< Esther 7 >

1 Ọba àti Hamani sì lọ sí àpèjẹ pẹ̀lú Esteri ayaba,
Ana higeno kini ne'ene Hemanikea kuini a' Esta'ma retro'ma hu'nea ne'za ome nenaku vu'na'e.
2 bí wọ́n sì ṣe ń mu wáìnì ní ọjọ́ kejì yìí, ọba sì tún béèrè pé, “Esteri ayaba, kí ni ẹ̀bẹ̀ rẹ? A ó sì fi fún ọ. Kí ni ìbéèrè rẹ? Bí ó tilẹ̀ jẹ́ ìdajì ìjọba à mi, n ó fi fún ọ.”
Hagi namba 2 zupama krentea ne'zane waini tinema neneno'a, kini ne'mo'a ete mago'ane Estana amanage huno antahige'ne, Kuini a' Estaga nazanku kave'nesifi nasmio? Na'ankuro nantahima kesana zana amne kamigahue. Kegavama hu'noa mopagu'ma nantahigesanke'na amne amu'nompintira refko hugamigahue.
3 Nígbà náà ni ayaba Esteri dáhùn, “Bí èmi bá rí ojúrere rẹ, ìwọ ọba, bí ó bá sì tẹ́ ọláńlá à rẹ lọ́rùn, fún mi ní ẹ̀mí mi, èyí ni ẹ̀bẹ̀ mi. Kí o sì pa àwọn ènìyàn mi mọ́—èyí ni ìbéèrè mi.
Higeno anante kuini a' Esta'a kenona'a huno, kini ne'moka musema hunantenka kavesi nantenunka, kantahigoanki nagri'ene vahe'ni'anena tahe ofrio.
4 Nítorí a ti ta èmi àti àwọn ènìyàn mi fún àwọn tí yóò pa wá run, à ti ṣe ìdájọ́ wa fún pípa àti píparẹ́. Bí a bá tilẹ̀ tà wá bí ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin, ǹ bá dákẹ́, nítorí irú ìpọ́njú bẹ́ẹ̀ kò tó èyí tí à ń yọ ọba lẹ́nu sí.”
Na'ankure nagri'ene vahe'ni'anena ko tahe'za akafri kafro nehu'za tazeri havizama nehu'za tahe vagamaresageta frisuna vahe zamazampi zagore tatre'naze. Hagi kazokzo eri'za vahe'ma tavarenaku'ma hiresina, nagra amanahu kea hu'na kna onkamusine. Hianagi nagri'ene naga'ni'anena mika'a tahe vagareke hu'naze.
5 Ọba Ahaswerusi bi Esteri ayaba léèrè pé, “Ta a ni ẹni náà? Níbo ni ẹni náà wà tí kò bẹ̀rù láti ṣe irú nǹkan bẹ́ẹ̀?”
Higeno kini ne' Serksisi'a kuini a' Estankura amanage hu'ne, Iza e'inahu kea hu'ne? Iga ana nera mani'nea ne'mo e'inahu zana huke hu'ne?
6 Esteri sọ wí pé, “Alátakò àti ọ̀tá náà ni Hamani aláìníláárí yìí.” Nígbà náà ni Hamani wárìrì níwájú ọba àti ayaba.
Higeno Esta'a kenona'a huno, E'i ana kefo avu'ava'ma nehuno ha'ma renerantea nera Hemanikino ama mani'ne. Anage higeno Hemani'a kuini a'mofo avugane, kini ne'mofo avuga tusi agogogu nehuno ahirahiku hu'ne.
7 Ọba sì dìde pẹ̀lú ìbínú, ó fi wáìnì sílẹ̀ ó sì jáde lọ sí àgbàlá ààfin. Ṣùgbọ́n nígbà tí Hamani, ti rí i dájú pé ọba ti pinnu láti pa òun, ó dúró lẹ́yìn láti bẹ Esteri ayaba nítorí ẹ̀mí rẹ̀.
Anage higeno kini ne'mo'a, tusi arimpa ahegeno otino atiramino knagune hozafi vu'ne. E'inama higeno'a, Hemani'a mani'neno kuini a'mo'ma asunku'ma huntesigu amesumesu hu'ne. Na'ankure agrama antahiana, kini ne'mo'ma eme ahe frizanku anara hu'ne.
8 Bí ọba ṣe padà dé láti àgbàlá ààfin wá sí gbọ̀ngàn àsè náà, Hamani ṣubú sórí àga tí Esteri ayaba fẹ̀yìn tì. Ọba sì pariwo pé, “Yóò ha tún tẹ́ ayaba níbí yìí, nínú ilé, ní ojú mi bí?” Ní kété tí ọba sọ ọ̀rọ̀ yìí jáde, wọ́n da aṣọ bo Hamani lójú.
Hagi kini ne'mo'ma knagune hozafinti'ma eno'ma eme keana Hemani'a kuini a'mofo tava'onte agafi mase'za nehigeno eme ke'ne. Hagi anante kini ne'mo'a huno, Ama ne'mo'a navufi kuini a' anteno vase'za nehifi? Anagema nehigeno'a, kini ne'mo'ma vahe'ma ahe frinaku'ma nehigeno'ma nehiaza hu'za eri'za vahe'amo'za ame hu'za Hemani agenopa tavravenu refite'naze.
9 Nígbà náà Harbona ọ̀kan nínú àwọn ìwẹ̀fà tó ń dúró níwájú ọba, sọ wí pé, “Igi tí ó ga tó ìwọ̀n ẹsẹ̀ bàtà marunlélaadọrin ni Hamani ti rì sí ẹ̀gbẹ́ ilé e rẹ̀. Ó ṣe é fún Mordekai, ẹni tí ó sọ̀rọ̀ jáde láti ṣe ìrànlọ́wọ́ fún ọba.” Ọba wí pé, ẹ so ó rọ̀ sórí i rẹ́!
Ana higeno anante kini ne'mofo eri'za ne'ma agonknazama hari'naza ne' Habona'a amanage hu'ne, 22mita hu'nea za'za zafa kuma'afina retrurente'neno, kini ne'mokama kahenaku'ma nehazageno hufore'ma huno kagu'ma vazi'nea ne' Modekaima aheno hanti'niaza retro hunte'ne, huno higeno kini ne'mo'a huno, Hemanina azerita ana zafare ome aheta hantiho.
10 Wọ́n sì so Hamani sórí igi tí ó ti pèsè sílẹ̀ fún Mordekai, ìbínú ọba sì rọ̀.
Hige'za Modekaiama aheno hantinaku'ma Hemani'ma retro'ma hunte'nea zafare ahe'za hanti'naze. Ana hazageno kini ne'mofo arimpa ahe'zamo'a evurami'ne.

< Esther 7 >