< Deuteronomy 5 >
1 Mose sì pe gbogbo Israẹli jọ, ó sì wí pé, Gbọ́ ìwọ Israẹli, gbọ́ ìlànà àti òfin tí mo mú wá sí etí ìgbọ́ ọ yín lónìí. Ẹ kọ wọ́n, kí ẹ sì ri dájú pé ẹ̀ ń ṣe wọ́n.
Musa nĩetire andũ a Isiraeli othe, akĩmeera atĩrĩ: Inyuĩ Aisiraeli, ta kĩiguei irĩra cia watho wa kũrũmĩrĩrwo, na mawatho marĩa ngũmwĩra ũmũthĩ mũkĩiguaga. Mũmeerute na mũtigĩrĩre nĩ mwamarũmĩrĩra.
2 Olúwa Ọlọ́run wa bá wa dá májẹ̀mú ní Horebu.
Jehova Ngai witũ nĩarĩĩkanĩire kĩrĩkanĩro na ithuĩ kũu Horebu.
3 Kì í ṣe àwọn baba wa ni Olúwa bá dá májẹ̀mú yìí bí kò ṣe àwa, àní pẹ̀lú gbogbo àwa tí a wà láààyè níbí lónìí.
Jehova ndarĩĩkanĩire kĩrĩkanĩro gĩkĩ na maithe maitũ oiki, no nĩarĩĩkanĩire na ithuĩ, ithuothe arĩa tũrĩ muoyo ũmũthĩ.
4 Olúwa bá a yín sọ̀rọ̀ lójúkojú láàrín iná lórí òkè.
Jehova aaranĩirie na inyuĩ ũthiũ kwa ũthiũ arĩ thĩinĩ wa mwaki kĩrĩma igũrũ.
5 (Ní ìgbà yìí, mo wà láàrín ẹ̀yin pẹ̀lú Ọlọ́run láti sọ ọ̀rọ̀ Olúwa fún un yín torí pé ẹ̀rù Ọlọ́run ń bà yín, ẹ kò sì lè kọjá lọ sórí òkè.) Ó sì wí pé,
(Hĩndĩ ĩyo niĩ ndarũgamĩte gatagatĩ kanyu na Jehova nĩguo ndĩmwĩre ũhoro wa Jehova, nĩ tondũ nĩmwetigagĩra mwaki ũcio, na mũtiigana kwambata kĩrĩma igũrũ.) Nake akĩmwĩra atĩrĩ:
6 “Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, tí ó mú un yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti, láti oko ẹrú jáde wá.
“Nĩ niĩ Jehova Ngai waku, ũrĩa wakũrutire bũrũri wa Misiri, kuuma bũrũri wa ũkombo.
7 “Ìwọ kò gbọdọ̀ ní ọlọ́run mìíràn pẹ̀lú mi.
“Ndũkanagĩe na ngai ĩngĩ tiga niĩ.
8 Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ère fún ara yín, tàbí àwòrán ohun kan tí ń bẹ ní òkè ọ̀run, tàbí ti ohun kan tí ń bẹ ní ìsàlẹ̀ ilẹ̀, tàbí ti ohun kan tí ń bẹ nínú omi ní ìsàlẹ̀ ilẹ̀.
“Ndũkanethondekere mũhianano mũicũhie wa mũhianĩre wa kĩndũ o gĩothe kĩrĩ kũũrĩa igũrũ, kana gũkũ thĩ, kana kĩrĩ maaĩ-inĩ marĩa marĩ mũhuro wa thĩ.
9 Ìwọ kò gbọdọ̀ tẹ orí ara rẹ ba fún wọn, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ sìn wọ́n; nítorí Èmi Olúwa Ọlọ́run rẹ, Ọlọ́run owú ni mí, tí ń bẹ ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba wò lára àwọn ọmọ, láti ìran kẹta títí dé ẹ̀kẹrin nínú àwọn tí ó kórìíra mi.
