< Deuteronomy 28 >
1 Bí ìwọ bá gbọ́rọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ ní kíkún kí o sì kíyèsára láti tẹ̀lé gbogbo ohun tí ó pàṣẹ tí mo fi fún ọ lónìí, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò gbé ọ lékè ju gbogbo orílẹ̀-èdè ayé lọ.
Ũngĩathĩkĩra Jehova Ngai waku kũna na ũmenyerere maathani make mothe marĩa ngũkũhe ũmũthĩ, Jehova Ngai waku nĩagagũtũũgĩria igũrũ rĩa ndũrĩrĩ ciothe cia thĩ.
2 Gbogbo ìbùkún yìí yóò wá sórí rẹ yóò sì máa bá ọ lọ bí o bá gbọ́rọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ.
Irathimo ici ciothe nĩ igagũkinyĩra na itwaranage nawe ũngĩathĩkĩra Jehova Ngai waku:
3 Ìbùkún ni fún ọ ni ìlú, ìbùkún ni fún ọ ní oko.
Nĩũkarathimĩrwo kũu itũũra-inĩ inene, na ũrathimĩrwo mĩgũnda-inĩ.
4 Ìbùkún ni fún ọmọ inú rẹ, àti èso ilẹ̀ rẹ, àti irú ohun ọ̀sìn rẹ àti ìbísí i màlúù rẹ àti ọmọ àgùntàn rẹ.
Ũciari wa nda yaku nĩũkarathimwo, o na ũrathimĩrwo maciaro ma mũgũnda waku na maciaro ma mahiũ maku, nĩmo njaũ cia ngʼombe ciaku na tũũri twa ndũũru ciaku cia mbũri.
5 Ìbùkún ni fún agbọ̀n rẹ àti fún ọpọ́n ipò ìyẹ̀fun rẹ.
Kĩondo gĩaku o na ndĩrĩ yaku ya gũkandĩra mũtu nĩikarathimwo.
6 Ìbùkún ni fún ọ nígbà tí ìwọ bá wọlé, ìbùkún ni fún ọ nígbà tí ìwọ bá jáde.
Nĩũrĩrathimagwo rĩinũkĩro-inĩ rĩa gwaku mũciĩ o na riumagarĩro-inĩ.
7 Olúwa yóò gbà fún ọ pé gbogbo ọ̀tá tí ó dìde sí ọ yóò bì ṣubú níwájú rẹ. Wọn yóò tọ̀ ọ́ wá ní ọ̀nà kan ṣùgbọ́n wọn yóò sá fún ọ ní ọ̀nà méje.
Jehova nĩarĩĩtũmaga thũ iria ingĩarahũka igũũkĩrĩre ihootagĩrwo mbere yaku. Irĩkũhithũkagĩra na njĩra ĩmwe, no irĩkũũragĩra na njĩra mũgwanja.
8 Olúwa yóò rán ìbùkún sí ọ àti sí ohun gbogbo tí o bá dáwọ́ rẹ lé. Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún un fún ọ nínú ilẹ̀ tí ó ń fi fún ọ.
Jehova nĩagatũma kĩrathimo kũu makũmbĩ-inĩ maku o na ũndũ-inĩ o wothe ũngĩka na moko maku. Jehova Ngai waku nĩagakũrathimĩra bũrũri-inĩ ũcio arakũhe.
9 Olúwa yóò fi ọ́ múlẹ̀ bí ènìyàn mímọ́, bí ó ti ṣe ìlérí fún ọ lórí ìbúra, bí o bá pa àṣẹ Olúwa Ọlọ́run rẹ mọ́ tí o sì ń rìn ní ọ̀nà rẹ̀.
Jehova nĩagakũhaanda agũtue rũrĩrĩ rwake rũtheru o ta ũrĩa aakwĩrĩire na mwĩhĩtwa, ũngĩmenyerera maathani ma Jehova Ngai waku na ũthiiage na njĩra ciake.
10 Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn tí ó wà ní ayé yóò rí i pé a pè ọ́ ní orúkọ Olúwa, wọn yóò sì bẹ̀rù rẹ.
Hĩndĩ ĩyo nacio ndũrĩrĩ ciothe cia gũkũ thĩ nĩcikoona atĩ wĩtanĩtio na rĩĩtwa rĩa Jehova, nacio nĩigagwĩtigĩra.
