< Deuteronomy 7 >

1 Nígbà tí Olúwa Ọlọ́run rẹ bá mú ọ dé ilẹ̀ náà, tí ìwọ yóò wọ̀ lọ láti gbà, tí ìwọ yóò sì lé ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè kúrò níwájú rẹ. Àwọn ará Hiti, Girgaṣi, Amori, Kenaani, Peresi, Hifi àti àwọn ará Jebusi. Àwọn orílẹ̀-èdè méje tí wọ́n lágbára tí wọ́n sì pọ̀jù ọ lọ,
Kad te Gospod Bog tvoj uvede u zemlju u koju ideš da je naslijediš, i otjera ispred tebe narode mnoge, Heteje i Gergeseje i Amoreje i Hananeje i Ferezeje i Jeveje i Jevuseje, sedam naroda veæih i jaèih od tebe,
2 nígbà tí Olúwa Ọlọ́run rẹ bá sì ti fi wọ́n lé ẹ lọ́wọ́, tí ìwọ sì ti ṣẹ́gun wọn, kí ìwọ kí ó sì pa wọ́n run pátápátá. Má ṣe bá wọn ṣe àdéhùn àlàáfíà, ìwọ kò sì gbọdọ̀ ṣàánú fún wọn.
I preda ih Gospod Bog tvoj tebi, i ti ih razbiješ, potri ih, ne hvataj s njima vjere, niti se smiluj na njih;
3 Ìwọ kò gbọdọ̀ bá wọn dá àna. Àwọn ọmọbìnrin rẹ kò gbọdọ̀ fẹ́ àwọn ọmọkùnrin wọn, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin rẹ,
Niti se prijatelji s njima; kæeri svoje ne daji za sina njihova, niti kæeri njihove uzimaj za sina svojega.
4 torí pé wọ́n yóò yí àwọn ọmọ rẹ padà kúrò lẹ́yìn mi, láti jẹ́ kí wọn máa sin òrìṣà, ìbínú Olúwa yóò sì wá sórí rẹ, yóò sì run yín kíákíá.
Jer bi otpadila sina tvojega od mene, i služio bi bogovima drugim, te bi se razgnjevio Gospod na vas i potro vas brzo.
5 Èyí ni kí ẹ ṣe sí wọn, ẹ wó pẹpẹ wọn lulẹ̀, ẹ bi òpó òkúta ibi mímọ́ òrìṣà wọn lulẹ̀, òpó òrìṣà Aṣerah wọn ni kí ẹ gé lulẹ̀ kí ẹ sì sun ère òrìṣà wọn ní iná.
Nego ovo im uèinite: oltare njihove raskopajte, i likove njihove polomite, lugove njihove isijecite, i rezane bogove njihove ognjem spalite.
6 Torí pé ènìyàn mímọ́ ni ẹ jẹ́ sí Olúwa Ọlọ́run yín, Olúwa Ọlọ́run yín ti yàn yín láàrín gbogbo ènìyàn lórí ilẹ̀ ayé, láti jẹ́ ènìyàn rẹ̀: ohun ìní iyebíye rẹ̀.
Jer si ti narod svet Gospodu Bogu svojemu, tebe je izabrao Gospod Bog tvoj da mu budeš narod osobit mimo sve narode na zemlji.
7 Olúwa kò torí pé ẹ pọ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ ju àwọn ènìyàn yòókù lọ yàn yín, ẹ̀yin sá à lẹ kéré jù nínú gbogbo ènìyàn.
Ne zato što bi vas bilo više nego drugih naroda prihvati vas Gospod i izabra vas; jer vas bijaše manje nego ikojega drugoga naroda;
8 Ṣùgbọ́n torí Olúwa fẹ́ràn yín, tí ó sì pa ìbúra tí ó ṣe pẹ̀lú àwọn baba ńlá yín mọ́ ni ó ṣe fi ọwọ́ agbára ńlá mú un yín jáde tí ó sì rà yín padà nínú oko ẹrú, àti láti ọwọ́ agbára Farao ọba Ejibiti.
Nego što vas Gospod miluje i što drži zakletvu kojom se zakleo ocima vašim, zato vas je Gospod izveo rukom krjepkom i izbavio vas iz kuæe ropske, iz ruke Faraona cara Misirskoga.
