< Deuteronomy 29 >
1 Èyí ni àwọn ìpinnu májẹ̀mú tí Olúwa pàṣẹ fún Mose láti ṣe pẹ̀lú àwọn ọmọ Israẹli ní Moabu, ní àfikún májẹ̀mú tí ó ti ṣe pẹ̀lú u wọn ní Horebu.
Hethateh, Horeb hmuen koe Isarelnaw hoi BAWIPA ni lawkkam e hloilah, Moab ram dawk Isarelnaw hoi lawkkam hanelah, Mosi koe a dei pouh e lawkkam lawk doeh.
2 Mose pàṣẹ fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ó sì wí fún wọn wí pé, ojú rẹ ti rí gbogbo ohun tí Olúwa ti ṣe ní Ejibiti sí Farao àti, sí gbogbo àwọn ìjòyè e rẹ̀ àti sí ilẹ̀ ẹ rẹ̀.
Mosi ni Isarelnaw pueng ama koe a kaw teh, nangmouh ni patuen bout na dei awh hane teh, Izip ram Faro siangpahrang hoi a taminaw hoi a ram pueng e lathueng na mithmu roeroe vah, BAWIPA ni a sak e pueng teh be na hmu awh toe.
3 Pẹ̀lú ojú ara rẹ ni ìwọ rí àwọn ìdánwò ńlá náà, àwọn iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu ńlá.
Tanouknae, mitnoutnaw, hoi kângairu hnonaw hah na mit hoi roeroe na hmu awh.
4 Ṣùgbọ́n títí di àsìkò yìí Olúwa kò fi ọkàn ìmòye tàbí ojú tí ó ń rí tàbí etí tí ó n gbọ́ fún ọ.
Hatei, thaipanueknae lung, hmuthainae mit, thaithainae hnânaw hah sahnin ditouh na poe awh hoeh rah.
5 Nígbà ogójì ọdún tí mò ń tọ́ yín ṣọ́nà ní aginjù, aṣọ ọ̀ rẹ kò gbó tàbí bàtà ẹsẹ̀ rẹ.
A kum 40 touh thung kahrawngum vah nangmouh na hrawi awh toe. Nangmae khohna pawn hoeh. na khokkhawm hai pawn hoeh.
6 O kò jẹ oúnjẹ tàbí mu wáìnì kankan tàbí rú ohun mímu mìíràn. Mo ṣe èyí kí o lè mọ̀ pé Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ.
BAWIPA teh nangmae BAWIPA Cathut lah ao tie na panue awh nahanelah, nangmouh ni vaiyei na cat awh hoeh, misur hoi yamu hai na net awh hoeh.
7 Nígbà tí o dé ibí yìí, Sihoni ọba Heṣboni àti Ogu ọba Baṣani jáde wá láti bá ọ jà, ṣùgbọ́n a ṣẹ́gun wọn.
Hete hmuen koe na pha awh navah, Heshbon siangpahrang Sihon hoi Bashan siangpahrang Og tinaw teh, kaimouh na tuk hanelah a tho awh teh, kaimouh ni ka tâ awh.
8 A gba ilẹ̀ wọn a sì fi fún àwọn ọmọ Reubeni, àti àwọn ọmọ Gadi, àti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase bí ogún.
Aram ka la awh hnukkhu Reuben, Gad, Manasseh miphun tangawn naw hah râw lah ka poe awh.
9 Nítorí náà, ẹ pa májẹ̀mú yìí mọ́, kí ẹ sì máa ṣe wọ́n, kí ẹ̀yin kí ó lè máa rí ire nínú gbogbo ohun tí o bá ń ṣe.
Na tawksak awh e hno pueng dawkvah, hawinae na coe awh nahanelah, hete lawkkam heh kuen awh nateh hringkhai awh.
10 Gbogbo yín ń dúró lónìí yìí níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ: àwọn olórí yín, àwọn ẹ̀yà yín, àwọn àgbàgbà yín àti àwọn ìjòyè yín, àní gbogbo àwọn ọkùnrin mìíràn ní Israẹli,
Atuvah miphun kahrawikung abuemlahoi,
11 pẹ̀lú gbogbo àwọn ọmọ ọ̀ rẹ àti ìyàwó ò rẹ àti àwọn àjèjì tí wọ́n ń gbé ní àgọ́ ọ̀ rẹ, tí ó ké pópòpó igi rẹ, tí ó sì gbé omi rẹ.