11 Olúwa yóò fi àlàáfíà fún ọ ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́, fún ọmọ inú rẹ, irú ohun ọ̀sìn rẹ àti àwọn èso ilẹ̀ rẹ ní ilẹ̀ tí ó ti búra fún àwọn baba ńlá rẹ láti fún ọ.
Jehova nĩagakũhe ũgaacĩru mũingĩ, akũgaacĩrithie ũciari-inĩ wa nda yaku, na maciaro-inĩ ma ũhiũ waku, na maciaro-inĩ ma mĩgũnda yaku, kũu bũrũri-inĩ ũrĩa erĩire maithe manyu ma tene na mwĩhĩtwa atĩ nĩagakũhe.
12 Olúwa yóò ṣí ọ̀run sílẹ̀, ìṣúra rere rẹ̀ fún ọ, láti rọ òjò sórí ilẹ̀ rẹ ní àsìkò rẹ àti láti bùkún gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ ọ̀ rẹ. Ìwọ yóò yá ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ṣùgbọ́n ìwọ kò ní í yá lọ́wọ́ ẹnìkankan.
Jehova nĩakahingũra igũrũ, o kũu kũrĩ nyũmba cia mũthiithũ wa indo iria aheanaga, nĩguo oirĩrie bũrũri waku mbura hĩndĩ yayo yakinya, na arathime wĩra wothe wa moko maku. Nĩũgakombagĩra ndũrĩrĩ nyingĩ indo, no wee ndũgakomba kuuma kũrĩ mũndũ o na ũrĩkũ.
13 Olúwa yóò fi ọ́ ṣe orí, ìwọ kì yóò sì jẹ́ ìrù. Bí o bá fi etí sílẹ̀ sí àṣẹ Olúwa Ọlọ́run rẹ tí mo fi fún ọ kí o sì máa rọra tẹ̀lé wọn, ìwọ yóò máa wà lókè, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kì yóò wà ní ìsàlẹ̀ láé.
Jehova agaagũtua wa gũtongoria, no ti wa kũrigia. Ũngĩrũmbũiya maathani ma Jehova Ngai waku marĩa ndĩrakũhe ũmũthĩ, na ũmenyerere ũmarũmĩrĩre, ũrĩkoragwo hĩndĩ ciothe ũrĩ wa mbere na ndũgatuĩka wa kũrigagia.
14 Má ṣe yà sọ́tùn tàbí sósì kúrò, nínú èyíkéyìí àwọn àṣẹ tí mo fi fún ọ ní òní yìí, kí o má ṣe tẹ̀lé àwọn ọlọ́run mìíràn láti máa sìn wọ́n.
Ndũkanehũgũre mwena wa ũrĩo kana wa ũmotho ũtigane na rĩathani o na rĩmwe rĩa maya ndĩrakũhe ũmũthĩ, kana ũrũmagĩrĩre ngai ingĩ na ũcitungatagĩre.
15 Ṣùgbọ́n bí o kò bá gbọ́ ti Olúwa Ọlọ́run rẹ kí o sì rọra máa tẹ̀lé gbogbo àṣẹ àti òfin rẹ̀ tí mò ń fún ọ lónìí, gbogbo ègún yìí yóò wá sórí rẹ yóò sì máa bá ọ lọ.
No rĩrĩ, ũngĩaga gwathĩkĩra Jehova Ngai waku, na wage kũrũmĩrĩra wega maathani make mothe na irĩra cia watho wa kũrũmĩrĩrwo iria ndĩrakũhe ũmũthĩ, irumi ici ciothe nĩigagũkinyĩrĩra:
16 Ègún ni fún ọ ní ìlú, ègún ni fún ọ ní oko.
Nĩũkanyiitwo nĩ kĩrumi ũrĩ itũũra-inĩ inene o na ũnyiitwo nĩ kĩrumi ũrĩ mĩgũnda-inĩ.
17 Ègún ni fún agbọ̀n rẹ àti ọpọ́n ìpo-fúláwà rẹ.
Kĩondo gĩaku na ndĩrĩ yaku ya gũkandĩrwo mũtu nĩikanyiitwo nĩ kĩrumi.
18 Ègún ni fún ọmọ inú rẹ, àti èso ilẹ̀ rẹ, ìbísí màlúù rẹ àti ọmọ àgùntàn rẹ.
