< Deuteronomy 29 >

1 Èyí ni àwọn ìpinnu májẹ̀mú tí Olúwa pàṣẹ fún Mose láti ṣe pẹ̀lú àwọn ọmọ Israẹli ní Moabu, ní àfikún májẹ̀mú tí ó ti ṣe pẹ̀lú u wọn ní Horebu.
Töwendikiler Perwerdigar Israillar bilen ehde baghlash üchün Moab zéminida Musagha tapilighan sözlerdur. Bu ehde Perwerdigar ular bilen Horebde qilghan ehdidin bashqa bir ehde idi.
2 Mose pàṣẹ fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ó sì wí fún wọn wí pé, ojú rẹ ti rí gbogbo ohun tí Olúwa ti ṣe ní Ejibiti sí Farao àti, sí gbogbo àwọn ìjòyè e rẹ̀ àti sí ilẹ̀ ẹ rẹ̀.
Musa pütkül Israilni chaqirip ulargha mundaq dédi: «Siler Perwerdigarning Misir zéminida Pirewn’ge, uning barliq xizmetkarliri we zéminning hemme yéride köz aldinglarda néme ish qilghinini kördünglar,
3 Pẹ̀lú ojú ara rẹ ni ìwọ rí àwọn ìdánwò ńlá náà, àwọn iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu ńlá.
yeni shu chong apetler bilen ulugh möjizilik alamet we karametlerni öz közünglar bilen kördünglar.
4 Ṣùgbọ́n títí di àsìkò yìí Olúwa kò fi ọkàn ìmòye tàbí ojú tí ó ń rí tàbí etí tí ó n gbọ́ fún ọ.
Lékin Perwerdigar silerge bügün’giche chüshen’güdek köngül, körgüdek köz we anglighudek qulaq bermidi.
5 Nígbà ogójì ọdún tí mò ń tọ́ yín ṣọ́nà ní aginjù, aṣọ ọ̀ rẹ kò gbó tàbí bàtà ẹsẹ̀ rẹ.
Men qiriq yil silerni bayawanda yéteklep yürdüm; shu waqitlarda üstünglardiki kiyimliringlar konirimidi, putunglardiki keshinglarmu konirap ketmidi.
6 O kò jẹ oúnjẹ tàbí mu wáìnì kankan tàbí rú ohun mímu mìíràn. Mo ṣe èyí kí o lè mọ̀ pé Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ.
Xuda Özining silerning Perwerdigar Xudayinglar ikenlikini bilsun dep, silerge yéyishke nan, ichishke sharab yaki küchlük ichimlik nésip qilmidi.
7 Nígbà tí o dé ibí yìí, Sihoni ọba Heṣboni àti Ogu ọba Baṣani jáde wá láti bá ọ jà, ṣùgbọ́n a ṣẹ́gun wọn.
Siler bu jaygha yétip kelgininglarda Heshbonning padishahi Sihon bilen Bashanning padishahi Og biz bilen jeng qilghili chiqti; emma biz ularni urup meghlup qilduq;
8 A gba ilẹ̀ wọn a sì fi fún àwọn ọmọ Reubeni, àti àwọn ọmọ Gadi, àti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase bí ogún.
biz ularning zéminlirini élip Rubenler bilen Gadlar we Manassehning yérim qebilisige miras qilip berduk.
9 Nítorí náà, ẹ pa májẹ̀mú yìí mọ́, kí ẹ sì máa ṣe wọ́n, kí ẹ̀yin kí ó lè máa rí ire nínú gbogbo ohun tí o bá ń ṣe.
Emdi siler hemme ishliringlarda rawaj tépish üchün bu ehdining sözlirini tutup, ulargha emel qilinglar.
10 Gbogbo yín ń dúró lónìí yìí níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ: àwọn olórí yín, àwọn ẹ̀yà yín, àwọn àgbàgbà yín àti àwọn ìjòyè yín, àní gbogbo àwọn ọkùnrin mìíràn ní Israẹli,
Bügün hemminglar — kebile bashliqliringlar, aqsqalliringlar, emeldarliringlar, shuningdek Israilning hemme erliri,
11 pẹ̀lú gbogbo àwọn ọmọ ọ̀ rẹ àti ìyàwó ò rẹ àti àwọn àjèjì tí wọ́n ń gbé ní àgọ́ ọ̀ rẹ, tí ó ké pópòpó igi rẹ, tí ó sì gbé omi rẹ.
