< Deuteronomy 3 >

1 Lẹ́yìn èyí ní a yípadà tí a sì kọrí sí ọ̀nà tí ó lọ sí Baṣani, Ogu ọba Baṣani àti gbogbo jagunjagun rẹ̀ ṣígun wá pàdé wa ní Edrei.
Nĩtwacookire tũkĩgarũrũka na tũkĩambata na njĩra tũrorete Bashani, nake Ogu mũthamaki wa Bashani akiumagara na mbũtũ ciake ciothe cia ita oke ahũũrane na ithuĩ kũu Edirei.
2 Olúwa sọ fún mi pé, “Má ṣe bẹ̀rù rẹ̀, nítorí tí mó tí fi òun lé ọ lọ́wọ́, àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, àti ilẹ̀ rẹ̀. Kí ìwọ kí ó ṣe sí i gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti ṣe sí Sihoni ọba Amori ẹni tí ó ń jẹ ọba ní Heṣboni.”
Nake Jehova akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Ndũkamwĩtigĩre, nĩ ũndũ nĩndĩmũneanĩte hamwe na mbũtũ ciake ciothe cia ita na bũrũri wake moko-inĩ maku. Mwĩke o ũrĩa wekire Sihoni mũthamaki wa Aamori, ũrĩa waathanaga Heshiboni.”
3 Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa Ọlọ́run wa fi Ogu ọba Baṣani àti àwọn jagunjagun rẹ̀ lé wa lọ́wọ́. A kọlù wọ́n títí kò fi ku ẹnìkan fún un láàyè.
Nĩ ũndũ ũcio Jehova Ngai witũ akĩneana Ogu mũthamaki wa Bashani moko-inĩ maitũ na mbũtũ yake yothe. Tũkĩmooraga na tũtiatigirie mũndũ o na ũmwe.
4 Ní ìgbà náà ní a gba gbogbo àwọn ìlú rẹ̀. Kò sí ọ̀kankan tí a kò gbà nínú àwọn ọgọta ìlú tí wọ́n ní, gbogbo agbègbè Argobu, lábẹ́ ìjọba Ogu ní Baṣani.
Ihinda-inĩ rĩu tũkĩmatunya matũũra mao mothe. Gũtirĩ itũũra o na rĩmwe rĩa matũũra mao mĩrongo ĩtandatũ tũtaamatunyire, marĩa maarĩ bũrũri-inĩ ũcio wothe wa Arigobu, ũthamaki-inĩ wa Ogu kũu Bashani.
5 Gbogbo ìlú wọ̀nyí ní a mọ odi gíga yíká pẹ̀lú àwọn ìlẹ̀kùn àti irin. Ọ̀pọ̀ àwọn ìlú kéékèèké tí a kò mọ odi yíká sì tún wà pẹ̀lú.
Matũũra macio mothe maarĩ mairigĩre na hinya, na thingo ndaaya na igũrũ, na ihingo ciarĩ na mĩgĩĩko, na ningĩ no kwarĩ tũtũũra tũingĩ tũtaarĩ tũirigĩre.
6 Gbogbo wọn ni a parun pátápátá gẹ́gẹ́ bí á ti ṣe sí Sihoni ọba Heṣboni, tí a pa gbogbo ìlú wọn run pátápátá: tọkùnrin tobìnrin àti àwọn ọmọ wọn.
Nĩtwamanangire biũ, o ta ũrĩa twekĩte Sihoni mũthamaki wa Heshiboni, tũkĩananga matũũra mothe manene, o na tũkĩniina arũme na andũ-a-nja o na ciana.
7 Ṣùgbọ́n a kó gbogbo ohun ọ̀sìn àti ìkógun àwọn ìlú wọn, fún ara wa.
No mahiũ mothe na indo iria twatahire kuuma matũũra macio mao manene nĩtwacioire tũgĩthiĩ nacio.
8 Ní ìgbà náà ni a ti gba ilẹ̀ tí ó wà ní Jordani láti odò Arnoni, títí dé orí òkè Hermoni lọ́wọ́ àwọn ọba Amori méjèèjì wọ̀nyí.