Ndũkanacinamĩrĩre kana ũcihooe, nĩgũkorwo niĩ Jehova Ngai waku ndĩ Ngai ũrĩ ũiru, herithagia ciana nĩ ũndũ wa mehia ma maithe mao nginya rũciaro rwa gatatũ na rwa kana rwa andũ arĩa maathũire,
10 Èmi a sì máa fi àánú hàn sí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn tí ó fẹ́ mi, tí wọ́n sì ń pa òfin mi mọ́.
no nĩ ngonania wendo kũrĩ njiarwa ngiri na ngiri cia andũ arĩa manyendete na magaathĩkĩra maathani makwa.
11 Ẹ má ṣe ṣi orúkọ Olúwa Ọlọ́run yín lò, torí pé ẹnikẹ́ni tí o bá ṣi orúkọ rẹ̀ lò kì yóò lọ láìjẹ̀bi.
“Ndũkanagwete rĩĩtwa rĩa Jehova Ngai waku na itherũ, nĩgũkorwo Jehova ndagatua atĩ mũndũ ndehĩtie ũrĩa ũgwetaga rĩĩtwa rĩake na itherũ.
12 Rántí ọjọ́ ìsinmi láti yà á sí mímọ́, bí Olúwa Ọlọ́run yín ti pàṣẹ fún un yín.
“Menyagĩrĩra mũthenya wa Thabatũ ũwamũrage, o ta ũrĩa Jehova Ngai waku agwathĩte.
13 Ọjọ́ mẹ́fà ni ìwọ yóò fi ṣiṣẹ́, kí ìwọ kí ó ṣe gbogbo iṣẹ́ rẹ.
Rutaga wĩra waku wothe mĩthenya ĩtandatũ,
14 Ṣùgbọ́n ọjọ́ keje ni ọjọ́ ìsinmi Olúwa Ọlọ́run rẹ: nínú rẹ̀ ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ kan: ìwọ, àti ọmọ rẹ ọkùnrin àti ọmọ rẹ obìnrin, ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ ọkùnrin àti ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ obìnrin, àti akọ màlúù rẹ, àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ, àti ohun ọ̀sìn rẹ kan, àti àlejò tí ń bẹ nínú ibodè rẹ; kí ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ ọkùnrin àti ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ obìnrin kí ó lè sinmi gẹ́gẹ́ bí ìwọ.
no mũthenya wa mũgwanja nĩ Thabatũ ya Jehova Ngai waku. Mũthenya ũcio ndũkanarute wĩra o na ũrĩkũ, wee mwene, kana mũrũguo, kana mwarĩguo, kana ndungata yaku ya mũndũ mũrũme kana ya mũndũ-wa-nja, kana ndegwa yaku, kana ndigiri yaku kana nyamũ o na ĩrĩkũ yaku, kana mũgeni ũrĩ gwaku mũciĩ, nĩgeetha ndungata yaku ya mũndũ mũrũme o na ya mũndũ-wa-nja o nacio ihurũke o tawe.
15 Sì rántí pé, ìwọ ti jẹ́ ẹrú ní Ejibiti rí, àti pé Olúwa Ọlọ́run rẹ yọ ọ́ kúrò níbẹ̀ pẹ̀lú agbára ńlá, àti nína ọwọ́ rẹ̀. Torí èyí ni Olúwa Ọlọ́run rẹ ṣe pàṣẹ fún ọ láti ya ọjọ́ ìsinmi sí mímọ́.
Ririkanaga o nawe warĩ ngombo bũrũri wa Misiri, na atĩ nĩ Jehova Ngai waku wakũrutire kuo na njara ĩrĩ hinya na guoko kwa ũhoti gũtambũrũkĩtio. Nĩ ũndũ ũcio Jehova Ngai waku agwathĩte ũmenyagĩrĩre mũthenya wa Thabatũ.
16 Bọ̀wọ̀ fún baba òun ìyá rẹ, bí Olúwa Ọlọ́run yín ti pàṣẹ fún ọ, kí ọjọ́ rẹ kí ó lè pẹ́, àti kí ó lè dára fún ọ ní ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ fi fún ọ.
