< Deuteronomy 4 >
1 Gbọ́ Israẹli, gbọ́ òfin àti ìlànà tí èmi yóò kọ́ ọ yín. Ẹ tẹ̀lé wọn kí ẹ ba à lè yè, kí ẹ ba à lè lọ láti gba ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín yóò fi fún un yín.
Atĩrĩrĩ, inyuĩ andũ a Isiraeli, iguai watho wa kũrũmĩrĩrwo, na mawatho marĩa ngũmũruta. Marũmagĩrĩrei nĩgeetha mũtũũre muoyo na nĩguo mũthiĩ mũtoonye mwĩgwatĩre bũrũri ũrĩa Jehova Ngai wa maithe manyu aramũhe.
2 Ẹ má ṣe fi kún àwọn ohun tí mo pàṣẹ fún un yín, ẹ kò sì gbọdọ̀ yọ kúrò nínú wọn, ṣùgbọ́n ẹ pa òfin Olúwa Ọlọ́run yín tí mo fún un yín mọ́.
Mũtikanongerere ũrĩa ngũmwatha kana mũrutarute, no rũmagiai maathani ma Jehova Ngai wanyu marĩa ngũmũhe.
3 Ẹ ti fi ojú ara yín rí ohun tí Olúwa ṣe ní Baali-Peori. Olúwa Ọlọ́run yín run gbogbo àwọn tí ó tẹ̀lé òrìṣà Baali-Peori kúrò ní àárín yín.
Nĩmweyoneire na maitho manyu ũrĩa Jehova eekire kũu Baali-Peori. Jehova Ngai wanyu nĩaniinire gatagatĩ-inĩ kanyu ũrĩa wothe warũmagĩrĩra Baali ya Peori,
4 Ṣùgbọ́n gbogbo ẹ̀yin tí ẹ gbẹ́kẹ̀lé Olúwa Ọlọ́run láìyẹsẹ̀ ni ẹ wà láààyè lónìí.
no arĩa othe anyu maarũmĩrĩire Jehova Ngai wanyu, marĩ muoyo nginya ũmũthĩ.
5 Ẹ kíyèsi i, mo ti kọ́ ọ yín ní àwọn òfin àti àṣẹ bí Olúwa Ọlọ́run mi ti pàṣẹ fún mi, kí ẹ ba à le tẹ̀lé wọn ní ilẹ̀ náà tí ẹ ń lọ láti ní ní ìní.
Atĩrĩrĩ, nĩndĩmũrutĩte watho wa kũrũmĩrĩrwo, na mawatho ta ũrĩa Jehova Ngai wakwa aanjathire, nĩgeetha mũmarũmagĩrĩre bũrũri-inĩ ũcio mũgũtoonya mũwĩgwatĩre.
6 Ẹ máa kíyèsi wọn dáradára. Èyí ni yóò fi ọgbọ́n àti òye yín han àwọn orílẹ̀-èdè. Àwọn tí wọn yóò gbọ́ nípa àwọn ìlànà wọ̀nyí, tí wọn yóò sì máa wí pé, “Dájúdájú, orílẹ̀-èdè ńlá yìí kún fún ọgbọ́n àti òye.”
Menyagĩrĩrai maathani macio wega, nĩgũkorwo ũguo nĩguo ũkoonania ũũgĩ na ũmenyo wanyu kũrĩ ndũrĩrĩ iria irĩiguaga ũhoro wa watho ũyũ wa kũrũmĩrĩrwo, ciugage atĩrĩ, “Ti-itherũ rũrĩrĩ rũrũ rũnene nĩ rũũgĩ na nĩ andũ marĩ na ũmenyo wa maũndũ.”
7 Orílẹ̀-èdè olókìkí wo ni ọlọ́run wọn tún súnmọ́ wọn, bí Olúwa Ọlọ́run wa ti súnmọ́ wa nígbàkígbà tí a bá ń ké pè é?
Nĩ rũrĩrĩ rũrĩkũ rũngĩ rũnene ũũ, rũrĩ na ngai ciao irĩ hakuhĩ nao ta ũrĩa Jehova Ngai witũ akoragwo hakuhĩ na ithuĩ rĩrĩa rĩothe tũkũmũhooya?