Nĩ ũndũ ũcio ihinda-inĩ rĩu nĩtwatunyanire bũrũri ũrĩa warĩ irathĩro rĩa Rũũĩ rwa Jorodani, kuuma kũrĩ athamaki acio eerĩ a Aamori, naguo uumĩte kĩanda kĩa Arinoni nginya kĩrĩma-inĩ kĩa Herimoni.
9 (Àwọn ará Sidoni ń pe Hermoni ní Sirioni. Àwọn Amori sì ń pè é ní Seniri).
(Kĩrĩma kĩa Herimoni gĩĩtagwo Sirioni nĩ Asidoni; nao Aamori magĩĩtaga Seniru.)
10 Gbogbo àwọn ìlú tí ó wà ní orí òkè olórí títẹ́ náà ni a gbà àti gbogbo Gileadi, àti gbogbo Baṣani, títí dé Saleka, àti Edrei, ìlú àwọn ọba Ogu ní ilẹ̀ Baṣani.
Nĩtwatahire matũũra mothe marĩa maarĩ kũndũ kwaraganu, na Gileadi guothe, na Bashani guothe, o nginya Saleka na Edirei, matũũra ma kũrĩa Ogu aathanaga kũu Bashani.
11 (Ogu tí í ṣe ọba Baṣani nìkan ni ó ṣẹ́kù nínú àwọn ará Refaimu. Ibùsùn rẹ̀ ni a fi irin ṣe, ó sì gùn ju ẹsẹ̀ bàtà mẹ́tàlá lọ ní gígùn àti ẹsẹ̀ bàtà mẹ́fà ní ìbú. Èyí sì wà ní Rabba ti àwọn Ammoni.)
(No Ogu mũthamaki wa Bashani wiki watigarire harĩ matigari ma Arefai. Gĩtanda gĩake kĩarĩ gĩa cuuma, na kĩarĩ na ũraihu wa makĩria ma buti ikũmi na ithatũ, na wariĩ wa buti ithathatũ. Gĩtanda kĩu kĩrĩ o kũu Raba kwa Aamoni.)
12 Nínú àwọn ilẹ̀ tí a gbà ní ìgbà náà, mo fún àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi, ní ilẹ̀ tí ó wà ní àríwá Aroeri níbi odò Arnoni, pọ̀ mọ́ ìdajì ilẹ̀ òkè Gileadi pẹ̀lú gbogbo ìlú wọn.
Naguo bũrũri ũrĩa twatunyanire hĩndĩ ĩyo-rĩ, nĩndagaĩire andũ a Rubeni na a Gadi bũrũri ũrĩa warĩ gathigathini wa Aroeri kũnyiitana na kĩanda kĩa Arinoni, hamwe na nuthu ya bũrũri ũrĩa ũrĩ irĩma wa Gileadi, o hamwe na matũũra makuo.
13 Gbogbo ìyókù Gileadi àti gbogbo Baṣani, ní ilẹ̀ ọba Ogu ni mo fún ìdajì ẹ̀yà Manase. (Gbogbo agbègbè Argobu ni Baṣani tí a mọ̀ sí ilẹ̀ àwọn ará Refaimu.
Nakuo kũrĩa kũngĩ guothe gwatigaire kũu Gileadi o na Bashani guothe, kũrĩa Ogu aathanaga, ngĩkũhe nuthu ya mũhĩrĩga wa Manase. (Bũrũri wothe wa Arigobu kũu Bashani hĩndĩ ĩmwe wetagwo bũrũri wa Arefai.
14 Jairi ọ̀kan nínú àwọn ìran Manase gba gbogbo agbègbè Argobu títí dé ààlà àwọn ará Geṣuri àti àwọn ará Maakati; a sọ ibẹ̀ ní orúkọ rẹ̀ torí èyí ni Baṣani fi ń jẹ́ Hafoti-Jairi títí di òní.)
Jairu, wa rũciaro rwa Manase, nĩegwatĩire bũrũri wothe wa Arigobu o nginya mũhaka-inĩ wa Ageshuru na Amaakathi; nakuo gũgĩĩtanio nake, nĩ ũndũ ũcio Bashani gwĩtagwo Havothu-Jairu o nginya ũmũthĩ.)
