< Deuteronomy 30 >

1 Nígbà tí gbogbo ìbùkún àti ègún wọ̀nyí tí mo ti gbé kalẹ̀ síwájú u yín bá wá sórí i yín àti tí o bá mú wọn sí àyà rẹ níbikíbi tí Olúwa Ọlọ́run rẹ bá tú ọ ká sí láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
BAWIPA Cathut ni na hreknae miphunnaw pueng koe kaawm e na hmalah ka hruek e yawhawinae hoi thoebonae hah na panue awh teh,
2 àti nígbà tí ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ bá yípadà sí Olúwa Ọlọ́run rẹ tí o sì gbọ́rọ̀ sí pẹ̀lú gbogbo àyà rẹ àti gbogbo ọkàn rẹ gẹ́gẹ́ bí gbogbo ohun tí mo ti paláṣẹ fún un yín lónìí.
BAWIPA koe bout na ban awh teh, atu kâ na poe e patetlah nama hoi na canaw hoi na lungthin, hringnae abuemlahoi a lawk na tarawi awh pawiteh,
3 Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò mú ohun ìní rẹ bọ̀ sípò yóò sì ṣàánú fún ọ, yóò sì tún ṣà yín jọ láti gbogbo orílẹ̀-èdè níbi tí ó ti fọ́n yín ká sí.
BAWIPA Cathut ni san coungnae koehoi na ban sak awh vaiteh, na pahren awh han. Hahoi BAWIPA ni miphun pueng koe kâkayeinae koehoi bout na pâkhueng awh han.
4 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ti lé ẹni rẹ kan sí ilẹ̀ tí ó jìnnà jù lábẹ́ ọ̀run, láti ibẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò ṣà yín jọ yóò sì tún mú u yín padà.
Nangmouh thung dawk talai pout totouh pâlei e awm pawiteh, BAWIPA na Cathut ni hote hmuen koehoi bout na pâkhueng awh vaiteh, hote hmuen koehoi bout na tâcokhai awh han.
5 Yóò mú ọ wá sí ilẹ̀ tí ó jẹ́ ti àwọn baba yín, ìwọ yóò sì mú ìní níbẹ̀. Olúwa yóò mú ọ wà ní àlàáfíà kíkún, yóò mú ọ pọ̀ sí i ju àwọn baba yín lọ.
Mintoenaw ni a pang e ram koelah, bout na hrawi awh vaiteh, na pang a han. Hatnavah bout na pahren awh vaiteh mintoenaw hlak hoe na pung sak han.
6 Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò kọ ọkàn rẹ ní ilà àti ọkàn àwọn ọmọ yín, nítorí kí o lè fẹ́ ẹ pẹ̀lú gbogbo àyà rẹ pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ, àti ayé rẹ.
Na hring thai nahan, BAWIPA na Cathut hah lungthin, hringnae abuemlahoi lungpataw sak hanlah, BAWIPA na Cathut ni na lungthin hoi na catounnaw e lungthin vuensom a a pouh han.
7 Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò mú gbogbo ègún yín wá sórí àwọn ọ̀tá à rẹ tí wọ́n kórìíra àti tí wọ́n ṣe inúnibíni rẹ.
Nang na ka taran ni teh na kapacekpahleknaw, lathueng hai thoseh, ka dei tangcoung patetlah thoebonae pueng ka pha sak han.
8 Ìwọ yóò tún gbọ́rọ̀ sí Olúwa àti tẹ̀lé gbogbo àṣẹ rẹ̀ tí mò ń fún ọ lónìí.
Bout na ban vaiteh, BAWIPA e a lawk dei e na tarawi vaiteh, sahnin na poe e kâpoelawknaw pueng na tarawi awh han.
9 Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò mú ọ ṣe rere nínú gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ ọ̀ rẹ, àti nínú gbogbo ọmọ inú rẹ, agbo ẹran ọ̀sìn rẹ àti èso ilẹ̀ rẹ. Olúwa yóò tún mú inú dídùn sínú rẹ yóò sì mú ọ ṣe déédé, gẹ́gẹ́ bí ó ti fi inú dídùn sínú àwọn baba rẹ.
Nang ni na BAWIPA Cathut e lawk hah na tarawi teh,
10 Bí o bá gbọ́ ti Olúwa Ọlọ́run rẹ tí o sì pa òfin rẹ̀ mọ́ àti àṣẹ tí a kọ sínú ìwé òfin yìí kí o sì yípadà sí Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀lú gbogbo àyà rẹ àti pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ.
kâlawk cauk dawk thut e lah kaawm e phunglawk pueng na tarawi pawiteh, na BAWIPA Cathut koe na lungthin abuemlahoi bout na ban pawiteh, na tawk e pueng dawk tânae na hmu awh nahan hoi na canaw, saringnaw, apawhiknaw pung sak vaiteh, nang han hawinae na sak pouh han. BAWIPA teh na mintoenaw koe a lunghawi e patetlah nang dawk a lunghawi vaiteh, nang hanelah ahawinae lah a sak han.
