< Ephesians 6 >

1 Ẹ̀yin ọmọ, ẹ máa gbọ́ tí àwọn òbí i yín nínú Olúwa, nítorí pé èyí ní ó tọ́.
Imrli, wotre batiembi wa batie ni mi Rjia, ahi kpe u bi.
2 “Bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ,” èyí tí í ṣe òfin kìn-ín-ní pẹ̀lú ìlérí,
To tie mbi ni yi mbi ni nfutu ahi njitre u mumlan ni alkawali.
3 “ki ó lé dára fún ọ, àti kí ìwọ lè wà pẹ́ ní ayé.”
ndu yi kpa lulu, ndi tie se gbugbuu ni mgbu mgblu yi
4 Àti ẹ̀yin baba, ẹ má ṣe mú àwọn ọmọ yín bínú, ṣùgbọ́n ẹ máa tọ́ wọn nínú ẹ̀kọ́ àti ìkìlọ̀ Olúwa.
Nakima me, Batie, na tie kpe wa ani kpa sron mrlimbi tir memea na, tsro ba kon ndi ndi ni mitre Baci.
5 Ẹ̀yin ọmọ ọ̀dọ̀, ẹ máa gbọ́ ti àwọn olúwa yín nípá ti ara, pẹ̀lú ìbẹ̀rù àti ìwárìrì, nínú òtítọ́ ọkàn yín, bí ẹni pé sí Kristi.
Igran, wo tre batie ko mbi u mgbumgbluyi ndi klu sissri mba ni mi dri mbi, wo tre mba nawa bi wo u' kristia.
6 Gbọ́ ọ̀rọ̀ sí wọn lẹ́nu kì í ṣe láti rí ojúrere wọn nígbà tí ojú wọn bá ń bẹ lára rẹ, ṣùgbọ́n bí ẹrú Kristi, ní ṣíṣe ìfẹ́ Ọlọ́run láti inú ọkàn rẹ.
Na tir kpe ndi ndi ni shishi ba tre ko mbi ni ndu ba gbre yi san na tie na bi gran kristi tie kpe wa Rji ni son'a rji nimi dri mbi.
7 Ẹ máa fi gbogbo ọkàn yin ṣe iṣẹ́ ìsìn bí sí Olúwa, kì í sí ṣe sí ènìyàn.
Tiendu ni sron me wawuu, na wu tie ni Baci, ana ni ndji na.
8 Bí ẹ̀yin ti mọ̀ pé ohun rere tí olúkúlùkù bá ṣe òun náà ní yóò sí gbà padà lọ́dọ̀ Olúwa, ìbá à ṣe ẹrú, tàbí òmìnira.
Ki to ndi kpe ndindi wa ndji ba tiea ba kpalulu ni Baci, I gran ko ndji wa ba cuwu cuwoa.
9 Àti ẹ̀yin ọ̀gá, ẹ máa ṣe irú ìtọ́jú kan náà sí àwọn ẹrú yin, ẹ máa dín ìbẹ̀rù yín kù bí ẹ̀yin ti mọ̀ pé Olúwa ẹ̀yin tìkára yín ń bẹ ní ọ̀run; kò sì ṣí ojúsàájú ènìyàn lọ́dọ̀ rẹ̀.
Na kima, i ttieko, tie ni gran na kima me na nuba sissri na. Irji mba ni u mbia he ni shu. ana tie sontuwa
10 Ní àkótán, ara mí, ẹ jẹ́ alágbára nínú Olúwa, àti nínú agbára ipá rẹ̀.
I clema, tie mgbe mgble ni mi Baci.
11 Ẹ gbé gbogbo ìhámọ́ra Ọlọ́run wọ̀, kí ẹ̀yin lè kọ ojú ìjà sí àrékérekè èṣù.
Sru kpe ku u Rji, ndi ndu zayi krli ni kagji u shetan.
12 Nítorí pé kì í ṣe ẹ̀jẹ̀ àti ẹran-ara ní àwa ń bá jìjàkadì, ṣùgbọ́n àwọn ìjòyè, àwọn ọlọ́lá, àwọn aláṣẹ ìbí òkùnkùn ayé yìí, àti àwọn ẹ̀mí búburú ní ojú ọ̀run. (aiōn g165)
Iku mbua na he u nama ni yi na, ama ahi mgbemgble, ni mahukunta u mgbumgblu yi ubwu ni rudunai bi bwu u memme ni mi shu gbugbuu. (aiōn g165)
13 Nítorí náà, ẹ gbé gbogbo ìhámọ́ra Ọlọ́run wọ̀, kí ẹ̀yin lè dúró tiiri sí ọjọ́ ibi, nígbà tí ẹ̀yin bá sì ti ṣe ohun gbogbo tan kí ẹ sì dúró.
