< Deuteronomy 31 >

1 Nígbà náà ni Mose jáde tí ó sì sọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí sí gbogbo Israẹli pé,
Moses te cet tih Israel pum taengah hekah olka he a thui.
2 “Mo jẹ́ ọmọ ọgọ́fà ọdún báyìí àti pé èmi kò ni lè darí i yín mọ́. Olúwa ti sọ fún mi pé, ‘Ìwọ kò ní kọjá Jordani.’
Te vaengah amih te, “Tihnin ah kai he kum ya pakul ka lo ca coeng tih ka voei ka bal ham ka coeng voel pawh. Te dongah BOEIPA loh kai taengah, ‘He Jordan he kat voel boeh,’ a ti.
3 Olúwa Ọlọ́run rẹ fúnra rẹ̀ ni yóò rékọjá fún ọ. Yóò pa àwọn orílẹ̀-èdè yìí run níwájú rẹ, ìwọ yóò sì mú ìní ilẹ̀ wọn, Joṣua náà yóò rékọjá fún ọ, bí Olúwa ti sọ.
Na hmai kah aka kat BOEIPA na Pathen amah loh namtom rhoek he na mikhmuh ah a mitmoeng sak vetih amih te na pang ni. BOEIPA loh a thui vanbangla Joshua tah nang hmai ah kat ni.
4 Olúwa yóò sì ṣe fún wọn ohun tí ó ti ṣe sí Sihoni àti sí Ogu ọba Amori, tí ó parun pẹ̀lú ilẹ̀ ẹ wọn.
Amori manghai Sihon neh Oga a saii tih a khohmuen neh rhenten a phae bangla BOEIPA loh a saii ni.
5 Olúwa yóò fi wọ́n fún ọ, kí o sì ṣe sí wọn gbogbo èyí tí mo ti pàṣẹ fún ọ.
Amih te BOEIPA loh na mikhmuh la han thak vaengah nang kang uen olpaek bangla amih taengah boeih na saii ni.
6 Jẹ́ alágbára kí o sì ní ìgboyà. Má ṣe bẹ̀rù tàbí jáyà nítorí i wọn, nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ ń lọ pẹ̀lú rẹ, Òun kò ní fi ọ́ sílẹ̀ tàbí kọ̀ ọ́ sílẹ̀.”
Thahuel uh lamtah namning sak uh. Amih maelhmai te rhih uh boel lamtah na sarhing uh boeh. Nang taengkah aka cet BOEIPA na Pathen loh nang ng'rhael pawt vetih nang ng'hnoo mahpawh,” a ti nah.
7 Nígbà náà ni Mose pe Joṣua ó sì wí fún un níwájú gbogbo Israẹli pé, “Jẹ́ alágbára àti onígboyà, nítorí o ní láti lọ pẹ̀lú àwọn ènìyàn wọ̀nyí sí ilẹ̀ tí Olúwa búra fún àwọn baba ńlá a wọn láti fún wọn, kí o sì pín ilẹ̀ náà láàrín wọn bí ogún wọn.
Te phoeiah Moses loh Joshua a khue tih Israel pum kah mikhmuh ah, “Thahuel lamtah namning sak. A napa taengah paek hamla BOEIPA loh a toemngam tangtae khohmuen la pilnam neh na puei uh vetih amih te na pang pawn ni.
8 Olúwa fúnra rẹ̀ ń lọ níwájú rẹ yóò sì wà pẹ̀lú rẹ; kò ní fi ọ́ sílẹ̀ tàbí kọ̀ ọ́ sílẹ̀. Má ṣe bẹ̀rù má sì ṣe fòyà.”
Nang mikhmuh ah aka pongpa BOEIPA amah long he nang taengah om vetih nang ng'rhael mahpawh, nang ng'hnoo mahpawh. Rhih boel lamtah rhihyawp boeh,” a ti nah.
9 Nígbà náà ni Mose kọ òfin yìí kalẹ̀ ó sì fi fún àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, tí ń gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti fún gbogbo àwọn àgbàgbà ní Israẹli.
