< Deuteronomy 34 >
1 Nígbà náà ni Mose gun òkè Nebo láti pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu sí orí Pisga tí ó dojúkọ Jeriko. Níbẹ̀ ni Olúwa ti fi gbogbo ilẹ̀ hàn án láti Gileadi dé Dani,
Niañambone ty vohi-Nìbo amy zao t’i Mosè, boak’ an-tanemira’ i Moabe pak’ antiotio’ i Pisgà, tandrife Ieriko; vaho natoro’ Iehovà aze i hene taney—boake Gilade pake Dane;
2 gbogbo Naftali, ilẹ̀ Efraimu àti Manase, gbogbo ilẹ̀ Juda títí dé Òkun Ńlá,
le i Naftalý iaby, naho ty tane’ i Efraime, naho ty a i Menasè, naho ze hene tane’ Iehoda pak’ amy riak’ ahandrefañey
3 gúúsù àti gbogbo àfonífojì Jeriko, ìlú ọlọ́pẹ dé Soari.
naho i Atimoy, naho ty tane pisak’ am-bavatane’ Ieriko ey, i rovan-tsatrañey pake Tsoare.
4 Nígbà náà ní Olúwa sọ fún un pé, “Èyí ni ilẹ̀ tí mo ṣèlérí lórí ìbúra fún Abrahamu, Isaaki, àti Jakọbu nígbà tí mo wí pé, ‘Èmi yóò fi fún irú-ọmọ rẹ.’ Mo ti jẹ́ kí o rí i pẹ̀lú ojú rẹ, ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò dé bẹ̀.”
Le hoe t’Iehovà ama’e, Ingo ty tane nifantàko amy Avrahame naho am’ Ietsàke naho am’ Iakobe ami’ty hoe, Hatoloko amo tarira’oo; nampahaisahako azo am-pihaino’o f’ie tsy hitsake mb’eo.
5 Bẹ́ẹ̀ ni Mose ìránṣẹ́ Olúwa kú ní ilẹ̀ Moabu, bí Olúwa ti wí.
Aa le nihomak’ an-tane Moabe eo t’i Mosè, mpitoro’ Iehovà ami’ty tsara’ Iehovà;
6 Ó sì sin ín nínú àfonífojì ní ilẹ̀ Moabu, ní òdìkejì Beti-Peori, ṣùgbọ́n títí di òní yìí, kò sí ẹnìkan tí ó mọ ibi tí ibojì i rẹ̀ wà.
vaho nalente’e am-bavatane an-tane’ i Moabe tandrife i Bet’peore ao, fe tsy fohi’ ondaty pake henane i kibori’ey.
7 Mose jẹ́ ẹni ọgọ́fà ọdún nígbà tí ó kú, síbẹ̀ ojú rẹ̀ kò ṣe bàìbàì bẹ́ẹ̀ ni agbára rẹ̀ kò dínkù.
Zato-tsi-roapolo-taoñe t’i Mosè te nihorogodoboke, tsy nirombitse o fihaino’eo, vaho tsy niketrake ty haozara’e.
8 Àwọn ọmọ Israẹli sọkún un Mose ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu ní ọgbọ̀n ọjọ́ títí di ìgbà tí ọjọ́ ẹkún àti ọ̀fọ̀ Mose parí.
Nandala aze telo-polo andro an-tanemira’ i Moabe eo o ana’ Israeleo, am’ para’ te niritse o andro firovetañe naho fandalàñeo.
9 Joṣua ọmọ Nuni kún fún ẹ̀mí ọgbọ́n nítorí Mose ti gbọ́wọ́ ọ rẹ̀ lé e lórí. Àwọn ọmọ Israẹli sì fetí sí i wọ́n sì ṣe ohun tí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
Nilifotse ty arofon-kihitse t’Iehosoa ana’ i None; ami’ty nanampeza’ i Mosè fitàñe, le nitsendreñe aze o ana’ Israeleo, vaho nanoe’ iareo ze nandilia’ Iehovà i Mosè.
10 Láti ìgbà náà kò sì sí wòlíì tí ó dìde ní Israẹli bí i Mose, ẹni tí Olúwa mọ̀ lójúkojú,
Ampara’ izay tsy teo ty mpitoky nitroatse e Israele ao nañirinkiriñe i Mosè, ie niarofoana’ Iehovà am-piatrefan-daharañe,
11 tí ó ṣe gbogbo iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu tí Olúwa rán an láti lọ ṣe ní Ejibiti sí Farao àti sí gbogbo àwọn ìránṣẹ́ ẹ rẹ̀ àti sí gbogbo ilẹ̀ náà.
amo hene viloñe naho raha tsitantane nañiraha’ Iehovà aze hanoe’e an-tane Mitsraime ao amy Paro naho amo mpitoro’e iabio vaho amy hene tane’ey;
12 Nítorí kò sí ẹni tí ó tí ì fi gbogbo ọ̀rọ̀ agbára hàn, tàbí ṣe gbogbo ẹ̀rù ńlá tí Mose fihàn ní ojú gbogbo Israẹli.
am-pitàñe ra’elahy an-kaozarañe naho amy fampangetraketrahañe folo’ay naboa’ i Mosè am-pahaisaha’ o ana’ Israele iabioy.