< Deuteronomy 33 >

1 Èyí ni ìbùkún tí Mose ènìyàn Ọlọ́run bùkún fún àwọn ọmọ Israẹli kí ó tó kú.
Pathen kah hlang Moses loh a duek hlanah tahae kah yoethennah he Israel ca rhoek taengah yoethen la a paek.
2 Ó sì wí pé, “Olúwa ti Sinai wá, ó sì yọ sí wọn láti Seiri wá ó sì tàn án jáde láti òkè Parani wá. Ó ti ọ̀dọ̀ ẹgbẹgbàarùn-ún àwọn mímọ́ wá láti ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ ni òfin kan a mú bí iná ti jáde fún wọn wá.
BOEIPA tah Sinai lamloh halo tih Seir lamloh thoeng. Amih ham Paran tlang lamloh a sae pah tih a bantang lamloh hlangcim a thawngsang neh thoeng. Amih ham olkhan hmai a khuen.
3 Nítòótọ́, ó fẹ́ràn àwọn ènìyàn an rẹ̀, gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́ wà ní ọwọ́ rẹ̀. Ní ẹsẹ̀ rẹ̀ ni wọ́n ti foríbalẹ̀, àti lọ́dọ̀ rẹ̀ ni wọ́n ti ń gba ọ̀rọ̀,
Na kut dongkah a hlangcim boeih loh pilnam a lungnah tih, na oluennah aka duen loh na kho taengah ngolhlung uh.
4 òfin tí Mose fi fún wa, ìní ti ìjọ ènìyàn Jakọbu.
Jakob vangpum kah khoh la olkhueng he, Moses loh mamih taengah ng'uen coeng.
5 Òun ni ọba lórí Jeṣuruni ní ìgbà tí olórí àwọn ènìyàn péjọpọ̀, pẹ̀lú àwọn ẹ̀yà Israẹli.
Jeshurun ah manghai la a om vaengah pilnam kah a lu rhoek loh Israel koca rhoek taengla tingtun uh.
6 “Jẹ́ kí Reubeni yè kí ó má ṣe kú, tàbí kí ènìyàn rẹ mọ níwọ̀n.”
Reuben tah hing mai saeh lamtah duek boel saeh. Anih te hlang sii la om boel saeh.
7 Èyí ni ohun tí ó sọ nípa Juda: “Olúwa gbọ́ ohùn Juda kí o sì mú tọ àwọn ènìyàn rẹ̀ wá. Kí ọwọ́ rẹ̀ kí ó tó fún un, kí ó sì ṣe ìrànlọ́wọ́ fún lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá rẹ̀!”
Judah kawng dongah he khaw, “Aw BOEIPA Judah ol he hnatun lamtah a pilnam taengla thak lah. Amah pum te a kut neh a huul vaengah a rhal khui lamkah khaw bomkung la nang om pah lah,” a ti.
8 Ní ti Lefi ó wí pé, “Jẹ́ kí Tumimu àti Urimu rẹ kí ó wà pẹ̀lú ẹni mímọ́ rẹ. Ẹni tí ó dánwò ní Massa, ìwọ bá jà ní omi Meriba.
Levi kawng dongah khaw, “Na Thummim neh na Urim he, Massah ah na noemcai tih, Meribah tui taengah na oelh tangtae, na hlang cim hut coeng ni,” a ti.
9 Ó wí fún baba àti ìyá rẹ pé, ‘Èmi kò buyì fún wọn.’ Kò mọ àwọn arákùnrin rẹ̀, tàbí mọ àwọn ọmọ rẹ̀, ṣùgbọ́n ó dúró lórí ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó sì pa májẹ̀mú rẹ̀ mọ́.
“A manu neh a napa ka phoe pawh,” a ti tih, a manuca khaw a hmat mueh la a ca kah a ca due ming voel pawh. Tedae na olthui te a ngaithuen uh tih na paipi te a kueinah uh.
10 Ó kọ́ Jakọbu ní ìdájọ́ rẹ̀ àti Israẹli ní òfin rẹ̀. Ó mú tùràrí wá síwájú rẹ̀ àti ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ẹbọ sísun sórí i pẹpẹ rẹ̀.
Nang kah laitloeknah te Jakob ham neh, na olkhueng te Israel ham a thuinuet pa uh. Na hmai ah hmueihul neh, na hmueihtuk ah boeih a khueh uh.
