< Deuteronomy 8 >

1 Ẹ kíyèsi i láti máa tẹ̀lé gbogbo àṣẹ tí mo fún un yín lónìí, kí ẹ bá à le yè, kí ẹ sì pọ̀ sí i wọ ilẹ̀ náà, kí ẹ sì le gba ilẹ̀ náà, tí Olúwa fì búra ṣèlérí fún àwọn baba ńlá a yín.
Kia mahara kia mahia nga whakahau katoa e whakahaua nei e ahau i tenei ra, kia ora ai koutou, kia tini ai, kia tae ai hoki, kia whiwhi ai ki te whenua i oati ra a Ihowa ki a koutou matua.
2 Ẹ rántí bí Olúwa Ọlọ́run yín ti tọ́ ọ yín ṣọ́nà ní gbogbo ọ̀nà ní aginjù fún ogójì ọdún wọ̀nyí láti tẹ orí yín ba àti láti dán an yín wò kí ó ba à le mọ bí ọkàn yín ti rí, bóyá ẹ ó pa òfin rẹ̀ mọ́ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Kia mahara hoki ki te ara katoa i arahi ai a Ihowa, tou Atua, i a koe i te koraha, i enei tau e wha tekau, kia iro ai koe, hei whakamatautau hoki i a koe, kia mohiotia ai nga aha noa i roto i tou ngakau, ka pupuri ranei koe i ana whakahau, kahore ranei.
3 Ó rẹ̀ yín sílẹ̀ nípa fífi ebi pa yín, Ó sì fi manna bọ́ ọ yín, èyí tí ẹ kò mọ̀, tí àwọn baba yín kò mọ̀, kí ó ba à lè kọ́ ọ yín pé, ènìyàn kò ti ipa oúnjẹ nìkan wà láààyè, bí kò ṣe ohun gbogbo tí ó jáde láti ẹnu Olúwa wá.
A whakawhiua ana koe e ia, whakamatea ana ki te kai, whangaia ana ki te mana, kihai nei i mohiotia e koe, kihai ano i mohiotia e ou matua; kia whakamohio ai ia i a koe e kore te tangata e ora i te taro kau, engari ma nga kupu katoa e puta mai ana i te mangai o Ihowa ka ora ai te tangata.
4 Aṣọ yín kò gbó mọ́ ọn yín lọ́rùn bẹ́ẹ̀ ní ẹsẹ̀ yín kò sì wú, ní ogójì ọdún náà.
Kihai tou kakahu i tawhitotia ki runga ki a koe, kihai ano hoki tou waewae i pupuhi, i enei tau e wha tekau.
5 Ẹ mọ̀ ní ọkàn an yín pé, bí baba ti ń kọ́ ọmọ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni Olúwa Ọlọ́run yín ń kọ́ ọ yín.
A ka mahara koe i roto i tou ngakau, e papaki ana a Ihowa, tou Atua i a koe, e pera ana me te tangata e papaki ana i tana tama.
6 Nítorí èyí, ẹ gbọdọ̀ pa òfin Olúwa Ọlọ́run yín mọ́, nípa rínrìn ní ọ̀nà rẹ̀, àti bíbẹ̀rù rẹ̀.
Na kia mau ki nga whakahau a Ihowa, a tou Atua, haere hoki i ana huarahi me te wehi ano ki a ia.
7 Nítorí pé Olúwa Ọlọ́run yín ń mú un yín bọ̀ wá sí ilẹ̀ rere ilẹ̀ tí ó kún fún odò àti ibú omi, pẹ̀lú àwọn ìsun tí ń sàn jáde láti orí òkè àti pẹ̀tẹ́lẹ̀.
Na te mea e kawe ana a Ihowa, tou Atua, i a koe ki te whenua pai, ki te whenua o nga awa wai, o nga puna, o nga wai hohonu, e pupu mai ana i nga raorao, i nga maunga;
8 Ilẹ̀ tí ó kún fún jéró àti ọkà barle, tí ó sì kún fún àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́, igi pomegiranate, òróró olifi àti oyin.
Ki te whenua o te witi, o te parei, o te waina, o te piki, o te pamekaranete: ki te whenua o te hinu oriwa, o te honi;
9 Ilẹ̀ tí oúnjẹ kò ti wọ́n, kò sí ohun tí ẹ̀yin yóò ṣe aláìní, ilẹ̀ tí irin ti pọ̀ bí òkúta, ẹ̀yin sì lè wa idẹ jáde láti inú òkè rẹ̀ wá.
Ki te whenua e kore ai e onge tau taro e kai ai koe, e kore rawa ai koe e hapa i tetahi mea; ki te whenua he rino ona kohatu, ka keri ano koe i te parahi i roto i ona maunga.
10 Nígbà tí ẹ bá ti jẹ tí ẹ sì yó tán ẹ yin Olúwa Ọlọ́run yín fún pípèsè ilẹ̀ rere fún un yín.
A ka kai koe, ka makona, na kia whakapai atu koe ki a Ihowa, ki tou Atua, mo te whenua pai kua homai e ia ki a koe.