Naki ban kpe ku u Rji, don ni krli mgbanmgban ni memme vi. Bita tie koge bi krli ni mgbemgble.
14 Ẹ dúró nítorí náà lẹ́yìn tí ẹ fi àmùrè òtítọ́ dì ẹ̀gbẹ́ yin, tí ẹ sì ti di ìgbàyà òdodo mọ́ra.
Krli mgban mgban, ndi lo rji rji ni tri mbi, ndi sru damgban u tsratsra.
15 Tí ẹ sì ti fi ìmúra ìyìnrere àlàáfíà wọ ẹsẹ̀ yín ní bàtà.
Tie nayi ndi lo za mbi mgbamgban ndi ji tre rji u si sron hi.
16 Ní àfikún, ẹ mú àpáta ìgbàgbọ́, nípa èyí tí ẹ̀yin lè máa fi paná gbogbo ọfà iná ẹni ibi náà.
Ni me kpe wawuu, ban dagban u yosron, wawumbi wu i whien bi memme.
17 Kí ẹ sì mú àṣíborí ìgbàlà, àti idà ẹ̀mí, tí í ṣe ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.
Ndi ban tagya u gbujbu ni njigban u brji tsratsra, wa a hi tre Rjia.
18 Pẹ̀lú gbogbo àdúrà àti ẹ̀bẹ̀ ni kí ẹ máa gbàdúrà nígbà gbogbo nínú Ẹ̀mí, kí ẹ sì máa ṣọ́ra sí i nínú ìdúró ṣinṣin gbogbo àti ẹ̀bẹ̀ fún gbogbo ènìyàn mímọ́.
Ni bre mbi wawuu, ta tre ni baci cacuu nimi tsratsra. Ni cleama, taya ni yosron nita tre ni baci nitu ndi bi hu wawuu.
19 Kí ẹ sì máa gbàdúrà fún mí pẹ̀lú, kí Ọlọ́run lè fún mí ní ọ̀rọ̀ tí ó yẹ kí èmi lè máa fì ìgboyà sọ àwọn ohun ìjìnlẹ̀ ìyìnrere náà.
Bre nimu ndu me kpa tori ni ton wa mi bwu yyua. Bre nimu ndume fe sron wa mi hla tre jaji wa baria.
20 Nítorí èyí tí èmí jẹ́ ikọ̀ nínú ẹ̀wọ̀n, kí èmi lè máa fi ìgboyà sọ̀rọ̀ nínú rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ó ti tọ́ fún mí láti máa sọ.
Nitu bishara mi kati ndi u tondu wa baya, zie ni mi zrea, ndi dume tre hamma ni glu sissiri.
21 Tikiku, arákùnrin olùfẹ́ àti ìránṣẹ́ olóòtítọ́ nínú Olúwa yóò sọ ohun gbogbo dí mí mọ̀ fún yín, kí ẹ̀yin pẹ̀lú lè mọ̀ bí nǹkan ti rí fún mí àti bí mo tí ń ṣe sí.
Tikikus, vayimu wa misonwu kpu kpome, ndi kpau y'me a hi gran nimi Baci, ani hla ni yuwuu wawuu.
22 Ẹni tí mo rán sí yín nítorí èyí náà, kí ẹ lè mọ̀ bí a tí wà, kì òun lè tu ọkàn yín nínú.
Nitu kimayi miton wu ye niyi ni ndu yito kpe wa ki he nimiandi ndu yi fe si ni sron bi.
23 Àlàáfíà fún àwọn ará, àti ìfẹ́ pẹ̀lú ìgbàgbọ́, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wà, àti Olúwa wà Jesu Kristi.
Ndu si he ni mrli, ison ni yosron ni Rji tie ni Baci Yesu Almasihu.
24 Kí oore-ọ̀fẹ́ wà pẹ̀lú gbogbo àwọn tí ó fẹ́ Olúwa wa Jesu Kristi ni àìṣẹ̀tàn.
Ndu si he ni biwa ba son Baci mbu Yesu Almasihu ni son u kakle.

< Ephesians 6 >