11 Bùsi ohun ìní rẹ̀, Olúwa, kí o sì tẹ́wọ́gbà iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀. Lu ẹgbẹ́ àwọn tí ó dìde sí i; àwọn tí ó kórìíra rẹ̀, kí wọn kí ó má ṣe dìde mọ́.”
Aw BOEIPA anih kah a thadueng te yoethen pae lamtah, a kut dongkah a bisai khaw uum pah. Anih aka thoh thil kah a cinghen te phop pah lamtah, a lunguet rhoek khaw thoo uh boel saeh.
12 Ní ti Benjamini ó wí pé, “Jẹ́ kí olùfẹ́ Olúwa máa gbé ní àlàáfíà lọ́dọ̀ rẹ̀, òun a máa bò ó ní gbogbo ọjọ́, ẹni tí Olúwa fẹ́ràn yóò máa sinmi láàrín èjìká rẹ̀.”
Benjamin kawng dongah, “BOEIPA kah lungnah tah, anih pum dongah ngaikhuek la rhaehrhong saeh. Hnin takuem ah anih te muekdah saeh lamtah, a laengpang laklo ah cu saeh,” a ti.
13 Ní ti Josẹfu ó wí pé, “Kí Olúwa bùkún ilẹ̀ rẹ, fún ohun iyebíye láti ọ̀run pẹ̀lú ìrì àti ibú tí ó ń bẹ níṣàlẹ̀;
Joseph kawng dongah, “A khohmuen te BOEIPA loh vaan cangtham, buemtui, tuidung laedil kah aka kol,
14 àti fún èso iyebíye tí ọ̀run mú wá àti ti ohun iyebíye tí ń dàgbà ní oṣooṣù;
khomik dongkah cangvuei cangtham, hla dongkah hicil cangtham,
15 pẹ̀lú ohun pàtàkì òkè ńlá ìgbàanì àti fún ohun iyebíye ìgbà ayérayé;
hlamat kah tlang som, kumhal som kah cangtham nen khaw,
16 Pẹ̀lú ohun iyebíye ayé àti ẹ̀kún un rẹ̀ àti fún ìfẹ́ ẹni tí ó ń gbé inú igbó. Jẹ́ kí gbogbo èyí sinmi lé orí Josẹfu, lórí àtàrí ẹni tí ó yàtọ̀ láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀.
diklai cangtham a soeprhaep nen khaw yoethen a paek. Te dongah tangpuem khuikah aka om kolonah te, Joseph lu neh a manuca hlangcoelh rhoek kah a luki ah na cuuk sak.
17 Ní ọláńlá ó dàbí àkọ́bí akọ màlúù; ìwo rẹ̀, ìwo àgbáǹréré ni. Pẹ̀lú wọn ni yóò fi ti àwọn orílẹ̀-èdè, pàápàá títí dé òpin ayé. Àwọn sì ni ẹgbẹẹgbàárùn mẹ́wàá Efraimu, àwọn sì ni ẹgbẹẹgbẹ̀rún Manase.”
A rhuepomnah vaito cacuek neh a cung ki loh pilnam neh Ephraim a thawng a sang, Manasseh a thawng a sang te, diklai khobawt duela a thoeh rhenten ni,” a ti.
18 Ní ti Sebuluni ó wí pé, “Yọ̀ Sebuluni, ní ti ìjáde lọ rẹ, àti ìwọ Isakari, nínú àgọ́ rẹ.
Zebulun kawng dongah khaw, “Zebulun nang na coe tih na dap khuiah Issakhar a om te na kohoe sak lah.
19 Wọn yóò pe àwọn ènìyàn sórí òkè àti níbẹ̀ wọn yóò rú ẹbọ òdodo, wọn yóò mu nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ Òkun, nínú ìṣúra tí ó pamọ́ nínú iyanrìn.”
Tlang kah pilnam rhoek te khue uh pahoi lamtah, duengnah hmueih nawn uh saeh. Te vaengah tuitunli khuehtawn neh laivin khuiah a thuh tih, a tung te cop uh saeh,” a ti.
20 Ní ti Gadi ó wí pé, “Ìbùkún ni ẹni tí ó mú Gadi gbilẹ̀! Gadi ń gbé níbẹ̀ bí kìnnìún, ó sì fa apá ya, àní àtàrí.
Gad kawng dongah khaw, “Sathuengnu bangla phuel uh tih, aka om Gad loh a yoethen tih, a lu pataeng a ban neh a phuet.