kichik baliliringlar, ayalliringlar, chédirgahinglarda turuwatqan musapirlar, shundaqla otun kesküchiliringlar we su toshughuchiliringlarmu, hemminglar Perwerdigarning aldida hazir turuwatisiler;
12 O dúró níhìn-ín yìí kí o lè wọ inú májẹ̀mú pẹ̀lú Olúwa Ọlọ́run rẹ, májẹ̀mú tí Olúwa ń ṣe pẹ̀lú rẹ lónìí yìí àti tí òun dè pẹ̀lú ìbúra,
meqset shuki, Perwerdigar Xudayinglarning ehdisige, yeni Perwerdigar Xudayinglar bügün silerge bergen qesimi bilen baghlighan ehdige daxil bolushunglar üchündur,
13 láti jẹ́wọ́ rẹ lónìí yìí bí ènìyàn an rẹ̀, pé kí ó lè jẹ́ Ọlọ́run rẹ bí ó ti ṣèlérí àti bí ó ti ṣe ìbúra fún àwọn baba à rẹ Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu.
We shuning bilen teng U silerni bügün Özige xas bir xelq qilip silerge wede qilghinidek, ata-bowiliringlargha, yeni Ibrahim, Ishaq we Yaqupqa qilghan qesimi boyiche özi silerge Xuda bolushtur.
14 Èmi ń ṣe májẹ̀mú yìí, pẹ̀lú ìbúra rẹ̀, kì í ṣe fún ìwọ nìkan
Lékin men bu ehde we qesemni yalghuz siler bilenla emes,
15 tí ó dúró níbí pẹ̀lú wa lónìí níwájú Olúwa Ọlọ́run wa ṣùgbọ́n àti fún gbogbo àwọn tí kò sí níbí lónìí.
belki bügün biz bilen bu yerde Perwerdigar Xudayimizning aldida turuwatqanlar, shundaqla bügün bu yerde biz bilen birge bolmighan kishilerning hemmisi bilenmu tüzüshimen.
16 Ìwọ fúnra à rẹ mọ bí a ṣe gbé ní Ejibiti àti bí a ṣe kọjá láàrín àwọn orílẹ̀-èdè nílẹ̀ ibí yìí.
(chünki siler bizning Misir zéminida qandaq turghanliqimiz we sepirimizde ellerning otturisidin qandaq ötüp kelginimizni obdan bilisiler;
17 Ìwọ rí láàrín wọn ìríra wọn, àwọn ère àti àwọn òrìṣà igi àti ti òkúta, ti fàdákà àti ti wúrà.
Siler ularning arisidiki yirginchlik nersilerni, ularning arisidiki yaghach, tash, altun we kümüshtin yasalghan butlarni kördünglar).
18 Rí i dájú pé kò sí ọkùnrin tàbí obìnrin, ìdílé tàbí ẹ̀yà láàrín yín lónìí tí ọkàn an rẹ̀ yóò yí kúrò lọ́dọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa láti lọ àti láti sin àwọn ọlọ́run àwọn orílẹ̀-èdè náà; rí i dájú pé kò sí gbòǹgbò tí ó ń mú irú èso kíkan bẹ́ẹ̀ jáde láàrín yín.
Ehdining meqsiti bolsa, silerning aranglardiki herbir er, herbir ayal, herbir aile we herbir qebililiringlardin bügün köngli Perwerdigar Xudayimizdin yénip, shu ellerning ilahlirining qulluqigha kirip kétidighan héch kishi bolmisun, shundaqla aranglarda öt süyi we emen chiqiridighan yiltiz peyda bolup qalmisun üchündur.
19 Nígbà tí irú ẹni bẹ́ẹ̀ bá gbọ́ ìbúra yìí, kí ó gbàdúrà ìbùkún sórí ara rẹ̀ nígbà náà ni kí ó ronú, “Èmi yóò wà ní àlàáfíà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti fi àáké kọ́rí nípa lílọ nínú ọ̀nà ti ara à mi.” Èyí yóò mú àjálù wá sórí ilẹ̀ tútù àti sórí ilẹ̀ gbígbẹ bákan náà
Derweqe shundaq boliduki, shu lenet sözlirini anglighanda öz könglide öz-özini bext-beriketlik sanap: «Men qanche bashbashtaqliq bilen mangsammu, tinch-amanliqta turiwérimen», dégüchi shundaq bir kishi bolidu; netijide, nem yermu changqaq yerge oxshashla weyran qilinidu.
20 Olúwa kì yóò ní ìfẹ́ sí àti dáríjì í; ìbínú àti ìtara rẹ̀ yóò jó ọkùnrin náà. Gbogbo àwọn ègún tí a kọ sínú ìwé yìí yóò wá sórí i rẹ̀, Olúwa yóò sì yọ orúkọ rẹ̀ kúrò lábẹ́ ọ̀run.
Perwerdigar mundaq kishini epu qilmaydu, belki Perwerdigarning ghezipi bilen otluq qehri tütündek shu kishige chüshidu; bu kitabta pütülgen hemme lenetler uning béshigha chüshidu; Perwerdigar uning ismini asmanning tégidin öchüridu.