8 Orílẹ̀-èdè wo ló tún le lókìkí láti ní àwọn ìlànà òdodo, àti òfin gẹ́gẹ́ bí àwọn òfin wọ̀nyí tí mo ń gbé kalẹ̀ fún un yín lónìí.
Ningĩ nĩ rũrĩrĩ rũrĩkũ rũngĩ rũnene ũũ rũrĩ na watho wa kũrũmĩrĩrwo, na mawatho ma kĩhooto ta maya ndĩramũhe ũmũthĩ?
9 Kìkì i kí ẹ kíyèsára, kí ẹ sì ṣọ́ra a yín gidigidi kí ẹ má ba à gbàgbé àwọn ohun tí ojú yín ti rí, kí wọn má sì ṣe sá kúrò lóókan àyà yín níwọ̀n ìgbà tí ẹ sì wà láààyè. Ẹ máa fi wọ́n kọ́ àwọn ọmọ yín àti àwọn ọmọ wọn tí ń bọ̀ lẹ́yìn wọn.
Mwĩmenyererei, na mũikare mwĩiguĩte nĩgeetha mũtikanariganĩrwo nĩ maũndũ marĩa muonete na maitho manyu, kana mũreke mehere ngoro-inĩ cianyu matukũ marĩa mothe mũgũtũũra muoyo. Marutagei ciana cianyu o na ciana cia ciana cianyu iria igooka thuutha.
10 Ẹ rántí ọjọ́ tí ẹ dúró níwájú Olúwa Ọlọ́run yín ní Horebu, nígbà tí ó wí fún mi pé, “Kó àwọn ènìyàn wọ̀nyí jọ síwájú mi láti gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, kí wọ́n lè kọ́ láti máa bu ọlá náà fún mi ní gbogbo ìgbà tí wọ́n bá gbé lórí ilẹ̀ náà, kí wọ́n sì le è fi wọ́n kọ́ àwọn ọmọ wọn.”
Ririkanai mũthenya ũrĩa mwarũgamire mbere ya Jehova Ngai wanyu kũu Horebu, rĩrĩa anjĩĩrire atĩrĩ, “Cookanĩrĩria andũ mbere yakwa nĩguo maigue ciugo ciakwa, nĩgeetha mamenye kwĩĩndigĩra rĩrĩa rĩothe megũtũũra muoyo bũrũri ũcio, na marute ciana ciao maũndũ macio.”
11 Ẹ̀yin súnmọ́ tòsí, ẹ sì dúró ní ẹsẹ̀ òkè náà, òkè náà sì ń jóná dé agbede-méjì ọrun, pẹ̀lú òkùnkùn, àti àwọsánmọ̀, àti òkùnkùn biribiri.
Nĩmwakuhĩrĩirie na mũkĩrũgama magũrũ-inĩ ma kĩrĩma hĩndĩ ĩrĩa kĩarĩrĩmbũkaga mwaki wakinyĩte o igũrũ, gũkĩgĩa na matu mairũ na nduma ndumanu.
12 Olúwa sì bá yín sọ̀rọ̀ láti àárín iná náà wá. Ẹ gbọ́ àwọn ìró ohùn, ṣùgbọ́n ẹ kò rí ẹnikẹ́ni, ohùn nìkan ni ẹ gbọ́.
Hĩndĩ ĩyo Jehova nĩamwarĩirie arĩ thĩinĩ wa mwaki ũcio. Nĩmwaiguire mũgambo, no gũtirĩ kĩndũ muonire; mũgambo noguo warĩ ho.
13 Ó sọ àwọn májẹ̀mú rẹ̀ fún un yín àní àwọn òfin mẹ́wẹ̀ẹ̀wá tí ó pàṣẹ fún un yín láti máa tẹ̀lé, ó sì kọ wọ́n sórí wàláà òkúta méjì.
Nĩamũmenyithirie ũhoro wa kĩrĩkanĩro gĩake, na nĩmo Maathani marĩa Ikũmi, marĩa aamwathire mũrũmagĩrĩre, na agĩcooka akĩmaandĩka ihengere-inĩ igĩrĩ cia mahiga.
