< Esther 4 >

1 Nígbà tí Mordekai gbọ́ gbogbo nǹkan tí ó ṣẹlẹ̀, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó wọ aṣọ ọ̀fọ̀, ó sì fi eérú kun ara, ó jáde lọ sí inú ìlú ó kígbe sókè ó sì sọkún kíkorò.
Ie nirendre’ i Mordekay i nanoeñe rezay, le niriate’ i Mordekay o saro’eo, le nisikin-gony naho lavenoke, le niheo añivo’ i rovay, nampipoña-koaike mafaitse.
2 Ṣùgbọ́n ó lọ sí ẹnu-ọ̀nà ọba nìkan, nítorí kò sí ẹnìkan tí ó wọ aṣọ ọ̀fọ̀ tì a gbà láààyè láti wọ ibẹ̀.
Nañavelo pak’ an-dalambeim-panjaka eo re, fa tsy eo ty mimoak’ amy lalambeim-panjakay misikin-gony.
3 Ní gbogbo ìgbèríko tí àṣẹ ikú ọba dé, ọ̀fọ̀ ńlá dé bá àwọn Júù, pẹ̀lú àwẹ̀, ẹkún àti ìpohùnréré ẹkún. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ wà nínú aṣọ ọ̀fọ̀ tí wọ́n fi eérú kúnra.
Aa ndra fifelehañe aia aia ty nandoaha’ i lily naho tsei’ mpanjakaiy, le akore ty habeim-pirovetañe amo nte-Iehodao, reke-lilitse, fangololoihañe naho fangoihoiañe; vaho maro ty niba­bok’ an-gony naho an-davenoke.
4 Nígbà tí àwọn ìránṣẹ́bìnrin àti àwọn ìwẹ̀fà Esteri wá, wọ́n sọ nípa Mordekai fún un, ayaba sì wà nínú ìbànújẹ́ ńlá. Ó fi aṣọ ránṣẹ́ sí i kí ó wọ̀ ọ́ dípò aṣọ ọ̀fọ̀ tí ó wọ̀, ṣùgbọ́n òun kò gbà wọ́n.
Aa le niheo mb’amy Estere mb’eo o mpiatra’eo naho o mpifehe’eo nitalily ama’e. Vata’e nalorè amy zao i mpanjaka-ampelay vaho nampañitrife’e lamba t’i Mordekay, hañafahañe i goni’ey, fe tsy rinambe’e.
5 Nígbà náà ni Esteri pe Hataki, ọ̀kan nínú àwọn ìwẹ̀fà ọba tí a yàn láti máa jíṣẹ́ fún un, ó pàṣẹ fún un pé kí ó béèrè ohun tí ó ń dààmú Mordekai àti ohun tí ó ṣe é.
Tinoka’ i Estere t’i Hatàke amo mpiatram-panjakao, i tinendre hiatrak’ azey le nafantok’ ama’e ty hiheo mb’ amy Mordekay mb’eo haharendreke t’ie inoñe ndra manao akore.
6 Bẹ́ẹ̀ ni Hataki jáde lọ bá Mordekai ní ìta gbangba ìlú níwájú ẹnu-ọ̀nà ọba.
Aa le nimb’amy Mordekay an-dala’ i rovay aolo’ i lalambeim-panjakay mb’eo t’i Hatàke.
7 Mordekai sọ ohun gbogbo tí ó ṣẹlẹ̀ fún un, papọ̀ pẹ̀lú iye owó tí Hamani ti ṣe ìpinnu láti san sínú àpò ìṣúra ọba fún ìparun àwọn Júù.
Le nitalilia’ i Mordekay ze fonga nifetsak’ ama’e naho ty drala do’e nampitamae’ i Hamane hondroha’e amo fañajam-baram-panjakao ty amo nte-Iehoda hamongorañeo.
8 Ó sì tún fún un ní ọ̀kan lára ìwé tí ó gbé jáde fún ìparun wọn, èyí tí a tẹ̀ jáde ní Susa, láti fihan Esteri kí ó sì ṣe àlàyé e rẹ̀ fún un, ó sì sọ fún un pé kí ó bẹ̀ ẹ́ kí ó lọ síwájú ọba láti bẹ̀bẹ̀ fún àánú, kí ó bẹ̀bẹ̀ nítorí àwọn ènìyàn rẹ̀.
Natolo’e aze ka ty dika-mira i taratasin-tsey zinara e Sosane ao hanjamanañe iareoy, hatoro’e amy Estere, hampalangesañe ama’e, hamantohañ’ aze ty homb’ amy mpanjakay, hitoreo fiferenaiñañe, hihalalia’e añatrefa’e eo ondati’eo.
