< Ephesians 6 >

1 Ẹ̀yin ọmọ, ẹ máa gbọ́ tí àwọn òbí i yín nínú Olúwa, nítorí pé èyí ní ó tọ́.
Balilar, Rǝbdǝ ata-aniliringlarƣa itaǝt ⱪilinglar; qünki bu durusdur.
2 “Bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ,” èyí tí í ṣe òfin kìn-ín-ní pẹ̀lú ìlérí,
«Atangni wǝ anangni ⱨɵrmǝtlǝ» — bu bolsa ɵz iqigǝ wǝdini alƣan birinqi ǝmrdur —
3 “ki ó lé dára fún ọ, àti kí ìwọ lè wà pẹ́ ní ayé.”
«Xuning bilǝn sening ixliring ⱪutluⱪ bolidu, zeminda uzun ɵmür kɵrisǝn» — [dǝp wǝdǝ ⱪilinƣan].
4 Àti ẹ̀yin baba, ẹ má ṣe mú àwọn ọmọ yín bínú, ṣùgbọ́n ẹ máa tọ́ wọn nínú ẹ̀kọ́ àti ìkìlọ̀ Olúwa.
Silǝr atilar, baliliringlarni hapa ⱪilmanglar, bǝlki ularni Rǝbning tǝrbiyisi ⱨǝm kɵrsǝtmisidǝ beⱪinglar.
5 Ẹ̀yin ọmọ ọ̀dọ̀, ẹ máa gbọ́ ti àwọn olúwa yín nípá ti ara, pẹ̀lú ìbẹ̀rù àti ìwárìrì, nínú òtítọ́ ọkàn yín, bí ẹni pé sí Kristi.
Silǝr ⱪullar, ǝttin bolƣan hojayininglarƣa Mǝsiⱨkǝ itaǝt ⱪilƣininglardǝk qin kɵnglünglardin ǝyminix wǝ titrǝx bilǝn itaǝt ⱪilinglar;
6 Gbọ́ ọ̀rọ̀ sí wọn lẹ́nu kì í ṣe láti rí ojúrere wọn nígbà tí ojú wọn bá ń bẹ lára rẹ, ṣùgbọ́n bí ẹrú Kristi, ní ṣíṣe ìfẹ́ Ọlọ́run láti inú ọkàn rẹ.
pǝⱪǝt kɵz aldidila hizmǝt ⱪilip, adǝmni hux ⱪilƣuqi ⱪullardin bolmanglar, bǝlki Mǝsiⱨning ⱪullirining süpitidǝ Hudaning iradisini jan-dil bilǝn bǝja kǝltürünglar,
7 Ẹ máa fi gbogbo ọkàn yin ṣe iṣẹ́ ìsìn bí sí Olúwa, kì í sí ṣe sí ènìyàn.
adǝmlǝrgǝ ǝmǝs, bǝlki Rǝbgǝ qin dilinglardin hizmǝt ⱪilinglar;
8 Bí ẹ̀yin ti mọ̀ pé ohun rere tí olúkúlùkù bá ṣe òun náà ní yóò sí gbà padà lọ́dọ̀ Olúwa, ìbá à ṣe ẹrú, tàbí òmìnira.
xuni bilgǝnki, ⱨǝrⱪandaⱪ adǝm birǝr yahxiliⱪ ⱪilsa, mǝyli u ⱪul bolsun yaki ⱨɵr bolsun, xu ix Rǝbdin uningƣa yanidu.
9 Àti ẹ̀yin ọ̀gá, ẹ máa ṣe irú ìtọ́jú kan náà sí àwọn ẹrú yin, ẹ máa dín ìbẹ̀rù yín kù bí ẹ̀yin ti mọ̀ pé Olúwa ẹ̀yin tìkára yín ń bẹ ní ọ̀run; kò sì ṣí ojúsàájú ènìyàn lọ́dọ̀ rẹ̀.