15 Mo sì fi Gileadi fún Makiri,
Na nĩndaheanire Gileadi kũrĩ Makiru.
16 ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Reubeni àti ọmọ Gadi ni mo fún ní ilẹ̀ láti Gileadi lọ dé odò Arnoni (àárín odò náà sì jẹ́ ààlà) títí ó fi dé odò Jabbok. Èyí tí i ṣe ààlà àwọn ará Ammoni.
No andũ a Rubeni na a Gadi ndaamaheire bũrũri ũrĩa uumĩte Gileadi ũgaikũrũka nginya kĩanda kĩa Arinoni (mũhaka warĩ gatagatĩ ga kĩanda kĩu), ũgacooka ũgakinya rũũĩ-inĩ rwa Jaboku, arĩ ruo mũhaka wa Aamoni.
17 Pẹ̀tẹ́lẹ̀ Arabah pẹ̀lú, àti Jordani gẹ́gẹ́ bí òpin ilẹ̀ rẹ̀, láti Kinnereti lọ títí dé Òkun pẹ̀tẹ́lẹ̀ Arabah, àní Òkun Iyọ̀, ní ìsàlẹ̀ àwọn orísun Pisga ní ìhà ìlà-oòrùn.
Mũhaka wakuo wa mwena wa ithũĩro warĩ Rũũĩ rwa Jorodani kũu Araba, kuuma Kinerethu nginya Iria-inĩ rĩa Araba (nĩrĩo Iria rĩa Cumbĩ), mũhuro wa iharũrũka cia Pisiga.
18 Mo pàṣẹ fún un yín ní ìgbà náà pé, “Olúwa Ọlọ́run yín ti fi ilẹ̀ yìí fún un yín láti ní i. Ṣùgbọ́n, gbogbo àwọn ọkùnrin yín tí ó lera tí wọ́n sì ti dira ogun, gbọdọ̀ kọjá síwájú àwọn arákùnrin yín: ará Israẹli.
Hĩndĩ ĩyo nĩndamwathire ngĩmwĩra atĩrĩ, “Jehova Ngai wanyu nĩamũheete bũrũri ũyũ mũwĩgwatĩre. No andũ anyu arĩa marĩ na hinya, arĩa meeohete indo cia mbaara, no nginya maringe mũrĩmo ũrĩa ũngĩ mbere ya andũ a Isiraeli ariũ a ithe wanyu.
19 Àwọn ẹ̀yà a yín, àwọn ọmọ yín àti àwọn ohun ọ̀sìn in yín (mo mọ̀ pé ẹ ti ní ohun ọ̀sìn púpọ̀) lè dúró ní àwọn ìlú tí mo fi fún un yín,
No rĩrĩ, atumia anyu, na ciana cianyu, o na ũhiũ wanyu (nĩnjũũĩ nĩ mũrĩ na ũhiũ mũingĩ) no maikare matũũra-inĩ marĩa ndĩmũheete,
20 títí di ìgbà tí Olúwa yóò fún àwọn arákùnrin yín ní ìsinmi bí ó ti fún un yín, àti ìgbà tí àwọn náà yóò fi gba ilẹ̀ náà tí Olúwa Ọlọ́run yín ti fún wọn ní ìhà kejì Jordani. Nígbà náà ni ọ̀kọ̀ọ̀kan yín tó lè padà lọ sí ìní rẹ̀ tí mo fún un.”
nginya rĩrĩa Jehova akaahe ariũ a thoguo ũhurũko ta ũrĩa amũheete inyuĩ, nao makorwo meyoeire bũrũri ũrĩa Jehova Ngai wanyu ekũmahe, mũrĩmo ũrĩa ũngĩ wa Rũũĩ rwa Jorodani. Thuutha ũcio-rĩ, o mũndũ wanyu no acooke handũ harĩa ndĩmũheete mwĩgwatĩre hatuĩke hanyu.”
21 Nígbà náà ni mo pàṣẹ fún Joṣua pé, “Ìwọ tí fi ojú rẹ rí ohun gbogbo tí Olúwa Ọlọ́run rẹ tí ṣe sí àwọn ọba méjèèjì wọ̀nyí. Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa yóò ṣe sí àwọn ilẹ̀ ọba tí ẹ̀yin n lọ.