Ũciari wa nda yaku nĩũkanyiitwo nĩ kĩrumi, o na irio cia mũgũnda waku, na mahiũ maku, ma njaũ cia ngʼombe na tũũri twa ndũũru ciaku cia mbũri.
19 Ègún ni fún ọ nígbà tí o bá wọlé ègún sì ni fún ọ nígbà tí ìwọ bá jáde.
Nĩũkanyiitwo nĩ kĩrumi rĩinũkĩro-inĩ rĩa gwaku mũciĩ, na ũnyiitwo nĩ kĩrumi ũkiumagara.
20 Olúwa yóò rán ègún sórí rẹ, rúdurùdu àti ìfibú nínú gbogbo ohun tí o bá dáwọ́ rẹ lé, títí ìwọ yóò fi parun àti wá sí ìparun lójijì nítorí búburú tí o ti ṣe ní kíkọ̀ mi sílẹ̀.
Jehova nĩagakũrehithĩria irumi, na kĩrigiicano, na ikũũma ũndũ-inĩ ũrĩa wothe ũrĩĩkaga na guoko gwaku, nginya akũniine ũthire na ihenya nĩ ũndũ wa wĩhia ũrĩa wĩkĩte wa kũmũtiganĩria.
21 Olúwa yóò fi àjàkálẹ̀-ààrùn bá ọ jà títí tí yóò fi pa ọ́ run kúrò ní ilẹ̀ tí ò ń wọ̀ lọ láti ní.
Jehova nĩagakũhũũra na mĩrimũ nginya akũniine wehere bũrũri ũrĩa ũratoonya ũwĩgwatĩre.
22 Olúwa yóò kọlù ọ́ pẹ̀lú ààrùn ìgbẹ́, pẹ̀lú ibà àti àìsàn wíwú, pẹ̀lú ìjóni ńlá àti idà, pẹ̀lú ìrẹ̀dànù àti ìmúwòdù tí yóò yọ ọ́ lẹ́nu títí ìwọ yóò fi parun.
Jehova nĩagakũhũũra na mũrimũ wa kũhũrũrũka mwĩrĩ, na wa kũhiũha mwĩrĩ, na wa kũrugĩka, na agũcine na ũrugarĩ mũingĩ, na kwaga mbura, na mbaa na mbuu, maũndũ macio makũhũũre nginya makũniine.
23 Ojú ọ̀run tí ó wà lórí rẹ yóò jẹ́ idẹ, ilẹ̀ tí ń bẹ níṣàlẹ̀ rẹ yóò sì jẹ́ irin.
Matu marĩa marĩ igũrũ wa mũtwe waku nĩmagatuĩka gĩcango, nakuo thĩ waku gũtuĩke kĩgera.
24 Olúwa yóò yí òjò ilẹ̀ rẹ sí eruku àti ẹ̀tù; láti ọ̀run ni yóò ti máa sọ̀kalẹ̀ sí ọ, títí tí ìwọ yóò fi run.
Jehova nĩagatũma mbura ya bũrũri waku ĩtuĩke rũkũngũ na mũtutu; ĩgaakuurĩra yumĩte igũrũ nginya ũniinwo.
25 Olúwa yóò fi ọ́ gégùn ún láti ṣubú níwájú àwọn ọ̀tá rẹ. Ìwọ yóò tọ̀ wọ́n wá ní ọ̀nà kan ṣùgbọ́n ìwọ yóò sá fún wọn ní ọ̀nà méje, ìwọ yóò sì padà di ohun ìbẹ̀rù fún gbogbo ìjọba lórí ayé.
Jehova nĩagatũma ũhootwo nĩ thũ ciaku. Ũgaacihithũkĩra na njĩra ĩmwe, no ũciũrĩre na njĩra mũgwanja, na nĩ ũgaatuĩka kĩndũ kĩ magigi harĩ mothamaki mothe ma thĩ.
26 Òkú rẹ yóò jẹ́ oúnjẹ fún gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run àti fún ẹranko ayé, àti pé kò ní sí ẹnikẹ́ni tí yóò lé wọn kúrò.
Ciimba ciaku igaatuĩka irio cia nyoni ciothe cia rĩera-inĩ na cia nyamũ cia gũkũ thĩ, na gũtikagĩa mũndũ wa gũcihahũra ciũre.