14 Olúwa sì pàṣẹ fún mi nígbà náà láti kọ yín ní ìlànà àti ìdájọ, kí ẹ̀yin kí ó lè máa ṣe wọ́n ní ilẹ̀ náà, ní ibi tí ẹ̀yin ń lọ láti gbà á.
Na rĩrĩ, Jehova nĩanjathire o ihinda rĩu ndĩmũrute watho ũcio wa kũrũmagĩrĩrwo, o na mawatho marĩa mũrĩrũmagĩrĩra mũrĩ bũrũri ũcio mũraringa Rũũĩ rwa Jorodani mũkawĩgwatĩre.
15 Ẹ kíyèsára gidigidi, torí pé, ẹ kò rí ìrísí ohunkóhun ní ọjọ́ tí Olúwa bá yín sọ̀rọ̀ ní Horebu láti àárín iná wá. Torí náà ẹ ṣọ́ra yín gidigidi,
Mũthenya ũrĩa Jehova aamwarĩirie o kũu Horebu arĩ thĩinĩ wa mwaki, mũtionire mũhianĩre o na ũrĩkũ. Nĩ ũndũ ũcio mwĩmenyagĩrĩrei mũno,
16 kí ẹ ma ba à ba ara yín jẹ́ nípa ṣíṣe ère fún ara yín, àní ère lóríṣìíríṣìí yálà èyí tí ó ní ìrísí ọkùnrin tàbí tí obìnrin,
nĩgeetha mũtikanethũkie na gwĩthondekera mũhianano mũicũhie, mũhiano wa kĩndũ o gĩothe, ũthondeketwo ũrĩ mũhianĩre wa mũndũ mũrũme kana wa mũndũ-wa-nja,
17 tàbí ti ẹranko orí ilẹ̀, tàbí ti ẹyẹ tí ń fò ní òfúrufú,
kana wa nyamũ o yothe ĩrĩ gũkũ thĩ, kana wa nyoni o yothe ĩrĩa yũmbũkaga rĩera-inĩ,
18 tàbí ti àwòrán onírúurú ẹ̀dá tí ń fà lórí ilẹ̀, tàbí ti ẹja nínú omi.
kana mũhianĩre wa nyamũ o na ĩrĩkũ ĩtambaga thĩ, kana mũhianĩre wa thamaki o na ĩrĩkũ ĩrĩa ĩrĩ maaĩ-inĩ marĩa marĩ mũhuro wa thĩ.
19 Bí ẹ bá wòkè tí ẹ rí oòrùn, òṣùpá àti àwọn ìràwọ̀: àwọn ohun tí a ṣe lọ́jọ̀ sójú ọ̀run, ẹ má ṣe jẹ́ kí wọ́n tàn yín jẹ dé bi pé ẹ̀yin yóò foríbalẹ̀ fún wọn, àti láti máa sin ohun tí Olúwa Ọlọ́run yín dá fún gbogbo orílẹ̀-èdè lábẹ́ ọ̀run.
Na rĩrĩa mwarora igũrũ, muona riũa, kana mweri na njata, arĩ cio mbũtũ ciothe cia igũrũ, mũtikanaguucĩrĩrio mũciinamĩrĩre, kana mũhooe indo iria Jehova Ngai wanyu aagaĩire ndũrĩrĩ iria ciothe irĩ gũkũ thĩ.
20 Olúwa Ọlọ́run yín sì ti mú ẹ̀yin jáde kúrò nínú iná ìléru ńlá, àní ní Ejibiti, láti lè jẹ́ ènìyàn ìní i rẹ̀, bí ẹ̀yin ti jẹ́ báyìí.
No inyuĩ-rĩ, Jehova nĩamũrutire icua-inĩ rĩu rĩa gũtwekia igera akĩmũruta bũrũri wa Misiri, nĩgeetha mũtuĩke andũ ake kĩũmbe, o ta ũrĩa mũtariĩ rĩu.
21 Inú Olúwa ru sí mi nítorí yín, ó sì ti búra pé èmi kì yóò la Jordani kọjá, èmi kì yóò sì wọ ilẹ̀ rere tí Olúwa Ọlọ́run fi fún un yín, ní ìní yín.