Te phoeiah olkhueng he Moses loh a daek tih, BOEIPA kah paipi thingkawng aka kawt, Levi koca khosoih rhoek neh Israel patong rhoek boeih taengah a paek.
10 Nígbà náà ni Mose pàṣẹ fún wọn, “Ní òpin ọdún méje méje, ní àkókò ọdún ìdásílẹ̀, nígbà àjọ àwọn àgọ́.
Hekah he kum rhih thok tih pohlip khotue laiba hlahnah kum kah khoning vaengah a thui tih amih te Moses loh a uen.
11 Nígbà tí gbogbo Israẹli bá wá láti fi ara hàn níwájú Olúwa Ọlọ́run wa ní ibi tí yóò yàn, ìwọ yóò ka òfin yìí níwájú wọn sí etí ìgbọ́ wọn.
Amah hmuen tuek kah BOEIPA na Pathen mikhmuh ah phoe hamla Israel pum loh ha pawk vaengah Israel pum kah a hna kaep ah olkhueng he doek pah.
12 Pe àwọn ènìyàn jọ àwọn ọkùnrin, àwọn obìnrin àti àwọn àjèjì tí ń gbé àwọn ìlú u yín kí wọn lè fetí sí i kí wọn sì lè kọ́ láti bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run rẹ kí wọn sì rọra tẹ̀lé gbogbo ọ̀rọ̀ òfin yìí.
Huta tongpa camoe, na vongka kah yinlai neh pilnam loh tingtun saeh lamtah hnatun uh saeh. Te daengah ni a cang uh vetih BOEIPA na Pathen rhih ham neh olkhueng ol boeih he vai hamla a ngaithuen uh eh.
13 Àwọn ọmọ wọn tí wọn kò mọ òfin yìí, gbọdọ̀ gbọ́ kí wọn sì kọ́ láti bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run rẹ níwọ̀n ìgbà tí o tí ń gbé ní ilẹ̀ tí ò ń kọjá la Jordani lọ láti ni.”
Te vaengah pang hamla Jordan na kat thil khohmuen kah na hingnah tue khuiah ah aka ming noek pawh a ca rhoek loh BOEIPA na Pathen rhih ham hnatun uh saeh lamtah cang uh saeh.
14 Olúwa sọ fún Mose pé, “Ọjọ́ ikú rẹ ti súnmọ́ etílé báyìí. Pe Joṣua kí ẹ sì fi ara yín hàn nínú àgọ́ àjọ, níbi tí èmi yóò ti fi àṣẹ fún un.” Nígbà náà ni Mose àti Joṣua wá, wọ́n sì fi ara wọn hàn níbi àgọ́ àjọ.
Te vaengah BOEIPA loh Moses te, “Duek hamla na khohnin loh yoei coeng he. Joshua te khue lamtah tingtunnah dap ah pai sak lamtah anih te ka uen eh,” a ti nah. Te dongah Moses neh Joshua te cet rhoi tih tingtunnah dap ah pai rhoi.
15 Nígbà náà ni Olúwa farahàn níbi àgọ́ ní ọ̀wọ́ àwọsánmọ̀, àwọsánmọ̀ náà sì dúró sókè ẹnu-ọ̀nà àgọ́.
Te vaengah BOEIPA tah dap ah cingmai tung la tueng tih cingmai tung khaw dap thohka ah pai.
16 Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Ìwọ ń lọ sinmi pẹ̀lú àwọn baba à rẹ, àwọn wọ̀nyí yóò sì ṣe àgbèrè ara wọn sí ọlọ́run àjèjì ilẹ̀ tí wọn ń wọ̀ lọ láìpẹ́. Wọn yóò kọ̀ mí sílẹ̀ wọn yóò sì da májẹ̀mú tí mo bá wọn dá.
Te vaengah Moses te BOEIPA loh, “Na pa rhoek taengah na yalh coeng atah pilnam he thoo vetih a kun thil khohmuen kah kholong pathen taengah cukhalh pawn ni he. Kai n'hnoo vetih anih taengkah ka saii ka paipi he a phae uh ni.