27 Olúwa yóò bá ọ jà pẹ̀lú oówo, Ejibiti àti pẹ̀lú kókó, ojú egbò kíkẹ̀ àti ìhúnra.
Jehova nĩagakũhũũra na mahũha marĩa ma bũrũri wa Misiri, na mĩrimũ ya ngaaĩ, na ironda iratogota, na ũhere, na ndũkahona.
28 Olúwa yóò bá ọ jà pẹ̀lú ìsínwín, ojú fífọ́ àti rúdurùdu àyà.
Jehova nĩagakũhũũra na ũgũrũki na ũtumumu, na kĩrigiicano kĩa meciiria.
29 Ní ọ̀sán gangan ìwọ yóò fi ọwọ́ tálẹ̀ kiri bí ọkùnrin afọ́jú nínú òkùnkùn ìwọ kì yóò ṣe àṣeyọrí nínú ohun gbogbo tí o bá ń ṣe, ojoojúmọ́ ni wọn yóò máa ni ọ́ lára àti jà ọ́ ní olè, tí kò sì ní í sí ẹnìkan láti gbà ọ́.
Nĩũgathiĩ ũkĩhambatagĩria kũrĩ mũthenya barigici ta mũndũ mũtumumu arĩ nduma-inĩ. Ndũkagaacĩra ũndũ-inĩ o wothe ũgeeka; mũthenya o mũthenya nĩũkahinyagĩrĩrio na ũgatunywo indo ciaku, hatarĩ mũndũ ũngĩgũteithũra.
30 Ìwọ yóò gba ògo láti fẹ́ obìnrin kan ṣùgbọ́n ẹlòmíràn yóò gbà á yóò sì tẹ́ ẹ́ ní ògo. Ìwọ yóò kọ́ ilé, ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò gbé ibẹ̀. Ìwọ yóò gbin ọgbà àjàrà, ṣùgbọ́n ìwọ kò tilẹ̀ ní gbádùn èso rẹ.
Nĩ ũkaagĩa kĩrĩĩko na mũndũ-wa-nja gĩa kũmũhikia, no mũndũ ũngĩ nĩakamuoya akome nake. Nĩũgaka nyũmba no ndũkamĩtũũra. Nĩũkahaanda mũgũnda wa mĩthabibũ no ndũkambĩrĩria gũkenera maciaro mayo.
31 Màlúù rẹ yóò di pípa níwájú rẹ, ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò jẹ nǹkan kan nínú rẹ̀. Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ yóò sì di mímú pẹ̀lú agbára kúrò lọ́dọ̀ rẹ, a kì yóò sì da padà. Àgùntàn rẹ yóò di mímú fún àwọn ọ̀tá rẹ, ẹnìkankan kò sì ní gbà á.
Ndegwa yaku nĩĩgathĩnjwo ũkĩonaga na maitho maku, no ndũkamĩrĩa. Ũgaatunywo ndigiri yaku na hinya na ndĩgacookio. Ngʼondu ciaku nĩikaneanwo kũrĩ thũ ciaku na gũtirĩ mũndũ ũgaaciteithũkia.
32 Àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin rẹ yóò di mímú fún àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, ìwọ yóò sì fi ojú rẹ ṣọ́nà dúró dè wọ́n láti ọjọ́ dé ọjọ́, ìwọ yóò sì jẹ́ aláìlágbára láti gbé ọwọ́.
Aanake aku na airĩtu aku nĩmakaneanwo kũrĩ rũrĩrĩ rũngĩ, namo maitho maku mathire hinya ũkĩmacũthĩrĩria mũthenya o mũthenya, na ndũkahota gwĩka ũndũ na guoko gwaku.
33 Èso ilẹ̀ rẹ àti gbogbo iṣẹ́ làálàá rẹ ni orílẹ̀-èdè mìíràn tí ìwọ kò mọ̀ yóò sì jẹ, ìwọ yóò jẹ́ kìkì ẹni ìnilára àti ẹni ìtẹ̀mọ́lẹ̀.
Rũrĩrĩ ũtooĩ nĩrũkarĩa irio cia bũrũri iria ũrutĩire wĩra, na gũtirĩ kĩndũ ũkaagĩa nakĩo, tiga o kũhinyĩrĩrio gũkĩru matukũ maku mothe.
34 Ìran tí ojú rẹ yóò rí, yóò sọ ọ́ di òmùgọ̀.
Maũndũ marĩa ũkoona nĩ magaatũma ũgũrũke.