Jehova nĩandakarĩire nĩ ũndũ wanyu, na akĩĩhĩta na mwĩhĩtwa akiuga atĩ ndikaringa Rũũĩ rwa Jorodani, ndonye bũrũri ũcio mwega ũrĩa Jehova Ngai wanyu aramũhe ũrĩ igai rĩanyu.
22 Èmi yóò kú ní ilẹ̀ yìí, èmi kì yóò la Jordani kọjá, ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti fẹ́ rékọjá sí òdìkejì odò láti gba ilẹ̀ rere náà.
Niĩ ngaakuĩra bũrũri ũyũ; ndikaringa Rũũĩ rwa Jorodani; no inyuĩ mũkirie kũringa mũrĩmo ũrĩa ũngĩ mwĩgwatĩre bũrũri ũcio mwega.
23 Ẹ ṣọ́ra, kí ẹ má ṣe gbàgbé májẹ̀mú Olúwa Ọlọ́run yín tí ó ti bá a yín dá. Ẹ má ṣe ṣe ère ní ìrísí ohunkóhun fún ara yín, èèwọ̀ ni Olúwa Ọlọ́run yín kà á sí.
Mwĩmenyererei mũtikariganĩrwo nĩ kĩrĩkanĩro kĩa Jehova Ngai wanyu kĩrĩa aarĩkanĩire na inyuĩ; mũtikanethondekere mũhianano wa kĩndũ o gĩothe kĩrĩa Ngai akaananĩtie.
24 Torí pé iná ajónirun ni Olúwa Ọlọ́run yín, Ọlọ́run owú ni.
Nĩgũkorwo Jehova Ngai wanyu nĩ mwaki ũniinanaga, na nĩ Ngai ũrĩ ũiru.
25 Lẹ́yìn ìgbà tí ẹ ti ní àwọn ọmọ àti àwọn ọmọ ọmọ, tí ẹ sì ti gbé ní ilẹ̀ yìí pẹ́, bí ẹ bá wá ba ara yín jẹ́ nípa ṣíṣe irú ère yówù tó jẹ́, tí ẹ sì ṣe búburú lójú Olúwa Ọlọ́run yín, tí ẹ sì mú un bínú.
Thuutha wa kũgĩa na ciana, o na ciana cia ciana cianyu, na mũkorwo mũtũũrĩte bũrũri ũcio ihinda iraaya, mũngĩgacooka mwĩthũkie mwĩthondekere mũhianano mũicũhie wa mũthemba o na ũrĩkũ, na mwĩke maũndũ mooru maitho-inĩ ma Jehova Ngai wanyu, mũtũme arakare-rĩ,
26 Mo pe ọ̀run àti ayé láti jẹ́rìí takò yín lónìí, pé kíákíá ni ẹ ó parun ní ilẹ̀ náà tí ẹ ń la Jordani kọjá lọ láti gbà. Ẹ kò ní pẹ́ ní ilẹ̀ náà, ṣùgbọ́n ẹ̀yin yóò run pátápátá.
ũmũthĩ ndeeta igũrũ na thĩ ituĩke aira atĩ nĩmũkaniinwo o narua kuuma bũrũri ũcio mũraringa Rũũĩ rwa Jorodani mũkawĩgwatĩre. Mũtigatũũra kũndũ kũu ihinda iraaya na hatirĩ nganja nĩ mũkaaniinwo.
27 Olúwa yóò fọ́n yín ká sí àárín àwọn ènìyàn náà, àwọn díẹ̀ nínú yín ni yóò yè láàrín orílẹ̀-èdè tí Olúwa yóò fọ́n yín sí.
Jehova nĩakamũharagania kũrĩ andũ a ndũrĩrĩ, na no andũ anini anyu magaatigara gatagatĩ-inĩ ka ndũrĩrĩ iria Jehova akaamũharaganĩria.
28 Ẹ ó sì máa sin ọlọ́run tí á fi ọwọ́ ènìyàn ṣe: tí wọ́n fi igi àti òkúta ṣe, èyí tí kò le ríran, gbọ́rọ̀, jẹun tàbí gbọ́ òórùn.