“Tĩĩa thoguo na nyũkwa o ta ũrĩa Jehova Ngai waku agwathĩte, nĩgeetha ũtũũre matukũ maingĩ, na maũndũ maku magĩrĩre bũrũri-inĩ ũrĩa Jehova Ngai waku egũkũhe.
17 Ìwọ kò gbọdọ̀ pànìyàn.
“Ndũkanoragane.
18 Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe panṣágà.
“Ndũkanatharanie.
20 Ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ́rìí èké sí ẹnìkejì rẹ.
“Ndũkanaigĩrĩre mũndũ ũrĩa ũngĩ kĩgeenyo.
21 Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò sí aya ẹnìkéjì rẹ, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò sí ilé ẹnìkéji rẹ, oko rẹ̀, àti ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ ọkùnrin, àti ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ obìnrin, akọ màlúù rẹ̀ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, àti ohun gbogbo tí í ṣe ti ẹnìkéji rẹ.”
“Ndũkanacumĩkĩre mũtumia wa mũndũ ũrĩa ũngĩ. Ndũkanerirĩrie nyũmba ya mũndũ ũrĩa ũngĩ kana gĩthaka gĩake, kana ndungata yake ya mũndũ mũrũme kana ya mũndũ-wa-nja, kana ndegwa yake kana ndigiri yake, kana kĩndũ o nakĩ kĩa mũndũ ũrĩa ũngĩ.”
22 Wọ̀nyí ni àwọn àṣẹ Olúwa tí a kéde rẹ̀ sí gbogbo ìpéjọpọ̀ ọ yín, níbẹ̀ ní orí òkè, láàrín iná, ìkùùkuu àti òkùnkùn biribiri, kò sì fi ohunkóhun kún un mọ́. Ó sì kọ wọ́n sínú wàláà méjì, Ó sì fi wọ́n lé mi lọ́wọ́.
Macio nĩmo maathani marĩa Jehova aarĩirie ũngano wanyu wothe na mũgambo mũnene kĩrĩma-inĩ kĩu arĩ thĩinĩ wa mwaki, o na itu-inĩ, o na nduma ndumanu; na ndoongereire ũndũ ũngĩ. Agĩcooka akĩmaandĩka ihengere-inĩ igĩrĩ cia mahiga, akĩĩnengera.
23 Nígbà tí ẹ gbóhùn láti inú òkùnkùn wá, nígbà tí iná náà ń yọ iná lala, àwọn aṣáájú ẹ̀yà a yín àti àwọn àgbàgbà yín tọ̀ mí wá.
Rĩrĩa mwaiguire mũgambo ũkiuma nduma-inĩ ĩyo, na kĩrĩma gĩgĩakanaga mwaki, athuuri na atongoria a mĩhĩrĩga yanyu yothe nĩmookire kũrĩ niĩ.
24 Ẹ sì sọ pé, “Olúwa Ọlọ́run wa ti fi ògo rẹ̀ hàn wá, àti títóbi rẹ̀ a sì ti gbóhùn rẹ̀ láti àárín iná wá. A ti rí i lónìí pé, ènìyàn sì lè wà láààyè lẹ́yìn tí Ọlọ́run bá bá a sọ̀rọ̀.
Mũkiuga atĩrĩ, “Jehova Ngai witũ nĩatuonetie riiri wake na ũnene wake, na nĩtũiguĩte mũgambo wake ũkiuma mwaki-inĩ. Ũmũthĩ nĩtwonete atĩ mũndũ no atũũre muoyo o na Ngai aarĩtie nake.
25 Ṣùgbọ́n èéṣe tí àwa yóò fi kú? Iná ńlá yìí yóò jó wa run, bí àwa bá sì tún gbọ́ ohun Olúwa Ọlọ́run wa, àwa ó kú.
No rĩrĩ, tũgũkua nĩkĩ? Mwaki ũyũ mũnene ũũ nĩ ũgũtũniina, na nĩtũgũkua tũngĩigua mũgambo wa Jehova Ngai witũ hĩndĩ ĩngĩ.