11 Nítorí àṣẹ yìí tí mo pa fún ọ lónìí, kò ṣòro jù fún ọ, bẹ́ẹ̀ ni kò kọjá agbára rẹ.
Sahnin na poe e lawk teh na thaipanuek hoeh e lawk nahoeh.
12 Kò sí ní ọ̀run, tí ìwọ kò bá fi wí pé, “Ta ni yóò gòkè lọ sí ọ̀run fún wa, tí yóò sì mú wa fún wa, kí àwa lè gbọ́, kí a sì le ṣe é?”
Nang hoi kâhlat hoeh. A lawk ngâi awh teh tarawi nahanelah, kalvan vah apimouh ka luen vaiteh, maimouh koe ka thokhai tie hah pacei sak hanelah kalvan vah kaawm e nahoeh.
13 Bẹ́ẹ̀ ni kò sí ní ìhà kejì Òkun, tí ìwọ ìbá fi wí pé, “Ta ni yóò rékọjá òkun lọ fún wa, tí yóò sì mú un wá fún wa, kí àwa lè gbọ́ ọ, kí a si le ṣe é?”
A lawk teh maimouh ni ngâi awh teh, tarawi awh nahan, talî apimaw ka rakat ni teh maimouh koe ka thokhai han telah ka pacei hanelah talî namran lah kaawm e nahoeh.
14 Kì í ṣe bẹ́ẹ̀, ọ̀rọ̀ náà súnmọ́ tòsí rẹ, ó wà ní ẹnu rẹ àti ní ọkàn rẹ kí ìwọ lè máa ṣe é.
A lawk teh na tarawi nahanelah nang hoi a hnai poung. Na pahni dawk thoseh, na lung dawk thoseh ao.
15 Wò ó mo gbé kalẹ̀ síwájú u yín lónìí, ìyè àti àlàáfíà, ikú àti ìparun.
Khenhaw! hringnae hoi hawinae, duenae hoi thoenae heh sahnin na hmalah ka hruek
16 Ní èyí tí mo pàṣẹ fún ọ ní òní láti máa fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ, láti máa rìn ní ọ̀nà rẹ̀ àti láti máa pa àṣẹ rẹ̀, àti ìlànà rẹ̀, àti ìdájọ́ rẹ̀ mọ́, kí ìwọ kí ó lè yè, kí ó sì máa bí sí i, kí Olúwa Ọlọ́run lè bù si fún ọ ní ilẹ̀ náà, ní ibi tí ìwọ ń lọ láti gbà á.
Na hring teh na pungdaw nahan hoi na pang hane ram dawk na BAWIPA Cathut ni yawhawi na poe nahan na Cathut hah na lungpataw han, a hnuk na kâbang vaiteh, kâpoelawknaw, phunglawknaw, hoi lawkcengnaenaw hah tarawi loe telah lawk na thui.
17 Ṣùgbọ́n tí ọkàn an yín bá yí padà tí ìwọ kò sì ṣe ìgbọ́ràn, àti bí o bá fà, lọ láti foríbalẹ̀ fún ọlọ́run mìíràn àti sìn wọ́n,
Hatei, na lungthin hah alouklah a kamlang teh, lawkngai laipalah tami dumnae koelah na kamlang teh alouke cathut na bawk pawiteh,
18 èmi ń sọ fún un yín lónìí yìí pé ìwọ yóò parun láìsí àní àní. O kò ní í gbé pẹ́ ní ilẹ̀ tí ìwọ ń kọjá Jordani láti gbà àti láti ní.
Jordan tui na raka teh na pang hane ram dawk na hring saw mahoeh. Atangcalah rawknae koe na pha han telah sahnin kâhruetcuetnae na poe.
19 Èmi pe ọ̀run àti ilẹ̀ láti jẹ́rìí tì yín ní òní pé, èmi fi ìyè àti ikú, ìbùkún àti ègún síwájú rẹ: nítorí náà yan ìyè, kí ìwọ kí ó lè yè, ìwọ àti irú-ọmọ rẹ,
Hringnae hoi duenae, yawhawi poenae hoi thoebonae naw na hmalah ka hruek. Nama hoi na canaw ni hring nahanlah rawi lawih. Kapanuekkung kalvan hoi talai ka kaw.
20 kí ìwọ kí ó le máa fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ, fetísílẹ̀ sí ohùn un rẹ̀, kí o sì dúró ṣinṣin nínú rẹ̀. Nítorí Olúwa ni ìyè rẹ, yóò sì fún ọ ní ọdún púpọ̀ ní ilẹ̀ tí ó ti búra láti fi fún àwọn baba rẹ Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu.
Hatdawkvah, nang hoi na catounnaw ni na hring nahan hoi nange BAWIPA Cathut na lungpataw teh a lawk na tarawi dawkvah, hringsawnae na kapoekung BAWIPA hah na kâhnai nahan thoseh, BAWIPA ni na mintoe Abraham, Isak, Jakop koe thoebo e ram dawk o hane hoi kâvan e hringnae rawi loe telah thoseh Isarel miphun koe a dei pouh.

< Deuteronomy 30 >