Mũrĩ kũu, nĩmũkahooyaga ngai ithondeketwo nĩ andũ cia mĩtĩ na cia mahiga, o iria itangĩhota kuona, kana ciigue, kana irĩe, o na kana ciigue mũrukĩ.
29 Bí ẹ̀yin bá wá Olúwa Ọlọ́run yín láti bẹ̀ ẹ́, ẹ ó ri i, bí ẹ bá wá a, pẹ̀lú gbogbo ọkàn yín àti gbogbo àyà a yín.
No mũngĩgaacaria Jehova Ngai wanyu mũrĩ kũu, nĩmũkamuona, angĩkorwo nĩmũkamũrongoria na ngoro cianyu ciothe na muoyo wanyu wothe.
30 Bí ẹ bá wà nínú wàhálà, bí gbogbo nǹkan wọ̀nyí bá ṣẹlẹ̀ sí yín, láìpẹ́ ẹ ó tún padà tọ Olúwa Ọlọ́run yín wá, ẹ ó sì gbọ́ tirẹ̀.
Rĩrĩa mũgaakorwo mũrĩ mathĩĩna-inĩ na maũndũ maya mothe mekĩke kũrĩ inyuĩ, nĩmũgacookerera Jehova Ngai wanyu na mũmwathĩkĩre matukũ-inĩ ma thuutha.
31 Nítorí pé Olúwa Ọlọ́run yín aláàánú ni, kò ní gbàgbé tàbí pa yín rẹ́ tàbí kó gbàgbé májẹ̀mú pẹ̀lú àwọn baba ńlá yín, èyí tí ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ nípa ìbúra.
Nĩgũkorwo Jehova Ngai wanyu nĩ Ngai ũrĩ-tha; ndakamũtiganĩria, kana amũniine, kana ariganĩrwo nĩ kĩrĩkanĩro gĩake na maithe manyu ma tene kĩrĩa aarĩkanĩire nao na mwĩhĩtwa.
32 Ẹ béèrè báyìí nípa ti àwọn ọjọ́ ìgbàanì ṣáájú kí a tó bí i yín, láti ìgbà tí Ọlọ́run ti dá ènìyàn sórí ilẹ̀ ayé. Ẹ béèrè láti igun ọ̀run kan sí èkejì. Ǹjẹ́ irú nǹkan olókìkí báyìí: ti ṣẹlẹ̀ rí? Ǹjẹ́ a ti gbọ́ irú u rẹ̀ rí?
Na rĩrĩ, ũriai ũhoro wa matukũ marĩa mahĩtũku, o marĩa maarĩ mbere yanyu, kuuma mũthenya ũrĩa Ngai ombire mũndũ gũkũ thĩ; ũriai kuuma gĩturi kĩmwe kĩa igũrũ nginya kĩrĩa kĩngĩ. Nĩ kũrĩ kwahaana ũndũ mũnene ta ũyũ, kana nĩ kũrĩ kwaiguĩka ũndũ ũngĩ taguo?
33 Ǹjẹ́ àwọn ènìyàn mìíràn tí ì gbọ́ ohùn Ọlọ́run rí, tí ó sọ̀rọ̀ jáde láti inú iná, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin ti gbọ́ tí ẹ sì yè?
Nĩ kũrĩ andũ angĩ marĩ maigua mũgambo wa Ngai akĩaria arĩ thĩinĩ wa mwaki, ta ũrĩa inyuĩ mũiguĩte, na magatũũra muoyo?
34 Ǹjẹ́ Ọlọ́run kan ti gbìyànjú àti mú orílẹ̀-èdè kan jáde kúrò nínú òmíràn fúnra rẹ̀ rí, nípa ìdánwò, nípa iṣẹ́ àmì, àti iṣẹ́ ìyanu nípa ogun, tàbí nípa ọwọ́ agbára tàbí nína apá, àti nípa ẹ̀rù ńlá: gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí Olúwa Ọlọ́run yín ṣe fún un yín ní Ejibiti ní ojú ẹ̀yin tìkára yín?