9 Hataki padà ó sì lọ ṣàlàyé fún Esteri ohun tí Mordekai sọ.
Aa le nimpoly mb’eo t’i Hatàke nitalily amy Estere i enta’ i Mordekaiy.
10 Nígbà náà ni Esteri pàṣẹ fún Hataki pé kí ó sọ fún Mordekai,
Le nisaontsie’ i Estere amy Hatàke ty hañitrike o entañe zao amy Mordekay:
11 “Gbogbo àwọn ìjòyè ọba àti àwọn ènìyàn agbègbè ìjọba rẹ̀ mọ̀ wí pé: fún ẹnikẹ́ni ọkùnrin tàbí obìnrin kan tàbí tí ó bá bá ọba sọ̀rọ̀ láìjẹ́ pé a ránṣẹ́ pè é (ọba ti gbé òfin kan kalẹ̀ pé) kíkú ni yóò kú. Ohun kan tí ó le yẹ èyí ni pé, kí ọba na ọ̀pá wúrà rẹ̀ sí i kí ó sì dá ẹ̀mí rẹ sí. Ṣùgbọ́n, ọgbọ̀n ọjọ́ ti kọjá tí a ti pè mí láti lọ sí ọ̀dọ̀ ọba.”
Fohi’ ze hene mpitoro’ i mpanjakay naho ze fonga ondatim-pifeleha’ i mpanjakay, te ndra ia ia, ke lahilahy he rakemba ty miheo mb’amy mpanjakay ankiririsa añate’e ao, ie tsy kinoike, le raik’ avao ty lili’e: havetrake naho tsy itolora’ i mpanjakay i kobaim-bolamenay, hiveloma’e; fe mboe tsy tinoka ho mb’ama’e mb’eo iraho o telo-polo andro zao.
12 Nígbà tí a sọ ọ̀rọ̀ Esteri fún Mordekai,
Natalili’ iareo amy Mordekay i lañona’ i Estere zay.
13 nígbà náà ni Mordekai sọ kí a dá Esteri lóhùn pé, “Má ṣe rò nínú ara rẹ pé nítorí pé ìwọ wà ní ilé ọba ìwọ nìkan là láàrín gbogbo àwọn Júù.
Aa le nahere’ i Mordekay amy Estere ty hoe: Ko mañarahara te ihe añ’anjomba’ i mpanjakay ty hahapolititse mandikoatse ze nte-Iehoda iaby.
14 Nítorí bí ìwọ bá dákẹ́ ní àkókò yìí, ìrànlọ́wọ́ àti ìtúsílẹ̀ fún àwọn Júù yóò dìde láti ibòmíràn, ṣùgbọ́n ìwọ àti àwọn ìdílé baba à rẹ yóò ṣègbé. Ta ni ó mọ̀ wí pé nítorí irú àkókò yìí ni o ṣe wà ní ipò ayaba?”
Aa naho mitsin-drehe henane zao le hiongake an-toetse ila’e ty famotsorañe naho ty fandrombahañe o nte-Iehodào, fe hirotsake irehe naho i anjomban-drae’oy; ia ty mahafohiñe, hera te nitsatok’ amy mahampanjaka azoy t’ie ho añ’andro hoe zao?
15 Nígbà náà ni Esteri rán iṣẹ́ yìí sí Mordekai:
Aa le nampibalike ty hoe amy Mordekay t’i Estere:
16 “Lọ, kí o kó gbogbo àwọn Júù tí ó wà ní Susa jọ, kí ẹ sì gbààwẹ̀ fún mi. Ẹ má ṣe jẹun tàbí omi fún ọjọ́ mẹ́ta, ní òru àti ní ọ̀sán. Èmi àti àwọn ìránṣẹ́bìnrin mi náà yóò gbààwẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin náà ti ṣe. Nígbà tí ẹ bá ṣe èyí, èmi yóò tọ ọba lọ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó lòdì sí òfin. Bí mo bá sì ṣègbé, mo ṣègbé.”
Akia, atontono ze hene nte-Iehodà tendreke e Sosane ao, le mililira ho ahy, ko mikama ndra minoñe telo andro, haleñe naho handro; hililitse manahake Izay ka iraho naho o somondrarakoo; Izay vaho hiheo mb’amy mpanjakay mb’eo, ie tsy milahatse amy liliy; fa naho hikenkan-draho le hikenkañe.
17 Bẹ́ẹ̀ ni Mordekai lọ, ó sì sọ gbogbo ohun tí Esteri pàṣẹ fún un.
Aa le nienga mb’eo t’i Mordekay, nanao ze hene namantoha’ i Estere.

< Esther 4 >