀lú ìdílé rẹ̀:
Ya: igobe egefelali ilia da e gilisili Idibidi sogega asi ilia dio da,
2 Reubeni, Simeoni, Lefi àti Juda;
Liubene, Simiane, Lifai, Yuda,
3 Isakari, Sebuluni àti Benjamini;
Isiga, Sebiulane, Bediamini,
4 Dani àti Naftali; Gadi àti Aṣeri.
Da: ne, Na: fadalai, Ga: de amola A: sie.
5 Àwọn ìran Jakọbu sì jẹ́ àádọ́rin ní àpapọ̀; Josẹfu sì ti wà ní Ejibiti.
Ya: igobe egaga fi huluane ilia idi da 70. Egefe Yousefe da Idibidi ganodini esalu.
6 Wàyí o, Josẹfu àti gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀ àti gbogbo ìran náà kú,
Ode da asili, Yousefe amola yolalali da bogoi. Amola eno dunu huluane ili defele lalelegei da bogoi.
7 ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli ń bí sí i, wọ́n ń pọ̀ sí i gidigidi, wọ́n kò sì ní òǹkà tí ó fi jẹ́ pé wọ́n kún ilẹ̀ náà.
Be iligaga fi (Isala: ili fi dunu) da mano bagohame lalelegei. Ilia idi da bagade heda: i amola ilia da gasa fi agoane ba: i. Idibidi soge da Isala: ili dunu amoga nabaiwane ba: i.
8 Nígbà náà ni ọba tuntun mìíràn tí kò mọ Josẹfu jẹ ní ilẹ̀ Ejibiti.
Amalalu, Felou gaheabolo da Idibidi soge ganodini hina bagade esalebe ba: i. E da Yousefe hame dawa: i galu.
9 Ó sọ fún àwọn ènìyàn rẹ̀, “Ẹ wò ó, àwọn ará Israẹli ti pọ̀ ní iye àti agbára jù fún wa.
E da ea fi ilima amane sia: i, “Wali Isala: ili dunu da bagohame amola gasa bagade ba: sa. Ilia da ninima hasalasimu agoai galebe.
10 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a lo ọgbọ́n àlùmọ̀kọ́rọ́yí láti dá wọn lẹ́kun, bí kò ṣe bẹ́ẹ̀ wọn yóò túbọ̀ máa pọ̀ sí i. Bí ogun bá sì bẹ́ sílẹ̀, wọn yóò darapọ̀ mọ́ àwọn ọ̀tá wa, wọn yóò sì da ojú ìjà kọ wá, wọn yóò sì sá àsálà kúrò ní ilẹ̀ yìí.”
Ninima ha lai dunu da ninima doagala: sea, Isala: ili dunu da ninima ha lai dunu gilisisa: besa: le amola Idibidi yolesili hobeasa: besa: le, ninia ili idi amo fonoboma: ne logo hogomu da defea.
11 Nítorí náà, wọ́n yan àwọn ọ̀gá akóniṣiṣẹ́ lé wọn lórí láti máa ni wọ́n lára pẹ̀lú iṣẹ́ àṣekára. Wọ́n sì kọ́ Pitomi àti Ramesesi gẹ́gẹ́ bí ìlú ìṣúra pamọ́ sí fún Farao.
Amaiba: le, Idibidi dunu da gasa fi ouligisu dunu Isala: ili dunu udigili gasa bagade hawa: hamosu hamoma: ne ilima asunasi. Isala: ili dunu da moilai bai bagade aduna amo Bidome amola La: misisi gagui. Amo moilai bai bagade aduna da Felou ea liligi ligisisu agoane ba: i.
12 Ṣùgbọ́n bí a ti ń ni wọ́n lára tó, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń pọ̀ sí i, tí wọ́n sì ń tànkálẹ̀. Nítorí náà, àwọn ará Ejibiti bẹ̀rù nítorí àwọn ará Israẹli.
Idibidi dunu da Isala: ili dunu fi baligili se nabasu i. Be Isala: ili fi da hame fonoboi. Ilia bu baligili heda: i amola Idibidi soge huluane amoga fi bagade ba: i.
13 Àwọn ará Ejibiti sì mú àwọn ọmọ Israẹli sìn ní àsìnpa.