Nĩ kũrĩ ngai yanageria kwĩyoera rũrĩrĩ ĩrũrutĩte thĩinĩ wa rũrĩa rũngĩ, na ũndũ wa magerio, na kũringa ciama, na morirũ, na kũhũũrana mbaara, na gwĩka maũndũ na njara ĩrĩ na hinya na guoko gũtambũrũkĩtio; o na kana ciĩko ingĩ nene na cia gwĩtigĩrwo ta maũndũ marĩa mothe Jehova Ngai wanyu aamwĩkĩire kũu bũrũri wa Misiri mũkĩĩonagĩra na maitho?
35 A fi gbogbo nǹkan wọ̀nyí hàn yín kí ẹ bá a lè gbà pé Olúwa ni Ọlọ́run. Kò sì sí ẹlòmíràn lẹ́yìn rẹ̀.
Muonirio maũndũ macio nĩgeetha mũmenye atĩ Jehova nĩwe Ngai; tiga o we wiki gũtirĩ ũngĩ.
36 Ó jẹ́ kí ẹ gbọ́ ohùn rẹ̀ láti ọ̀run wá, láti kọ́ ọ yín. Ní ayé, ó fi iná ńlá rẹ̀ hàn yín, ẹ sì gbọ́ ohùn rẹ̀ láti àárín iná wá,
Nĩatũmire mũigue mũgambo wake kuuma igũrũ nĩguo amũrute. Nakuo thĩ akĩmuonia mwaki wake mũnene, na mũkĩigua ciugo ciake ikiuma mwaki-inĩ ũcio.
37 torí pé ó fẹ́ràn àwọn baba ńlá yín, ó sì yan àwọn ọmọ wọn ní ipò lẹ́yìn wọn. Nípa ìwà láààyè àti nípa agbára ńlá rẹ̀ ni ó fi mú un yín kúrò ní Ejibiti.
Tondũ nĩendeete maithe manyu ma tene, na agĩthuura njiaro iria igooka thuutha wao, nĩamũrũtire bũrũri wa Misiri na hinya mũnene, na agĩtwarana na inyuĩ,
38 Láti lé àwọn orílẹ̀-èdè tí ó tóbi tí ó sì lágbára níwájú yín; láti le è mú un yín wá sí ilẹ̀ wọn kí ẹ lè jogún rẹ̀ bí ó ti rí lónìí.
nĩgeetha amũingatĩre ndũrĩrĩ nene na irĩ hinya kũmũkĩra, amũrehe bũrũri wacio, amũhe guo ũtuĩke igai rĩanyu, ta ũrĩa gũtariĩ ũmũthĩ.
39 Ẹ gbà kí ẹ sì fi sọ́kàn lónìí pé Olúwa ni Ọlọ́run lókè ọ̀run lọ́hùn ún àti ní ilẹ̀ ní ìsàlẹ̀ níhìn-ín. Kò sí òmíràn mọ́.
Menyai na mũnyiite na ngoro cianyu ũmũthĩ atĩ Jehova nĩwe Ngai kũu igũrũ na gũkũ thĩ. Gũtirĩ ũngĩ.
40 Ẹ pa àwọn ìlànà àti àṣẹ rẹ̀ mọ́ tí mo ń fún un yín lónìí; kí ó ba à le è yẹ yín, kí ẹ̀yin sì le è pẹ́ ní ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run yín fún un yín ní gbogbo ìgbà.
Rũmiai watho wake wa kũrũmĩrĩrwo na maathani make marĩa ngũmũhe ũmũthĩ, nĩgeetha muonage maũndũ mega inyuĩ ene na ciana cianyu iria igooka thuutha wanyu, na nĩguo mũtũũre matukũ maingĩ bũrũri ũrĩa Jehova Ngai wanyu ekũmũhe nginya tene.