35 Olúwa yóò lu eékún àti ẹsẹ̀ rẹ pẹ̀lú oówo dídùn tí kò le san tán láti àtẹ̀lé méjèèjì rẹ lọ sí òkè orí rẹ.
Jehova nĩakahũũra maru maku na magũrũ maku na mahũha marĩ ruo matangĩhona, namo mahunje kuuma makinya maku nginya ruototia rwa mũtwe waku.
36 Olúwa yóò lé ọ àti ọba tí ó yàn lórí rẹ lọ sí orílẹ̀-èdè tí ìwọ kò mọ̀ tàbí ti àwọn baba rẹ kò mọ̀. Ibẹ̀ ni ìwọ̀ yóò sì sin ọlọ́run mìíràn, ọlọ́run igi àti òkúta.
Jehova nĩagagũtwara hamwe na mũthamaki ũrĩa wĩrũgamĩirie agwathage kũrĩ rũrĩrĩ ũtooĩ kana rũkamenywo nĩ maithe manyu. Ũrĩ kũu nĩũkahooyaga ngai ingĩ, ngai cia mĩtĩ na cia mahiga.
37 Ìwọ yóò di ẹni ìyanu, àti ẹni òwe, àti ẹni ìfisọ̀rọ̀ sọ nínú gbogbo orílẹ̀-èdè tí Olúwa yóò darí rẹ sí.
Ũgaatuĩka kĩndũ kĩ magigi, na kĩndũ gĩa gũthekererwo na kũnyararwo nĩ ndũrĩrĩ ciothe kũu Jehova agaagũtwara.
38 Ìwọ yóò gbin irúgbìn púpọ̀ ṣùgbọ́n ìwọ yóò kórè kékeré, nítorí eṣú yóò jẹ ẹ́ run.
Ũkaahaanda mbegũ nyingĩ mũgũnda-inĩ no ũkaagetha o tũnini, nĩ ũndũ nĩikarĩĩo nĩ ngigĩ.
39 Ìwọ yóò gbin ọgbà àjàrà púpọ̀ ìwọ yóò sì ro wọ́n ṣùgbọ́n kò ní mú wáìnì náà tàbí kó àwọn èso jọ, nítorí kòkòrò yóò jẹ wọ́n run.
Ũkaahaanda mĩgũnda ya mĩthabibũ na ũmĩrĩmĩre, no ndũkanyua ndibei yayo kana ũtue thabibũ, nĩ ũndũ igunyũ nĩigacirĩa.
40 Ìwọ yóò ní igi olifi jákèjádò ilẹ̀ rẹ ṣùgbọ́n ìwọ kò ní lo òróró náà, nítorí olifi náà yóò rẹ̀ dànù.
Ũgaakorwo na mĩtĩ ya mĩtamaiyũ bũrũri-inĩ waku wothe, no ndũkahũthĩra maguta mayo, nĩ ũndũ ndamaiyũ nĩigaitĩka thĩ.
41 Ìwọ yóò ní àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin ṣùgbọ́n ìwọ kò nípa wọ́n mọ́, nítorí wọn yóò lọ sí ìgbèkùn.
Ũkaagĩa na aanake na ũgĩe na airĩtu no ndũgatũũra nao, nĩ ũndũ nĩmagatahwo mathiĩ ũkombo-inĩ.
42 Ọ̀wọ́ eṣú yóò gba gbogbo àwọn igi rẹ àti àwọn èso ilẹ̀ rẹ.
Mĩrumbĩ ya ngigĩ nĩĩkegwatĩra mĩtĩ yaku yothe na ĩrĩe irio cia bũrũri waku.
43 Àjèjì tí ń gbé láàrín rẹ yóò gbé sókè gíga jù ọ́ lọ, ṣùgbọ́n ìwọ yóò máa di ìrẹ̀sílẹ̀.
Mũndũ wa kũngĩ ũrĩa ũtũũranagia na inyuĩ agaakĩrĩrĩria kwambatĩra igũrũ rĩaku, na we ũkĩrĩrĩrie o kũnyiiha.
44 Yóò yà ọ́, ṣùgbọ́n o kì yóò yà á, òun ni yóò jẹ́ orí, ìwọ yóò jẹ́ ìrù.
Nĩ agagũkombagĩra nowe ndũkamũkombagĩra. Agaatuĩka wa gũtongoria nawe ũtuĩke wa kũrigia.