kacuenaw hoi kahrawikungnaw, Isarelnaw pueng, camosennaw, na yunaw, na imluennaw, na thing katâtuengnaw, na tui kadonaw totouh,
12 O dúró níhìn-ín yìí kí o lè wọ inú májẹ̀mú pẹ̀lú Olúwa Ọlọ́run rẹ, májẹ̀mú tí Olúwa ń ṣe pẹ̀lú rẹ lónìí yìí àti tí òun dè pẹ̀lú ìbúra,
sahnin BAWIPA ni nangmouh koevah, thoebo lah kaawm e lawkkam thungvah na kâen awh thai nahane hoi,
13 láti jẹ́wọ́ rẹ lónìí yìí bí ènìyàn an rẹ̀, pé kí ó lè jẹ́ Ọlọ́run rẹ bí ó ti ṣèlérí àti bí ó ti ṣe ìbúra fún àwọn baba à rẹ Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu.
na pa Abraham, Isak, hoi Jakop hoi nangmouh koe lawk a kam teh a dei tangcoung patetlah nangmae Cathut lah ao thai nahane hoi a tami lah na o thai nahanelah caksak lah na o awh nahan,
14 Èmi ń ṣe májẹ̀mú yìí, pẹ̀lú ìbúra rẹ̀, kì í ṣe fún ìwọ nìkan
thoebonae hoi lawkkamnae hah nangmouh koe dueng ka sak e tho hoeh.
15 tí ó dúró níbí pẹ̀lú wa lónìí níwájú Olúwa Ọlọ́run wa ṣùgbọ́n àti fún gbogbo àwọn tí kò sí níbí lónìí.
Sahnin BAWIPA Cathut hmalah kangdout e hoi atu hi kaawm hoeh e naw koehai a sak e doeh.
16 Ìwọ fúnra à rẹ mọ bí a ṣe gbé ní Ejibiti àti bí a ṣe kọjá láàrín àwọn orílẹ̀-èdè nílẹ̀ ibí yìí.
(Bangkongtetpawiteh, Izip ram vah bangtelamaw khosak awh tie hoi nangmouh ni na ceinae miphunnaw e rahak vah bangtelamaw na cei awh tie hai na panue awh.
17 Ìwọ rí láàrín wọn ìríra wọn, àwọn ère àti àwọn òrìṣà igi àti ti òkúta, ti fàdákà àti ti wúrà.
Ahnimae panuettho e hnopainaw hoi, ahnimouh koe kaawm e thing, talung, sui, ngun naw hoi sak e ahnimae meikaphawknaw hah nangmouh ni na hmu awh toe. )
18 Rí i dájú pé kò sí ọkùnrin tàbí obìnrin, ìdílé tàbí ẹ̀yà láàrín yín lónìí tí ọkàn an rẹ̀ yóò yí kúrò lọ́dọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa láti lọ àti láti sin àwọn ọlọ́run àwọn orílẹ̀-èdè náà; rí i dájú pé kò sí gbòǹgbò tí ó ń mú irú èso kíkan bẹ́ẹ̀ jáde láàrín yín.
BAWIPA Cathut koehoi phen hane ngainae lungpouk na tawn awh teh, hote miphunnaw e cathutnaw koe na cei awh teh, tongpa, napui, imthung thoseh, miphunnaw hoi ka cet e, kakhat e a paw lungkhueknae a paw, a khongyang teh nangmouh dawk a paw han tie thoseh,
19 Nígbà tí irú ẹni bẹ́ẹ̀ bá gbọ́ ìbúra yìí, kí ó gbàdúrà ìbùkún sórí ara rẹ̀ nígbà náà ni kí ó ronú, “Èmi yóò wà ní àlàáfíà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti fi àáké kọ́rí nípa lílọ nínú ọ̀nà ti ara à mi.” Èyí yóò mú àjálù wá sórí ilẹ̀ tútù àti sórí ilẹ̀ gbígbẹ bákan náà
hot patetlae tami teh, thoebonae lawk a thai navah, a lungpata e patetlah ka sak vaiteh, tui kahrannae dawk paruinae mek bawksak nakunghai, lungmawng lah ka o han ka tet e awm langvaih tie ngaihrinae ao.
20 Olúwa kì yóò ní ìfẹ́ sí àti dáríjì í; ìbínú àti ìtara rẹ̀ yóò jó ọkùnrin náà. Gbogbo àwọn ègún tí a kọ sínú ìwé yìí yóò wá sórí i rẹ̀, Olúwa yóò sì yọ orúkọ rẹ̀ kúrò lábẹ́ ọ̀run.
Ahni teh BAWIPA ni pasai hoeh, dipmanae, lungkhueknae hmaikhu a tâco teh, Cakathoung dawk thut e thoebonae naw ahnimae lathueng ao han. BAWIPA ni ahnie min teh, kalvan rahim a raphoe han.