21 Ó sì yan ilẹ̀ tí ó dára jù fún ara rẹ̀; ìpín olórí ni a sì fi fún un. Nígbà tí ó rí tí gbogbo àwọn ènìyàn péjọ, ó mú òdodo Olúwa ṣẹ, àti ìdájọ́ rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ọmọ Israẹli.”
A tanglue te amah ham a sawt tih, pilnam kah a lu rhoek halo uh vaengah, khamyai aka taem te sul a bung thil. BOEIPA kah duengnah neh Israel taengah, laitloeknah a saii,” a ti.
22 Ní ti Dani ó wí pé, “Ọmọ kìnnìún ni Dani, tí ń fò láti Baṣani wá.”
Dan kawng khaw, “Dan he sathueng ca bangla, Bashan lamloh cungpet,” a ti.
23 Ní ti Naftali ó wí pé, “Ìwọ Naftali, kún fún ojúrere Ọlọ́run àti ìbùkún Olúwa; yóò jogún ìhà ìwọ̀-oòrùn àti gúúsù.”
Naphtali kawng dongah, “Naphtali nang tah, BOEIPA kah kolonah neh yoethennah te, ngaikhuek la a baetawt dongah, tuitunli neh tuithim khaw na pang,” a ti.
24 Ní ti Aṣeri ó wí pé, “Ìbùkún ọmọ ni ti Aṣeri; jẹ́ kí ó rí ojúrere láti ọ̀dọ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀ kí ó sì ri ẹsẹ̀ rẹ̀ sínú òróró.
Asher kawng dongah khaw, “Asher koca rhoek loh a yoethen. A manuca rhoek taengah a kolo om saeh lamtah a kho te situi khuiah nuem saeh,” a ti.
25 Bàtà rẹ̀ yóò jẹ́ irin àti idẹ, agbára rẹ̀ yóò sì rí bí ọjọ́ rẹ̀.
Thicung neh rhohum he na thohkalh la om lamtah, na khohnin bangla na thaa om saeh.
26 “Kò sí ẹlòmíràn bí Ọlọ́run Jeṣuruni, ẹni tí ń gun ọ̀run fún ìrànlọ́wọ́ rẹ àti ní ojú ọ̀run nínú ọláńlá rẹ̀.
Vaan ke a ngol thil tih, nang ham bomkung la om. Te dongah a hoemnah neh khomong dongah aka om, Jeshurun kah Pathen bang he a om moenih.
27 Ọlọ́run ayérayé ni ibi ìsádi rẹ, àti ní ìsàlẹ̀ ni apá ayérayé wà. Yóò lé àwọn ọ̀tá rẹ níwájú rẹ, ó sì wí pé, ‘Ẹ máa parun!’
Hlamat Pathen kah a khuisaek neh, kumhal bantha hmuiah ah tah, thunkha khaw na mikhmuh lamkah a haek vetih, mitmoeng sak a ti bitni.
28 Israẹli nìkan yóò jókòó ní àlàáfíà, orísun Jakọbu nìkan ní ilẹ̀ ọkà àti ti ọtí wáìnì, níbi tí ọ̀run ti ń sẹ ìrì sílẹ̀.
Te vaengah Jakob kah a mik Israel bueng ni, cangpai neh misur thai kho ah ngaikhuek kho a sak vetih, vaan buemtui long khaw a tlan thil eh.
29 Ìbùkún ni fún ọ, Israẹli, ta ni ó dàbí rẹ, ẹni tí a gbàlà láti ọ̀dọ̀ Olúwa? Òun ni asà àti ìrànwọ́ rẹ̀ àti idà ọláńlá rẹ̀. Àwọn ọ̀tá rẹ yóò tẹríba fún ọ, ìwọ yóò sì tẹ ibi gíga wọn mọ́lẹ̀.”
Israel nang tah na yoethen pai. Nang kah bomkung photling neh na hoemnah cunghang, BOEIPA loh nang bangla u bang pilnam nim a khang coeng. Te dongah na thunkha loh nang hmaiah mai a tum uh vetih amih kah hmuensang soah na cangdoek bitni.

< Deuteronomy 33 >