11 Ẹ ṣọ́ra kí ẹ má gbàgbé Olúwa Ọlọ́run yín, nípa kíkùnà láti pa àṣẹ rẹ̀, àwọn òfin rẹ̀, àti àwọn ìlànà rẹ̀ tí mo ń fún un yín lónìí mọ́.
Kia tupato kei wareware ki a Ihowa, ki tou Atua, kei kore koe e pupuri i ana whakahau, i ana whakaritenga, i ana tikanga, e whakahaua nei e ahau ki a koe i tenei ra:
12 Kí ó má ba à jẹ́ pé, nígbà tí ẹ bá jẹun yó tán, tí ẹ bá kọ́ ilé tí ó dára tán, tí ẹ sí ń gbé inú rẹ̀,
Kei kai koe, a ka makona, kei hanga hoki i nga whare papai, a noho iho;
13 nígbà tí àwọn agbo màlúù yín àti tí ewúrẹ́ ẹ yín bá pọ̀ sí i tán, tí fàdákà àti wúrà yín sì ń peléke sí i, tí ohun gbogbo tí ẹ ní sì ń pọ̀ sí i,
A ka tini haere au kau, me au hipi, ka nui hoki te hiriwa me te koura ki a koe, a ka tini haere nga mea katoa ki a koe;
14 nígbà náà ni ọkàn yín yóò gbéga, tí ẹ̀yin yóò sì gbàgbé Olúwa Ọlọ́run yín, tí ó mú un yín jáde láti Ejibiti wá, nínú oko ẹrú.
Na ka kake tou ngakau, a ka wareware koe ki a Ihowa, ki tou Atua, i whakaputa mai ra i a koe i te whenua o Ihipa, i te whare pononga;
15 Òun ni ó mú un yín la aginjù ẹlẹ́rù ńlá já, ilẹ̀ tí kò sí omi tí ó sì kún fún òǹgbẹ, pẹ̀lú àwọn ejò olóró ńlá ńlá àti àkéekèe. Ó mú omi jáde fún un yín láti inú àpáta.
I arataki hoki i a koe i tena koraha nui, whakamataku, i reira nei nga nakahi tu a ahi me nga kopiona, me te whenua matewai, kahore o reira wai; i whakaputa mai ano i te wai mou i roto i te kohatu kiripaka;
16 Ó fún yín ní manna láti jẹ nínú aginjù, ohun tí àwọn baba yín kò mọ̀ rí, kí Òun bá à le tẹ orí yín ba kí ó sì lè dán an yín wò, kí ó bá à lè dára fún un yín.
I whangai i a koe i te koraha ki te mana, kihai nei i mohiotia e ou matua; kia iro ai koe, kia whakamatautau ai hoki ia i a koe, a kia pai ai te tukunga iho ki a koe;
17 Ẹ lè rò nínú ara yín pé, “Agbára mi àti iṣẹ́ ọwọ́ mi ni ó mú ọ̀rọ̀ wọ̀nyí wá fún mi.”
A ka mea koe i roto i tou ngakau, Na toku kaha, na te uaua hoki o toku ringa, i whiwhi ai ahau ki enei taonga.
18 Ṣùgbọ́n ẹ rántí Olúwa Ọlọ́run yín tí ó fún un yín ní agbára àti lè ní àwọn ọrọ̀ wọ̀nyí, tí ó sì fi mú májẹ̀mú rẹ̀ ṣẹ tí ó ti búra fún àwọn baba ńlá a yín bí ó ti rí lónìí.
Engari kia mahara ki a Ihowa, ki tou Atua, nana hoki i homai te kaha ki a koe i whiwhi ai ki te taonga; kia mana ai tana kawenata i oati ai ia ki ou matua, a ka rite nei inaianei.
19 Bí ẹ bá wá gbàgbé Olúwa Ọlọ́run yín, tí ẹ sì tẹ̀lé àwọn òrìṣà mìíràn, tí ẹ sì sìn wọ́n, tí ẹ sì foríbalẹ̀ fún wọn, Mo kìlọ̀ fún un yín pé rírun ni ẹ̀yin yóò run.
Na ki te wareware koe ki a Ihowa, ki tou Atua, a ka whai ki nga atua ke, ka mahi ki a ratou, ka koropiko atu hoki ki a ratou, maku e ki atu ki a koutou i tenei ra, ka ngaro rawa koutou.
20 Bí àwọn orílẹ̀-èdè tí Olúwa parun níwájú u yín, bákan náà ni ẹ ó parun, torí pé ẹ kò gbọ́rọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run yín lẹ́nu.
Ka rite ki nga iwi e whakangaromia nei e Ihowa i to koutou aroaro, ka pera ano koutou, ka ngaro; mo koutou kihai i rongo ki te reo o Ihowa, o to koutou Atua.

< Deuteronomy 8 >