Silǝr hojayinlar, ⱪulliringlarƣimu ohxax yol bilǝn muamilǝ ⱪilip, ularƣa ⱨǝywǝ ⱪilixtin ⱪol üzünglar; qünki ularningmu wǝ silǝrningmu hojayininglar ǝrxtidur, Uningda ⱨǝrⱪandaⱪ adǝmning yüz-hatirisini ⱪilix degǝnning yoⱪluⱪini bilisilǝr.
10 Ní àkótán, ara mí, ẹ jẹ́ alágbára nínú Olúwa, àti nínú agbára ipá rẹ̀.
Ahirda, ⱪerindaxlar, Rǝbdǝ wǝ Uning küq-ⱪudritidǝ küqlǝndürlünglar;
11 Ẹ gbé gbogbo ìhámọ́ra Ọlọ́run wọ̀, kí ẹ̀yin lè kọ ojú ìjà sí àrékérekè èṣù.
Iblisning ⱨiylǝ-nǝyrǝnglirigǝ taⱪabil turuxunglar üqün Hudaning pütkül sawut-yariƣini kiyiwelinglar;
12 Nítorí pé kì í ṣe ẹ̀jẹ̀ àti ẹran-ara ní àwa ń bá jìjàkadì, ṣùgbọ́n àwọn ìjòyè, àwọn ọlọ́lá, àwọn aláṣẹ ìbí òkùnkùn ayé yìí, àti àwọn ẹ̀mí búburú ní ojú ọ̀run. (aiōn g165)
qünki elixidiƣinimiz ǝt wǝ ⱪan igiliri ǝmǝs, bǝlki ⱨɵkümranlar, ⱨoⱪuⱪdarlar, bu dunyadiki ⱪarangƣuluⱪni baxⱪurƣuqi dunyawi ǝmirlǝr, yǝni ǝrxlǝrdǝ turuwatⱪan rǝzil roⱨiy küqlǝrdur. (aiōn g165)
13 Nítorí náà, ẹ gbé gbogbo ìhámọ́ra Ọlọ́run wọ̀, kí ẹ̀yin lè dúró tiiri sí ọjọ́ ibi, nígbà tí ẹ̀yin bá sì ti ṣe ohun gbogbo tan kí ẹ sì dúró.
Muxu wǝjidin ɵzünglarƣa Hudaning pütün sawut-yariⱪini elip artinglarki, rǝzillik künidǝ bǝrdaxliⱪ bilǝn ⱪattiⱪ turidiƣan, ahir ⱨǝmmǝ ixni ada ⱪilip, yǝrni qing dǝssǝp turidiƣan bolisilǝr.
14 Ẹ dúró nítorí náà lẹ́yìn tí ẹ fi àmùrè òtítọ́ dì ẹ̀gbẹ́ yin, tí ẹ sì ti di ìgbàyà òdodo mọ́ra.
Əmdi qing turunglar — ⱨǝⱪiⱪǝt bǝlweƣini belinglarƣa baƣlap, mǝydǝnglǝrgǝ ⱨǝⱪⱪaniyliⱪ sawutini kiyip, putunglarƣa hatirjǝm-inaⱪliⱪ hux hǝwirini yǝtküzüxkǝ tǝyyarliⱪ qoruⱪini kiyip, yǝrni qing dǝssǝp turunglar.
15 Tí ẹ sì ti fi ìmúra ìyìnrere àlàáfíà wọ ẹsẹ̀ yín ní bàtà.
16 Ní àfikún, ẹ mú àpáta ìgbàgbọ́, nípa èyí tí ẹ̀yin lè máa fi paná gbogbo ọfà iná ẹni ibi náà.
Bu ixlarning ⱨǝmmisidǝ iman-ixǝnqning ⱪalⱪinini ⱪolƣa elinglar; uning bilǝn silǝr rǝzil bolƣuqining barliⱪ ot oⱪlirini ɵqüriwetǝlǝydiƣan bolisilǝr.