17 Ní ọjọ́ náà ni èmi yóò bínú sí wọn èmi yóò sì kọ̀ wọ́n sílẹ̀; èmi yóò pa ojú mi mọ́ kúrò fún wọn, wọn yóò sì parun. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àjálù àti ìṣòro yóò wá sórí wọn, àti ní ọjọ́ náà ni wọn yóò béèrè pé, ‘Ǹjẹ́ ìpọ́njú wọ̀nyí kò wá sórí i wa nítorí Ọlọ́run wa kò sí pẹ̀lú u wa?’
Tekah khohnin ah tah ka thintoek loh anih taengah sai vetih amih te ka hnoo ni. Te vaengah amih taeng lamloh ka maelhmai ka thuh vetih maeham la poeh ni. Yoethae cungkuem neh citcai loh anih a hmuh ni. Te khohnin ah, ‘Ka khui ah ka Pathen loh a om pawt dongah pawt nim? He bang yoethae loh kai m'hmuh,’ a ti ni.
18 Èmi yóò sì pa ojú mi mọ́ dájúdájú ní ọjọ́ náà nítorí i gbogbo ìwà búburú wọn ní yíyípadà sí ọlọ́run mìíràn.
Boethae cungkuem te a saii tih pathen tloe rhoek taengah a hooi uh khohnin van vaengah kai long khaw ka maelhmai ka thuh rhoe ka thuh tak van ni.
19 “Ní báyìí kọ ọ́ kalẹ̀ fúnra à rẹ orin yìí kí o sì kọ ọ́ sí Israẹli kí o sì jẹ́ kí wọn kọ ọ́ kí ó lè jẹ́ ẹ̀rí ì mi sí wọn.
Te dongah hekah laa he namah loh daek laeh. Israel ca rhoek te tuuk lamtah a ka dongah hoei pah. Te daengah ni hekah laa loh Israel ca rhoek taengah kai kah laipai la a om eh.
20 Nígbà tí mo ti mú wọn wá sí ilẹ̀ tí ń sàn fún wàrà àti fún oyin, ilẹ̀ tí mo ti ṣe ìlérí ní ìbúra fún àwọn baba ńlá wọn, àti nígbà tí wọ́n bá jẹ, tí ó sì tẹ́ wọn lọ́rùn, tí wọ́n sì gbilẹ̀, wọn yóò yí padà sí ọlọ́run mìíràn wọn yóò sì sìn wọ́n, wọn yóò kọ̀ mí sílẹ̀, wọn yóò sì da májẹ̀mú mi.
A napa rhoek taengah ka toemngam tangtae tih, khoitui neh suktui aka long khohmuen la ka khuen ni. Te vaengah kodam la ca khangrhang cakhaw pathen tloe taengla hooi uh vetih amih taengah ni tho a thueng uh eh. Kai yah m'bai uh vetih ka paipi a phae uh mai hoeh veh.
21 Àti nígbà tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìpọ́njú àti ìṣòro bá wá sórí i wọn, orin yìí yóò jẹ́ ẹ̀rí sí wọn, nítorí kò ní di ìgbàgbé fún àwọn ọmọ wọn. Mo mọ̀ ohun tí wọ́n ní inú dídùn sí láti ṣe, pàápàá kí èmi tó mú wọn wá sí ilẹ̀ tí mo ṣe ìlérí fún wọn lórí ìbúra.”
Tedae ana om saeh, anih te yoethae neh citcai loh muep a muk van vaengah hekah laa loh a mikhmuh ah laipai la a doo bitni. A tiingan ka lamkah te khaw hnilh boel saeh. Ka toemngam bangla anih te khohmuen la ka pha puei hlan ah pataeng tihnin kah a saii neh a benbonah te ka ming,” a ti nah.