Ningĩ ngĩatha Joshua ngĩmwĩra atĩrĩ: “Nĩwĩoneire na maitho maku ũrĩa wothe Jehova Ngai wanyu ekĩte athamaki acio eerĩ. Ũguo noguo Jehova ageeka mothamaki marĩa mothe marĩ kũndũ kũu mũrathiĩ.
22 Ẹ má ṣe bẹ̀rù wọn, Olúwa Ọlọ́run yín tìkára rẹ̀ ni yóò jà fún un yín.”
Ndũkanametigĩre; Jehova Ngai wanyu nĩwe ũrĩmũrũagĩrĩra.”
23 Nígbà náà ni mo bẹ Olúwa wí pé,
Hĩndĩ ĩyo nĩndathaithire Jehova ngĩmwĩra atĩrĩ:
24 “Olúwa Olódùmarè, ìwọ tí bẹ̀rẹ̀ sí fi títóbi rẹ àti ọwọ́ agbára rẹ han ìránṣẹ́ rẹ. Ọlọ́run wo ló tó bẹ́ẹ̀ láyé àti lọ́run tí ó lè ṣe àwọn iṣẹ́ agbára ńlá tí o ti ṣe?
“We Mwathani Jehova, nĩwambĩrĩirie kuonia ndungata yaku ũnene waku na hinya wa guoko gwaku. Nĩ ũndũ-rĩ, nĩ ngai ĩrĩkũ igũrũ kana thĩ ĩngĩĩka ciĩko cia hinya ta iria wee wĩkaga?
25 Jẹ́ kí n kọjá lọ wo ilẹ̀ rere ti ìkọjá Jordani, ilẹ̀ òkè dídára nì àti Lebanoni.”
Reke ninge kũndũ kũu mũrĩmo wa Rũũĩ rwa Jorodani ngeyonere bũrũri mwega, bũrũri ũcio mwega ũrĩ irĩma o na bũrũri wa Lebanoni.”
26 Ṣùgbọ́n torí i tiyín, Olúwa Ọlọ́run bínú sí mi kò sì gbọ́ tèmi. Olúwa sọ wí pé, “Ó tó gẹ́ẹ́, ìwọ kò gbọdọ̀ sọ ohunkóhun lórí ọ̀rọ̀ yìí sí mi mọ́.
No nĩ ũndũ wanyu-rĩ, Jehova nĩandakarĩire na ndangĩathikĩrĩirie. Jehova akiuga atĩrĩ, “Reke ũhoro ũcio ũkinye hau, ndũkanjarĩrie rĩngĩ ũndũ wĩgiĩ ũhoro ũcio.
27 Gòkè lọ sí orí òkè Pisga, sì wò yíká ìwọ̀-oòrùn, ìlà-oòrùn, àríwá àti gúúsù. Fi ojú ara rẹ wo ilẹ̀ náà níwọ̀n bí ìwọ kò tí ní kọjá Jordani yìí.
Ambata gacũmbĩrĩ ga kĩrĩma kĩa Pisiga wĩrorere mwena wa ithũĩro, na wa gathigathini, na wa gũthini, o na wa irathĩro. Wĩrorere bũrũri ũcio na maitho maku, nĩ ũndũ ndũkũringa rũũĩ rũrũ rwa Jorodani.
28 Ṣùgbọ́n yan Joṣua, kí o sì gbà á níyànjú, mú un lọ́kàn le, torí pé òun ni yóò síwájú àwọn ènìyàn wọ̀nyí kọjá, yóò sì jẹ́ kí wọn jogún ilẹ̀ náà tí ìwọ yóò rí.”
No rĩrĩ, taara Joshua, na ũmũũmĩrĩrie, na ũmwĩkĩre hinya, nĩgũkorwo nĩwe ũgaatongoria andũ aya maringe mathiĩ mũrĩmo ũrĩa ũngĩ, na atũme magae bũrũri ũcio ũkuona.”
29 Báyìí ni a dúró ní àfonífojì ní ẹ̀bá Beti-Peori.
Nĩ ũndũ ũcio tũgĩikara kũu gĩtuamba-inĩ hakuhĩ na Bethi-Peori.

< Deuteronomy 3 >