< Ecclesiastes 12 >
1 Rántí Ẹlẹ́dàá rẹ ní ọjọ́ èwe rẹ, nígbà tí ọjọ́ ibi kò tí ì dé àti tí ọdún kò tí ì ní súnmọ́ etílé, nígbà tí ìwọ yóò wí pé, “Èmi kò ní ìdùnnú nínú wọn,”
Amaiba: le, dilia da goi gogawane, dili Hahamosu Dunu dawa: ma. Fa: no da: i dioi eso da dilima doaga: mu. Amo ganodini dilia da, “Na esalusu ganodini, na da hahawane hame gala,” amane sia: mu.
2 kí oòrùn àti ìmọ́lẹ̀ àti òṣùpá àti àwọn ìràwọ̀ tó ṣókùnkùn, àti kí àwọsánmọ̀ tó padà lẹ́yìn òjò;
Amo esoha eso amola oubi amola gasumuni ilia hadigi amo di da gasi hahamoi agoane ba: mu, amola eso huluane gibu mobi da dialumu.
3 nígbà tí olùṣọ́ ilé yóò wárìrì tí àwọn ọkùnrin alágbára yóò tẹríba, nígbà tí àwọn tí ó ń lọ dákẹ́ nítorí pé wọn kò pọ̀, tí àwọn tí ń wo òde láti ojú fèrèsé yóò ṣókùnkùn;
Amasea, dia lobo (amo da di gaga: i dialu) da yagugumu amola dia emo waha gasa galebe, da goayamu. Dia bese oda da duduga: iba: le, dia ha: i manu agimu gogolemu amola dia si da uliligiba: le, noga: le ba: mu gogolemu.
4 nígbà tí ìlẹ̀kùn sí ìgboro yóò tì tí ariwo ọlọ yóò dákẹ́; nígbà tí àwọn ènìyàn yóò dìde sí ariwo àwọn ẹyẹ ṣùgbọ́n gbogbo orin wọn yóò máa lọ ilẹ̀.
Dia ge da ga: i dagoiba: le, logoba: le ga: da hame nabimu. Di da gagoma goudasu ea ga: amola baidama dubi amo fonobahadi fawane nabimu. Be sio ea gesami hea: su amoga fawane da dia golabe didilisimu.
5 Nígbà tí ènìyàn yóò bẹ̀rù ibi gíga àti ti ìfarapa ní ìgboro; nígbà tí igi almondi yóò tanná àti tí ẹlẹ́ǹgà yóò wọ́ ara rẹ̀ lọ tí ìfẹ́ kò sì ní ru sókè mọ́ nígbà náà ni ènìyàn yóò lọ ilé rẹ́ ayérayé tí àwọn aṣọ̀fọ̀ yóò máa rìn kiri ìgboro.
Di da gadodafa sogebi amoga masa: ne beda: mu, amola dia ahoabe da se nabasa: besa: le, beda: mu. Dia dialuma hinabo da gago aligimu. Di da gasa fili masunu gogolemu amola dia hanai dawa: su da asi dagoi ba: mu. Ninia da esalebe dagomusa: helefisu amoga ahoa, amola ninia bogosea, dunu da logoga heawini dinanebe ba: mu.
6 Rántí rẹ̀ kí okùn fàdákà tó já, tàbí kí ọpọ́n wúrà tó fọ́; kí iṣà tó fọ́ níbi ìsun, tàbí kí àyíká kẹ̀kẹ́ kí ó tó kán níbi kànga.
Silifa sia: ine da damui dagoi ba: mu. Gouliga hamoi gamali da hanega: ne sa: ili, goudamu. Hano nasu ulidou ea hano disu efe da damuni gala: mu amola hano disu ofodo da goudamu.
7 Tí erùpẹ̀ yóò sì padà sí ilẹ̀ ibi tí ó ti wà, tí ẹ̀mí yóò sì padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run tí ó fi í fún ni.
Ninia da: i da osobo guluga buhagimu. Amola ninia mifo amo Gode da ninma i, amo da Hima buhagimu.
8 “Asán! Asán!” ni Oniwaasu wí. “Gbogbo rẹ̀ asán ni!”
Sia: Dabe Alofele Iasu Dunu da amane sia: i, “Hamedei! Hamedei! Huluanedafa da hamedei!”
9 Kì í ṣe wí pé Oniwaasu jẹ́ ọlọ́gbọ́n nìkan, ṣùgbọ́n ó tún kọ́ àwọn ènìyàn ní ìmọ̀. Ó rò ó dáradára ó sì ṣe àwárí, ó sì gbé ọ̀pọ̀lọpọ̀ òwe kalẹ̀ lẹ́sẹẹsẹ.
Be Sia: Dabe Alofele Iasu Dunu da dawa: bagade lai dagoiba: le, e da gebewane dunu oda ilima ea dawa: hou olelelalu. E da malasu dedei ilia bai hogolalu, ilia hou ba: le dawa: musa: adoba: i.
10 Oniwaasu wádìí láti rí àwọn ọ̀rọ̀ tí ó tọ̀nà, ohun tí ó kọ sì dúró ṣinṣin ó sì jẹ́ òtítọ́.
E da eno dunu dogo denesima: ne sia: hogoi helei. Be e da sia: moloidafa fawane dedei.
11 Ọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n dàbí ẹ̀gún, àkójọpọ̀ ọ̀rọ̀ wọn sì dàbí ìṣó tí a kàn pọ̀ dáradára, tí olùṣọ́-àgùntàn kan fi fún ni.
Bagade dawa: su dunu ilia fada: i sia: da galiamo debei amoga sibi ouligisu dunu da ilia sibi sesu, agoaiwane gala. Amola malasu gilisi da mae mugululi, gafesi noga: le dabagala: i defele agoane ba: mu. Gode da ninia Sibi Ouligisudafa afadafa fawane esala. Amola E da amo malasu ninima i dagoi.
12 Àti síwájú láti inú èyí, ọmọ mi, gba ìmọ̀ràn. Nínú ìwé púpọ̀, òpin kò sí, ìwé kíkà púpọ̀ a máa mú ara ṣàárẹ̀.
Nagofe! Liligi eno amo di noga: le dawa: digima: ne diala. Buga dedesu dagomu dibi da hamedafa. Amola di da baligili dawa: bagade lamusa: hamosea, hele bagade nabimu.
13 Nísinsin yìí, òpin gbogbo ọ̀rọ̀ tí a gbọ́ ni pé, bẹ̀rù Ọlọ́run, kí o sì pa òfin rẹ̀ mọ́, nítorí èyí ni ojúṣe gbogbo ènìyàn.
Wali, sia: huluane da sia: i dagoi. Be sia: dagomusa: , sia: afadafa fawane gala, amane. “Godeba: le beda: ma! Ea hamoma: ne sia: i nabawane hamoma! Bai amo hou hamoma: ne, Gode da dunu fi hahamoi dagoi.
14 Nítorí Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ olúkúlùkù iṣẹ́ àti ohun ìkọ̀kọ̀, kì bá à ṣe rere kì bá à ṣe búburú.
Gode da ninia hamoi, noga: i o wadela: i, amo huluane amoma fofada: mu. Siga ba: i hou amola wamo hamoi hou, amo huluanema, E da fofada: mu.” Sia: ama dagoi