21 Olúwa yóò sì yọ òun nìkan kúrò nínú gbogbo ẹ̀yà Israẹli fún àjálù, gẹ́gẹ́ bí gbogbo ègún májẹ̀mú tí a kọ sí inú ìwé òfin yìí.
Perwerdigar bu qanun kitabida pütülgen ehdining hemme lenetliri boyiche Israilning barliq qebililiridin uni ayrip chiqip, apetke muptila qilidu.
22 Àwọn ọmọ rẹ tí ó tẹ̀lé ìran rẹ lẹ́yìn àti àwọn àjèjì tí ó wá láti ilẹ̀ jíjìn yóò rí wàhálà tí ó wá sórí ilẹ̀ àti àwọn ààrùn pẹ̀lú tí Olúwa mú bá ọ.
Kelgüsi dewr bolsa, yeni silerdin kéyin chiqidighan baliliringlar we shundaqla yiraq yurttin kelgen musapirlar Perwerdigar shu zéminning üstige ewetken balayi’apetler bilen késellerni köridu;
23 Gbogbo ilẹ̀ náà yóò di imí-oòrùn, àti iyọ̀, àti ìjóná tí a kò lè fi ọkàn sí, tàbí tí kò lè so èso tàbí tí koríko kò lè hù nínú u rẹ̀, yóò dàbí ìbìṣubú Sodomu àti Gomorra, Adma àti Seboimu, tí Olúwa bì ṣubú nínú ìbínú rẹ̀, àti ìkáàánú rẹ̀.
Perwerdigar ghezipi we qehri bilen weyran qilghan Sodom, Gomorra, Admah we Zeboimlarning weyranchiliqidek zéminning hemme yéri günggürtliship, shorliship, köyüp ketkinini, tériqchiliqmu, hosulmu bolmighinini, ot-chöpmu ünmiginini köridu;
24 Gbogbo orílẹ̀-èdè yóò béèrè pé, “Kí ló dé tí Olúwa fi ṣe èyí sí ilẹ̀ yìí? Kí ni a lè mọ ooru ìbínú ńlá yìí sí?”
buni körgenler, hetta hemme el-yurt: «Némishqa Perwerdigar bu zémin’gha mundaq qilghandu? Némishqa Uning ghezipi shunche qattiq, esheddiy bolghandu?» dep soraydu;
25 Ìdáhùn yóò sì jẹ́ báyìí: “Nítorí tí ènìyàn yìí kọ Olúwa Ọlọ́run baba wọn sílẹ̀, májẹ̀mú tí ó ti bá wọn dá nígbà tí ó mú wọn jáde wá láti Ejibiti.
andin ulargha jawab bérilip: «Ular ata-bowilirining Xudasi Perwerdigarning ularni Misir zéminidin qutquzup chiqarghinida ular bilen békitken ehdini tashlap,
26 Wọ́n lọ wọ́n sì sin ọlọ́run mìíràn, wọ́n sì foríbalẹ̀ fún wọn, ọlọ́run tí wọn kò mọ̀, ọlọ́run tí kò fi fún wọn.
bérip ularning nésiwisi bolmighan, özimu tonumighan ilahlarning qulluqigha kirip, ulargha choqun’ghini üchün shundaq boldi.
27 Nígbà náà ni ìbínú Olúwa ru sí ilẹ̀ wọn, dé bi pé ó mú gbogbo ègún tí a kọ sínú ìwé yìí wá sórí i rẹ̀.
Mana bu sewebtin Perwerdigarning ghezipi bu zémin’gha tutiship, bu kitabta pütülgen hemme lenetni uning üstige keltürdi.
28 Ní ìbínú àti ní ìkáàánú, àti ní ìrunú ńlá, Olúwa sì fà wọ́n tu kúrò ní ilẹ̀ wọn, ó sì lé wọn lọ sí ilẹ̀ mìíràn, bí ó ti rí ní òní yìí.”
Shuning üchün Perwerdigar ghezep, achchiq we zor qehr bilen ularni yurtidin yulup, bashqa bir yurtqa tashlidi» — déyilidu.
29 Ohun ìkọ̀kọ̀ jẹ́ ti Olúwa Ọlọ́run wa, ṣùgbọ́n ohun tí a fihàn jẹ́ ti wa àti ti àwọn ọmọ wa títí láé, kí a lè tẹ̀lé gbogbo ọ̀rọ̀ inú òfin yìí.
Herbir yoshurun sirlar bolsa Perwerdigar Xudayimizningkidur; lékin herqandaq ashkarilan’ghan wehiyler bolsa bu qanunning sözlirige emel qilishimiz üchün ebedgiche biz we balilirimizningkidur.

< Deuteronomy 29 >