17 Kí ẹ sì mú àṣíborí ìgbàlà, àti idà ẹ̀mí, tí í ṣe ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.
Ⱨǝmdǝ bexinglarƣa nijatning dubulƣisini kiyip, Hudaning sɵz-kalamini, yǝni Roⱨning ⱪiliqini elinglar;
18 Pẹ̀lú gbogbo àdúrà àti ẹ̀bẹ̀ ni kí ẹ máa gbàdúrà nígbà gbogbo nínú Ẹ̀mí, kí ẹ sì máa ṣọ́ra sí i nínú ìdúró ṣinṣin gbogbo àti ẹ̀bẹ̀ fún gbogbo ènìyàn mímọ́.
ⱨǝmmǝ waⱪit-pǝsildǝ Roⱨta ⱨǝrhil dua-tilawǝt ⱨǝm iltija bilǝn dua ⱪilinglar; dǝl bu ixta ⱪǝt’iy ⱨoxyar turup barliⱪ muⱪǝddǝs bǝndilǝr üqün ⱨǝr tǝrǝplimǝ dua-iltijalar ⱪilinglar;
19 Kí ẹ sì máa gbàdúrà fún mí pẹ̀lú, kí Ọlọ́run lè fún mí ní ọ̀rọ̀ tí ó yẹ kí èmi lè máa fì ìgboyà sọ àwọn ohun ìjìnlẹ̀ ìyìnrere náà.
mǝn üqünmu dua ⱪilinglarki, — eƣiz aqⱪinimda manga sɵzlǝr kǝlsun, hux hǝwǝrning sirini dadilliⱪ bilǝn axkarǝ ⱪilay.
20 Nítorí èyí tí èmí jẹ́ ikọ̀ nínú ẹ̀wọ̀n, kí èmi lè máa fi ìgboyà sọ̀rọ̀ nínú rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ó ti tọ́ fún mí láti máa sọ.
Mǝn dǝl xu ixⱪa zǝnjirlǝr bilǝn baƣlanƣan ǝlqimǝn; xunga ⱪilixⱪa tegixlikim boyiqǝ, [hux hǝwǝr yǝtküzüxtǝ] dadilliⱪ bilǝn sɵz ⱪiliximƣa [dua ⱪilinglar].
21 Tikiku, arákùnrin olùfẹ́ àti ìránṣẹ́ olóòtítọ́ nínú Olúwa yóò sọ ohun gbogbo dí mí mọ̀ fún yín, kí ẹ̀yin pẹ̀lú lè mọ̀ bí nǹkan ti rí fún mí àti bí mo tí ń ṣe sí.
Əmdi mening toƣramdiki ixlardin, mening ⱪandaⱪ ɵtüwatⱪanliⱪimdin hǝwǝrlinixinglar üqün, sɵyümlük ⱪerindax ⱨǝm Rǝbdǝ sadiⱪ hizmǝtkar bolƣan Tikikus silǝrgǝ ⱨǝmmǝ ixlarni mǝlum ⱪilidu.
22 Ẹni tí mo rán sí yín nítorí èyí náà, kí ẹ lè mọ̀ bí a tí wà, kì òun lè tu ọkàn yín nínú.
Mening uni dǝl muxu ix üqün yeninglarƣa ǝwǝtixim, silǝrning ixlirimizdin hǝwǝrdar boluxinglar wǝ uning kɵnglünglarƣa tǝsǝlli wǝ ilⱨam berixi üqündur.
23 Àlàáfíà fún àwọn ará, àti ìfẹ́ pẹ̀lú ìgbàgbọ́, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wà, àti Olúwa wà Jesu Kristi.
Ⱪerindaxlarƣa hatirjǝmlik, muⱨǝbbǝt ⱨǝm iman-ixǝnq Huda’Ata wǝ Rǝb Əysa Mǝsiⱨdin bolƣay!
24 Kí oore-ọ̀fẹ́ wà pẹ̀lú gbogbo àwọn tí ó fẹ́ Olúwa wa Jesu Kristi ni àìṣẹ̀tàn.
Rǝb Əysa Mǝsiⱨni ɵlmǝs-qirimas sɵygü bilǝn sɵygüqilǝrgǝ meⱨir-xǝpⱪǝt yar bolƣay!

< Ephesians 6 >