9 Nítorí náà ẹ mọ̀ dájúdájú pé Olúwa Ọlọ́run yín, Òun ni Ọlọ́run, Ọlọ́run olóòtítọ́ ni, tí ń pa májẹ̀mú ìfẹ́ rẹ̀ mọ́ fún ẹgbẹẹgbẹ̀rún ìran, àwọn tí ó fẹ́ ẹ tí ó sì ń pa àṣẹ rẹ̀ mọ́.
I tako znaj da je Gospod Bog tvoj Bog, Bog vjeran, koji drži zavjet svoj i milost svoju do tisuæu koljena onima koji ga ljube i drže zapovijesti njegove,
10 Ṣùgbọ́n àwọn tí ó kórìíra rẹ̀ ni yóò san ẹ̀san fún ní gbangba nípa pípa wọ́n run; kì yóò sì jáfara láti san ẹ̀san fún àwọn tí ó kórìíra rẹ̀ ní gbangba.
I plaæa onima koji mrze na nj, svakome istrebljujuæi ga, i ne odgaða onome koji mrzi na nj, plaæa svakome.
11 Nítorí náà ẹ kíyèsi láti máa tẹ̀lé àwọn àṣẹ, ìlànà àti òfin tí mo fun un yín lónìí.
Zato drži zapovjesti i uredbe i zakone, koje ti danas ja zapovijedam, da ih tvoriš.
12 Bí ẹ bá ń kíyèsi àwọn òfin wọ̀nyí tí ẹ sì ń ṣọ́ra láti ṣe wọ́n, nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run yín yóò pa májẹ̀mú ìfẹ́ rẹ̀ mọ́ fún un yín, bí ó ti búra fún àwọn baba ńlá a yín.
I ako ove zakone uzaslušate i uzdržite i ustvorite, i Gospod æe Bog tvoj držati tebi zavjet i milost, za koju se zakleo ocima tvojim;
13 Yóò fẹ́ràn yín, yóò bùkún un yín yóò sì mú kí ẹ pọ̀ sí i. Yóò bùkún èso inú yín, ọ̀gbìn ilẹ̀ yín, oúnjẹ yín, wáìnì tuntun àti òróró yín, àwọn màlúù, agbo ẹran yín, àti àwọn àgùntàn, ọ̀wọ́ ẹran yín, ní ilẹ̀ tí ó ti búra fún àwọn baba ńlá yín láti fún un yín.
I milovaæe te i blagosloviæe te i umnožiæe te; blagosloviæe plod utrobe tvoje i plod zemlje tvoje, žito tvoje i vino tvoje i ulje tvoje, plod goveda tvojih i stada ovaca tvojih u zemlji za koju se zakleo ocima tvojim da æe ti je dati.
14 A ó bùkún un yín ju gbogbo ènìyàn lọ, kò sí ẹni tí yóò yàgàn nínú ọkùnrin tàbí obìnrin yín, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ọ̀kan nínú àwọn ohun ọ̀sìn in yín tí yóò wà láìlọ́mọ.
Biæeš blagosloven mimo sve narode: neæe biti u tebe ni muškoga ni ženskoga neplodna, ni meðu stokom tvojom.
15 Olúwa yóò pa ọ́ mọ́ kúrò nínú ààrùn gbogbo, kì yóò jẹ́ kí èyíkéyìí ààrùn búburú tí ẹ mọ̀ ní Ejibiti wá sára yín, ṣùgbọ́n yóò fi wọ́n lé ara gbogbo àwọn tí ó kórìíra yín.
I ukloniæe od tebe Gospod svaku bolest, i od ljutih zala Misirskih koja znaš neæe nijednoga pustiti na tebe, nego æe ih pustiti na one sve koji mrze na te.
16 Gbogbo àwọn ènìyàn tí Olúwa Ọlọ́run yín fi lé yín lọ́wọ́ ni kí ẹ parun pátápátá. Ẹ má ṣe ṣàánú fún wọn, ẹ má ṣe sin olúwa ọlọ́run wọn torí pé ìdánwò ni èyí jẹ́ fún un yín.
I istrijebi sve narode koje ti Gospod Bog tvoj preda, neka ih ne požali oko tvoje, i nemoj služiti bogovima njihovijem, jer bi ti to bilo zamka.
17 Ẹ lè máa rò láàrín ara yín pé, “Àwọn orílẹ̀-èdè yìí lágbára jù wá lọ. Báwo ni a o ṣe lé wọn jáde?”