45 Gbogbo ègún yìí yóò wá sórí rẹ, wọn yóò lé ọ wọn yóò sì bá ọ títí tí ìwọ yóò fi parun, nítorí ìwọ kò gbọ́rọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ, ìwọ kò sì kíyèsi àṣẹ àti òfin tí ó fi fún ọ.
Irumi ici ciothe nĩigagũkinyĩrĩra. Nĩigathingatana nawe igũtoorie nginya ikũniine, nĩ tondũ ndwathĩkĩire Jehova Ngai waku, na ndũmenyereire maathani na irĩra cia watho wa kũrũmĩrĩrwo iria aakũheire.
46 Wọn yóò jẹ́ àmì àti ìyanu fún ọ àti fún irú-ọmọ rẹ títí láé.
Igaatuĩka kĩmenyithia na igegania harĩwe, o na harĩ njiaro ciaku nginya tene.
47 Nítorí ìwọ kò sin Olúwa Ọlọ́run rẹ ní ayọ̀ àti inú dídùn ní àkókò àlàáfíà.
Tondũ ndũigana gũtungatĩra Jehova Ngai waku ũrĩ na gĩkeno na ũcanjamũkĩte hĩndĩ ya ũgaacĩru,
48 Nítorí náà nínú ebi àti òǹgbẹ, nínú ìhòhò àti àìní búburú, ìwọ yóò sin àwọn ọ̀tá à rẹ tí Olúwa rán sí ọ. Yóò sì fi àjàgà irin bọ̀ ọ́ ní ọrùn, títí yóò fi run ọ́.
tondũ ũcio ũgaatungatĩra thũ ciaku iria Jehova agaagũtũmĩra igũũkĩrĩre, ũrĩ mũhũtu na ũnyootiĩ, na ũrĩ njaga na ũrĩ mũthĩĩnĩku mũno. Nĩagagwĩkĩra icooki rĩa kĩgera ngingo nginya akũniine.
49 Olúwa yóò mú àwọn orílẹ̀-èdè wá sí ọ láti ọ̀nà jíjìn, bí òpin ayé, bí idì ti ń bẹ́ láti orí òkè sílẹ̀, orílẹ̀-èdè tí ìwọ kò gbọ́ èdè wọn.
Jehova nĩagakũrehithĩria rũrĩrĩ ruumĩte kũraya, rũgũũkĩrĩre, kuuma ituri-inĩ cia thĩ, rũmbũkĩte o ta nderi, rũrĩrĩ ũtangĩmenya rwario rwa ruo,
50 Orílẹ̀-èdè tí ó rorò tí kò ní ojúrere fún àgbà tàbí àánú fún ọmọdé.
rũrĩrĩ rwa gwĩtigĩrwo, rũtangĩtĩĩa andũ akũrũ kana rũiguĩre andũ ethĩ tha.
51 Wọn yóò jẹ ohun ọ̀sìn rẹ run àti àwọn èso ilẹ̀ rẹ títí tí ìwọ yóò fi parun. Wọn kì yóò fi hóró irúgbìn kan fún ọ, wáìnì tuntun tàbí òróró, tàbí agbo ẹran màlúù rẹ kankan tàbí ọ̀wọ́ ẹran àgùntàn rẹ títí ìwọ yóò fi run.
Nĩmakarĩa njaũ cia mahiũ maku, na marĩe maciaro ma bũrũri waku nginya makũniine. Matigagũtigĩria ngano, kana ndibei ya mũhihano, kana maguta, o na kana magũtigĩre njaũ o na ĩmwe ya ndũũru cia ngʼombe ciaku kana tũũri twa rũũru rwa mbũri ciaku, nginya ũthĩĩnĩke biũ.
52 Wọn yóò gbógun ti gbogbo ìlú rẹ títí tí odi ìdáàbòbò gíga yẹn tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé yóò fi wó lulẹ̀. Wọn yóò gbógun ti gbogbo ìlú rẹ jákèjádò ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ ń fún ọ.
Nĩmakarigiicĩria matũũra mothe manene guothe bũrũri-inĩ waku, o nginya thingo icio ndaihu ciakĩtwo na hinya na wĩhokete imomoke. Nĩmakarigiicĩria matũũra manene mothe marĩa marĩ bũrũri-inĩ ũrĩa Jehova Ngai waku egũkũhe.