21 Olúwa yóò sì yọ òun nìkan kúrò nínú gbogbo ẹ̀yà Israẹli fún àjálù, gẹ́gẹ́ bí gbogbo ègún májẹ̀mú tí a kọ sí inú ìwé òfin yìí.
Hete kâlawk cauk dawk thut e thoebonae lawkkam e patetlah Isarel miphun pueng thung hoi BAWIPA ni a kapek han.
22 Àwọn ọmọ rẹ tí ó tẹ̀lé ìran rẹ lẹ́yìn àti àwọn àjèjì tí ó wá láti ilẹ̀ jíjìn yóò rí wàhálà tí ó wá sórí ilẹ̀ àti àwọn ààrùn pẹ̀lú tí Olúwa mú bá ọ.
Ram thungvah BAWIPA ni a poe hane lacik hoi patawnae hah na hnuklah ka tho hane sekatha na catounnaw hoi ahlanae koehoi ka tho hane ramlouk e taminaw ni a hmu awh toteh,
23 Gbogbo ilẹ̀ náà yóò di imí-oòrùn, àti iyọ̀, àti ìjóná tí a kò lè fi ọkàn sí, tàbí tí kò lè so èso tàbí tí koríko kò lè hù nínú u rẹ̀, yóò dàbí ìbìṣubú Sodomu àti Gomorra, Adma àti Seboimu, tí Olúwa bì ṣubú nínú ìbínú rẹ̀, àti ìkáàánú rẹ̀.
Ram thungvah gan, palawi, hoi hmaisaan, cati patue thaihoehnae, apawhik a tâcohoehnae, a lungphuennae hoi a lungkhueknae hoi BAWIPA ni a tâkhawng e Sodom hoi Gomorrah hoi Admah hoi Zeboiim patetlah a tâkhawng e a hmu awh toteh,
24 Gbogbo orílẹ̀-èdè yóò béèrè pé, “Kí ló dé tí Olúwa fi ṣe èyí sí ilẹ̀ yìí? Kí ni a lè mọ ooru ìbínú ńlá yìí sí?”
miphun pueng ni, bangkongmaw BAWIPA ni hete ram heh hettelah a sak. Hete kalenpounge lungkhueknae heh bang nama aw ati awh han.
25 Ìdáhùn yóò sì jẹ́ báyìí: “Nítorí tí ènìyàn yìí kọ Olúwa Ọlọ́run baba wọn sílẹ̀, májẹ̀mú tí ó ti bá wọn dá nígbà tí ó mú wọn jáde wá láti Ejibiti.
Hattoteh taminaw ni, Izip ram hoi a tâcokhai navah, ahnimouh hoi lawk a kam e ahnimae mintoenaw e BAWIPA Cathut e lawkkam hah a ceitakhai awh teh,
26 Wọ́n lọ wọ́n sì sin ọlọ́run mìíràn, wọ́n sì foríbalẹ̀ fún wọn, ọlọ́run tí wọn kò mọ̀, ọlọ́run tí kò fi fún wọn.
ahnimouh hanelah banghai ka pouk thai hoeh e cathut alouke, a panue awh boihoeh e cathut thaw a tawk awh dawk doeh ati awh han.
27 Nígbà náà ni ìbínú Olúwa ru sí ilẹ̀ wọn, dé bi pé ó mú gbogbo ègún tí a kọ sínú ìwé yìí wá sórí i rẹ̀.
Hete cakathoung dawk thut lah kaawm e thoebonae pueng, hete ram dawk phasak hanelah, BAWIPA a lungkhuek.
28 Ní ìbínú àti ní ìkáàánú, àti ní ìrunú ńlá, Olúwa sì fà wọ́n tu kúrò ní ilẹ̀ wọn, ó sì lé wọn lọ sí ilẹ̀ mìíràn, bí ó ti rí ní òní yìí.”
BAWIPA ni lungphuennae, puenghoi lungkhueknae, Lungphuennae hoi ahnimae ram dawk hoi ahnimouh hah a rasa teh, sahnin e patetlah alouke ram dawk a pâlei toe tie hah doeh.
29 Ohun ìkọ̀kọ̀ jẹ́ ti Olúwa Ọlọ́run wa, ṣùgbọ́n ohun tí a fihàn jẹ́ ti wa àti ti àwọn ọmọ wa títí láé, kí a lè tẹ̀lé gbogbo ọ̀rọ̀ inú òfin yìí.
Kamnuek hoeh rae naw teh BAWIPA Cathut mae doeh. Hatei, pâpho e naw teh maimouh hoi maimae canaw hanelah pout laipalah ao teh, hete kâlawknaw pueng teh tarawi nahanelah doeh.