22 Nígbà náà ni Mose kọ orin yìí kalẹ̀ ní ọjọ́ náà ó sì kọ ọ́ sí Israẹli.
Te dongah laa he Moses loh amah khohnin vaengah a daek tih Israel ca rhoek te a cang puei.
23 Olúwa sì fún Joṣua ọmọ Nuni ní àṣẹ yìí: “Jẹ́ alágbára àti onígboyà, nítorí ìwọ yóò mú Israẹli wá sí ilẹ̀ tí mo ṣèlérí fún wọn lórí ìbúra, èmi fúnra à mi yóò sì wà pẹ̀lú rẹ.”
Te phoeiah Nun capa Joshua te a uen tih, “Amih ham ka toemngam tangtae khohmuen la Israel ca rhoek te na khuen ham coeng dongah thahuel lamtah namning sak. Nang taengah kai ka om bitni,” a ti nah.
24 Lẹ́yìn ìgbà tí Mose ti parí i kíkọ ọ̀rọ̀ òfin yìí sínú ìwé láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin,
Olkhueng ol he a soep hil cabu dongah daek ham te Moses loh a coeng tih om coeng.
25 ó sì fi àṣẹ yìí fún àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n ń gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa:
Te phoeiah BOEIPA kah paipi thingkawng aka kawt Levi rhoek te Moses loh a uen tih,
26 “Gba ìwé òfin yìí kí o sì fi sí ẹ̀gbẹ́ àpótí ẹ̀rí Olúwa Ọlọ́run rẹ. Níbẹ̀ ni yóò wà bí ẹ̀rí sí ọ.
“Olkhueng cabu he lo laeh. BOEIPA na Pathen paipi thingkawng kaep ah khueh lamtah nang taengah laipai la om saeh.
27 Nítorí mo mọ irú ọlọ̀tẹ̀ àti ọlọ́rùn líle tí ẹ jẹ́. Bí o bá ṣe ọlọ̀tẹ̀ sí Olúwa nígbà tí mo pàpà wà láyé pẹ̀lú yín, báwo ní ẹ ó ti ṣe ọlọ̀tẹ̀ tó nígbà tí mo bá kú tán!
Na boekoek neh na rhawn a mangkhak khaw kai loh ka ming. Nangmih taengkah ka hing tue vaengah pataeng BOEIPA aka koek la na om uh atah ka duek phoei aisat oeih.
28 Ẹ péjọpọ̀ síwájú mi gbogbo àgbà ẹ̀yà yín àti àwọn aláṣẹ yín, kí èmi lè sọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí sí etí ìgbọ́ ọ́ wọn.
Nangmih koca kah patong rhoek neh na rhoiboei boeih loh kai taengla ha tingtun uh laeh. Vaan neh diklai he amih taengah ka laipai puei saeh lamtah a hna ah olka he ka thui lah eh.
29 Nítorí tí mo mọ̀ pé lẹ́yìn ikú mi, ó dájú pé ìwọ yóò padà di ìbàjẹ́ pátápátá, ẹ ó sì yípadà kúrò ní ọ̀nà tí mo ti pàṣẹ fún un yín. Ní ọjọ́ tó ń bọ̀, ìpọ́njú yóò sọ̀kalẹ̀ sórí i yín nítorí ẹ̀yin yóò ṣe búburú níwájú Olúwa ẹ ó sì mú u bínú nípa ohun tí ọwọ́ yín ti ṣe.”
Ka dueknah hnukah khaw ka ming coeng. A po la na po vetih nangmih taengah kang uen bangla longpuei lamloh na nong uh ni. Hmailong khohnin ah yoethaenah loh nangmih m'mah ni. Na kut dongkah khoboe neh amah veet hamla BOEIPA mikhmuh ah boethae ni na saii uh eh.”
30 Mose sì ka ọ̀rọ̀ inú orin yìí láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin sí etí ìgbọ́ ọ gbogbo ìjọ Israẹli:
Te dongah hekah laa lung he a boeih due Israel hlangping boeih kah a hna ah Moses loh a thui pah.

< Deuteronomy 31 >