26 Ta ni nínú ẹlẹ́ran ara tí ó ti gbọ́ ohun Ọlọ́run alààyè láti inú iná rí, bí àwa ti gbọ́ ọ, tí a sì wà láyé?
Nĩ ũndũ-rĩ, nĩ mũndũ ũrĩkũ ũrĩ muoyo ũrĩ waigua mũgambo wa Ngai ũrĩa ũtũũraga muoyo akĩaria arĩ thĩinĩ wa mwaki ta ũrĩa ithuĩ tũiguĩte, na agatũũra muoyo?
27 Súnmọ́ tòsí ibẹ̀ kí o sì gbọ́ gbogbo ohun tí Olúwa Ọlọ́run wa yóò sọ, nígbà náà sọ ohunkóhun tí Olúwa Ọlọ́run wa sọ fún ọ fún wa. A ó sì fetísílẹ̀, a ó sì gbọ́rọ̀.”
Wee thiĩ ũkuhĩrĩrie, ũigue ũrĩa wothe Jehova Ngai witũ ekuuga. Ũcooke ũũke ũtwĩre ũrĩa wothe Jehova Ngai witũ egũkwĩra. Nĩtũkũigua na twathĩke.”
28 Olúwa ń gbọ́ nígbà tí ẹ̀yin ń bá mi sọ̀rọ̀, Olúwa sì sọ fún mi pé, “Mo ti gbọ́ ohun tí àwọn ènìyàn yí sọ fún ọ. Gbogbo ohun tí wọ́n sọ dára,
Jehova nĩamũiguire rĩrĩa mwanjaragĩria, nake Jehova akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Nĩnjiguĩte ũrĩa andũ aya makwĩrĩte. Ũhoro ũcio wothe maarĩtie nĩ mwega.
29 ìbá ti dára tó, bí ọkàn wọn bá lè bẹ̀rù mi, tí ó sì ń pa gbogbo òfin mi mọ́ nígbà gbogbo, kí ó bá à lè dára fún wọn, àti àwọn ọmọ wọn láéláé.
Naarĩ korwo magĩa na ngoro ya gũtũma meĩndigagĩre na matũũre marũmĩtie maathani makwa hĩndĩ ciothe, nĩguo matũũre monaga maũndũ mega o ene o na ciana ciao nginya tene!
30 “Lọ sọ fún wọn kí wọn padà sínú àgọ́ wọn.
“Thiĩ ũmeere macooke hema-inĩ ciao.
31 Ṣùgbọ́n ìwọ túbọ̀ dúró síbí pẹ̀lú mi, kí n bá à lè fún ọ ní àwọn àṣẹ tí o gbọdọ̀ fi kọ́ wọn láti máa tẹ̀lé ní ilẹ̀ náà tí èmi ó fi fún wọn láti ní.”
No wee-rĩ, ikara haha harĩ niĩ nĩgeetha ngũhe ũhoro wa maathani mothe, na irĩra cia watho wa kũrũmĩrĩrwo, na mawatho marĩa ũrĩmarutaga nĩguo mamarũmagĩrĩre marĩ bũrũri ũrĩa ngũmahe mawĩgwatĩre ũtuĩke wao.”
32 Torí èyí, ẹ ṣọ́ra láti máa ṣe ohun tí Olúwa Ọlọ́run yín tí pa ní àṣẹ fún un yín; ẹ má ṣe yà sọ́tùn ún tàbí sósì.
Nĩ ũndũ ũcio, mwĩmenyererei nĩguo mwĩkage ũrĩa Jehova Ngai wanyu amwathĩte; mũtikarore na mwena wa ũrĩo kana wa ũmotho.
33 Ẹ rìn ní gbogbo ọ̀nà tí Olúwa Ọlọ́run yín ti pàṣẹ fún un yín, kí ẹ bá à le yè, kí ó sì dára fún un yín, kí ọjọ́ ọ yín bá à lè pẹ́ ní ilẹ̀ tí ẹ̀yin yóò gbà.
Thiiagai na mĩthiĩre ĩrĩa yothe Jehova Ngai wanyu amwathĩte, nĩguo mũtũũre muoyo na mũgaacĩre, na nĩguo mũtũme matukũ manyu maingĩhe ma gũtũũra bũrũri ũcio mũkegwatĩra.