41 Mose sì ya àwọn ìlú mẹ́ta kan sọ́tọ̀ ní apá ìwọ̀-oòrùn Jordani.
Hĩndĩ ĩyo Musa akĩamũra matũũra matatũ manene mwena wa irathĩro wa Jorodani,
42 Kí apànìyàn kí ó lè máa sá síbẹ̀, tí ó bá ṣi ẹnìkejì rẹ̀ pa, tí kò sì kórìíra rẹ̀ tẹ́lẹ̀ rí, àti pé bí ó bá sá sí ọ̀kan nínú ìlú wọ̀nyí kí ó lè là.
marĩa mũndũ o na ũrĩkũ ũragĩte mũndũ angĩorĩire angĩkorwo oragĩte mũndũ wa itũũra rĩake atathugundĩte, na atarĩ na rũthũũro. Nĩangĩorĩire itũũra rĩmwe rĩa macio ahonokie muoyo wake.
43 Àwọn ìlú mẹ́tẹ̀ẹ̀ta náà nìwọ̀nyí: Beseri ní ijù, ní ilẹ̀ pẹ̀tẹ́lẹ̀, tí àwọn ọmọ Reubeni; Ramoti ní Gileadi, ti àwọn ọmọ Gadi àti Golani ní Baṣani, ti àwọn ará Manase.
Matũũra macio nĩmo maya: Bezeri kũu werũ-inĩ ũrĩa mwaraganu, nĩ ũndũ wa andũ a mũhĩrĩga wa Rubeni; na Ramothu kũu Gileadi, nĩ ũndũ wa andũ a mũhĩrĩga wa Gadi; na Golani kũu Bashani, nĩ ũndũ wa mũhĩrĩga wa Manase.
44 Èyí ni òfin tí Mose gbé kalẹ̀ fún àwọn ará Israẹli.
Ũyũ nĩguo watho ũrĩa Musa aaheire andũ a Isiraeli maũrũmagĩrĩre.
45 Wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀rí, àti ìlànà àti ìdájọ́ tí Mose fi lélẹ̀ fún ún àwọn ọmọ Israẹli, lẹ́yìn tí wọ́n ti jáde kúrò ní Ejibiti.
Ici nĩcio irĩkanĩro na watho wa kũrũmĩrĩrwo, na mawatho marĩa Musa aamaheire rĩrĩa moimire bũrũri wa Misiri,
46 Tí wọ́n sì wà ní ẹ̀bá àfonífojì Beti-Peori ní ìlà-oòrùn Jordani; ní ilẹ̀ Sihoni, ọba àwọn Amori tí ó jẹ ọba Heṣboni tí Mose àti àwọn ọmọ Israẹli ṣẹ́gun, bí wọ́n ṣe ń ti Ejibiti bọ̀.
na maarĩ gĩtuamba-inĩ gũkuhĩ na Bethi-Peori, irathĩro rĩa Rũũĩ rwa Jorodani, bũrũri-inĩ wa Sihoni mũthamaki wa Aamori, ũrĩa waathanaga Heshiboni, nĩwe wahootirwo nĩ Musa na andũ a Isiraeli hĩndĩ ĩrĩa moimaga bũrũri wa Misiri.
47 Wọ́n gba ilẹ̀ rẹ̀, àti ilẹ̀ Ogu ọba Baṣani àwọn ọba Amori méjèèjì tí ń bẹ ní ìlà-oòrùn Jordani.
Nĩmegwatĩire bũrũri wake na makĩĩgwatĩra bũrũri wa Ogu mũthamaki wa Bashani, athamaki acio eerĩ a Aamori a kũu irathĩro rĩa Rũũĩ rwa Jorodani.
48 Ilẹ̀ wọ̀nyí bẹ̀rẹ̀ láti Aroeri ní etí odò Arnoni dé orí òkè Sirioni (èyí ni Hermoni).
Bũrũri ũcio uumĩte Aroeri, mũthia-inĩ wa kĩanda kĩa Arinoni ũgakinya kĩrĩma-inĩ kĩa Sirioni (na nĩkĩo Herimoni),
49 Àti gbogbo aginjù ní ìlà-oòrùn Jordani títí dé Òkun Iyọ̀ ní ìsàlẹ̀ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Pisga.
na ũkanyiita Araba guothe mwena wa irathĩro rĩa Rũũĩ rwa Jorodani, o nginya iria rĩa Araba, mũhuro wa iharũrũka cia Pisiga.