Ako bi rekao u srcu svom: veæi su ovi narodi od mene, kako ih mogu izagnati?
18 Ṣùgbọ́n ẹ má ṣe bẹ̀rù wọn, ẹ rántí dáradára ohun tí Olúwa Ọlọ́run yín ṣe sí Farao àti gbogbo Ejibiti.
Ne boj ih se; pamti dobro što je uèinio Gospod Bog tvoj s Faraonom i sa svijem Misircima,
19 Ẹ sá à fi ojú u yín rí àwọn àdánwò ńlá, àwọn iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu ńlá, ọwọ́ agbára àti nínà ọwọ́ tí Olúwa Ọlọ́run yín fi mú un yín jáde. Olúwa Ọlọ́run yín yóò ṣe bákan náà sí gbogbo àwọn ènìyàn náà tí ẹ ń bẹ̀rù.
Velika kušanja, koja vidješe oèi tvoje, i znake i èudesa i ruku krjepku i mišicu podignutu, kojom te izvede Gospod Bog tvoj; onako æe uèiniti Gospod Bog tvoj sa svijem narodima od kojih bi se uplašio.
20 Pẹ̀lúpẹ̀lú, Olúwa Ọlọ́run yín yóò rán oyin sáàrín wọn títí tí àwọn tí ó sálà tí wọ́n sá pamọ́ fún un yín, yóò fi ṣègbé.
I stršljene æe poslati Gospod Bog tvoj na njih dokle ne izginu koji bi ostali i sakrili se od tebe.
21 Ẹ má gbọ̀n jìnnìjìnnì torí wọn, torí pé Olúwa Ọlọ́run yín tí ó wà láàrín yín, Ọlọ́run alágbára ni, àti Ọlọ́run tí ó tóbi lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
Ne plaši se od njih, jer je Gospod Bog tvoj usred tebe, Bog veliki i strašni.
22 Olúwa Ọlọ́run yín yóò lé gbogbo orílẹ̀-èdè wọ̀n-ọn-nì kúrò níwájú u yín díẹ̀díẹ̀. A kò nígbà yín láààyè láti lé wọn dànù lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo. Kí àwọn ẹranko igbó má ba à gbilẹ̀ sí i láàrín yín.
Gospod æe Bog tvoj malo pomalo potrti te narode ispred tebe; neæeš ih moæi odjedanput istrijebiti, da se ne bi umnožilo na tebe zvijerje poljsko.
23 Ṣùgbọ́n Olúwa Ọlọ́run yín yóò fi wọ́n lé e yín lọ́wọ́, yóò sì máa fà wọ́n sínú dàrúdàpọ̀ títí tí wọn yóò fi run.
Ali æe ih predati Gospod Bog tvoj tebi, i zatiraæe ih zatiranjem velikim dokle se ne zatru.
24 Yóò fi àwọn ọba wọn lé e yín lọ́wọ́, ẹ̀yin ó sì pa orúkọ wọn rẹ́ lábẹ́ ọ̀run. Kò sí ẹni tí yóò lè dojú ìjà kọ yín títí tí ẹ ó fi pa wọ́n run.
I predaæe careve njihove u tvoje ruke da zatreš ime njihovo pod nebom, neæe se nijedan održati pred tobom, dokle ih ne potreš.
25 Dá iná sun àwọn ère òrìṣà wọn, ẹ má ṣe ṣe ojúkòkòrò sí fàdákà tàbí wúrà tí ó wà lára wọn. Ẹ má ṣe mú un fún ara yín, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ yóò jẹ́ ìdẹ̀kùn fún un yín, torí pé ìríra ni sí Olúwa Ọlọ́run yín.
Rezane bogove njihove spali ognjem, nemoj da se polakomiš na srebro ili zlato što je na njima i da ga uzmeš, da ti ne bude zamka, jer je gadno pred Gospodom Bogom tvojim.
26 Ẹ má ṣe mú ohun ìríra wá sí ilé yín, kí ìwọ má ba à di ẹni ìparun bí i rẹ̀. Ẹ kórìíra rẹ̀ kí ẹ sì kà á sí ìríra pátápátá, torí pé a yà á sọ́tọ̀ fún ìparun ni.
I nemoj da uneseš gada u dom svoj, da ne budeš proklet kao i on, nego se gadi na nj i grozi se od njega, jer je prokleto.

< Deuteronomy 7 >