Idibidi dunu da Isala: ili dunuma beda: i galu. Amaiba: le, ilia da Isala: ili dunu se nabima: ne, ilima gasa fi hamone, ili da udigili hawa: hamosu dunu ba: i. Idibidi fi da Isala: ili dunu ilia diasu gaguma: ne amola ifabi hawa: hamoma: ne logei. Ilia da Isala: ili dunuma hamedafa asigisu.
14 Wọ́n mú wọn gbé ìgbé ayé kíkorò nípa iṣẹ́ bíríkì àti àwọn onírúurú iṣẹ́ oko; àwọn ará Ejibiti ń lò wọ́n ní ìlòkulò.
15 Ọba Ejibiti sọ fún àwọn agbẹ̀bí Heberu ti orúkọ wọn ń jẹ́ Ṣifura àti Pua pé,
Amalalu, Idibidi Felou da Sifala amola Bua (amo da mano lasu fidisu uda aduna ela da Hibulu uda fidisu) elama amane sia: i,
16 “Nígbà ti ẹ̀yin bá ń gbẹ̀bí àwọn obìnrin Heberu, tí ẹ sì kíyèsi wọn lórí ìkúnlẹ̀ ìrọbí wọn, bí ó bá jẹ́ ọkùnrin ni ọmọ náà, ẹ pa á; ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ obìnrin, ẹ jẹ́ kí ó wà láààyè.”
“Alia da Hibulu uda ilia mano lalelegesu hou fidisia, mano lai da dunu mano ba: sea, amo fanelegema. Be uda mano ba: sea, mae fanelegema.”
17 Ṣùgbọ́n àwọn agbẹ̀bí bẹ̀rù Ọlọ́run, wọn kò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ọba Ejibiti ti wí fún wọn; wọ́n jẹ́ kí àwọn ọmọkùnrin wà láààyè.
Be mano lasu fidisu uda da Godema dawa: i. Amaiba: le, ela da Felou ea sia: hame nabi. Ela da dunu mano hame fanelegei.
18 Ọba Ejibiti pe àwọn agbẹ̀bí ó sì béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin fi ṣe èyí? Èéṣe tí ẹ̀yin fi dá àwọn ọmọkùnrin si?”
Amaiba: le, Felou da mano lasu fidisu uda ema misa: ne sia: ne, elama amane sia: i, “Alia da abuliba: le agoane hamosala: ? Abuliba: le dunu mano hame fanelegesala: ?”
19 Àwọn agbẹ̀bí náà sì dá Farao lóhùn pé, “Àwọn obìnrin Heberu kò rí bí àwọn obìnrin Ejibiti, wọ́n ní agbára, wọ́n sì ti máa ń bí ọmọ kí àwọn agbẹ̀bí tó dé ọ̀dọ̀ wọn.”
Ela da bu adole i, “Hibulu uda da Idibidi uda defele hame hamosa. Ilia mano da hedolowane lalelegesa. Ania da mae doaga: le, ilia mano da lalelegei dagoi ba: sa.”
20 Nítorí náà Ọlọ́run ṣàánú fún àwọn agbẹ̀bí náà, àwọn ọmọ Israẹli sì ń le sí i, wọ́n sì ń pọ̀ sí i jọjọ.
Mano lasu fidisu uda da Godema beda: iba: le, Gode da ela hahawane ba: i. Gode da elama sosogo fi mano i dagoi. Isala: ili dunu ilia idi da bu bagade heda: i amola ilia gasa bagade fi agoane ba: i.
21 Nítorí pé àwọn agbẹ̀bí bẹ̀rù Ọlọ́run, Ọlọ́run sì fún wọn ni ìdílé tiwọn.
22 Nígbà náà ni Farao pàṣẹ yìí fún gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ pé, “Gbogbo ọmọkùnrin tí a bí ni kí ẹ gbé jù sínú odò Naili, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ọmọbìnrin ni kí ẹ jẹ́ kí wọn ó wà láààyè.”
Amo ba: beba: le, Felou da ea fi dunu huluane ilima hamoma: ne sia: i hamoi dagoi. E amane sia: i, “Dilia Hibulu dunu mano gaheabolo lalelegei ba: sea, amo lale, Naile hano amoga bogoma: ne ha: digima. Uda mano fawane mae fanelelegema.”