53 Ìwọ ó sì jẹ èso ọmọ inú rẹ̀, ẹran-ara àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti ti àwọn ọmọ rẹ obìnrin tí Olúwa Ọlọ́run ti fi fún ọ; nínú ìdótì náà àti nínú ìhámọ́ náà tí àwọn ọ̀tá rẹ yóò há ọ mọ́.
Tondũ wa thĩĩna ũrĩa ũkaareherwo nĩ thũ yaku hĩndĩ ya kũrigiicĩrio, nĩ ũkaarĩa maciaro ma nda, ũrĩe nyama cia ariũ na airĩtu arĩa Jehova Ngai waku akũheete.
54 Ọkùnrin tí àwọ̀ rẹ̀ tutù nínú yín, tí ó sì ṣe ẹlẹgẹ́, ojú rẹ̀ yóò korò sí arákùnrin rẹ̀ àti sí aya oókan àyà rẹ̀, àti sí ìyókù ọmọ rẹ̀ tí òun jẹ kù.
O na mũndũ ũrĩa mũhooreri mũno na ũrĩ tha gatagatĩ-inĩ kanyu ndakaiguĩra mũrũ wa nyina tha, kana mũtumia wake ũrĩa endete, kana ciana ciake iria itigaire,
55 Bẹ́ẹ̀ ni kì yóò fún ẹnikẹ́ni nínú ẹran-ara àwọn ọmọ rẹ̀ tí ó ń jẹ, nítorí kò sí ohun kan tí ó kù sílẹ̀ fún un nínú ìdótì náà àti ìhámọ́, tí àwọn ọ̀tá yóò fi há ọ mọ́ ní ibodè rẹ gbogbo.
na ndarĩ mũndũ o na ũmwe wao akaahe nyama cia ciana ciake icio araarĩa. Icio nocio kĩndũ kĩrĩa agaakorwo atigĩtie nĩ ũndũ wa thĩĩna ũrĩa thũ yaku ĩgaakũrehere hĩndĩ ĩrĩa ĩkaarigiicĩria matũũra maku manene mothe.
56 Obìnrin tí àwọ̀ rẹ̀ tutù nínú yín, tí ó sì ṣe ẹlẹgẹ́, tí kò jẹ́ dáṣà láti fi àtẹ́lẹsẹ̀ ẹ rẹ̀ kan ilẹ̀ nítorí ìkẹ́ra àti ìwà ẹlẹgẹ́, ojú u rẹ̀ yóò korò sí ọkọ oókan àyà rẹ̀, àti sí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àti ọmọ rẹ̀ obìnrin,
Mũndũ-wa-nja ũrĩa mũhooreri mũno na ũrĩ tha gatagatĩ-inĩ kanyu, ũcio ũrĩ tha mũno na mũhooreri nginya ndangĩũmĩrĩria kũhutia thĩ na ikinya rĩake, nĩakaima mũthuuriwe ũrĩa endete, na mũriũ kana mwarĩ,
57 àti sí ọmọ rẹ̀ tí ó ti agbede-méjì ẹsẹ̀ rẹ̀ jáde, àti sí àwọn ọmọ rẹ̀ tí yóò bí. Nítorí òun ó jẹ wọ́n ní ìkọ̀kọ̀, nítorí àìní ohunkóhun nínú ìdótì àti ìhámọ́ náà, tí àwọn ọ̀tá yóò fi há ọ mọ́ ní ibodè rẹ.
njogu ĩrĩa yumĩte nda yake na ciana iria agaciara. Nĩgũkorwo no ende gũcirĩa na hitho hĩndĩ ĩyo ya kũrigiicĩrio na ya thĩĩna ũrĩa thũ ciaku igaakũrehere kũu matũũra-inĩ manene manyu.
58 Bí ìwọ kò bá rọra tẹ̀lé gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ òfin yìí, tí a kọ sínú ìwé yìí, tí ìwọ kò sì bu ọlá fún ògo yìí àti orúkọ dáradára: orúkọ Olúwa Ọlọ́run rẹ,
Ũngĩaga kũrũmĩrĩra wega ciugo ciothe cia watho ũyũ, iria ciandĩkĩtwo ibuku-inĩ rĩĩrĩ, na wage gũtĩĩa rĩĩtwa rĩĩrĩ rĩrĩ riiri na rĩa gwĩtigĩrwo, rĩa Jehova Ngai waku,
59 Olúwa yóò sọ ìyọnu rẹ di ìyanu, àti ìyọnu irú-ọmọ ọ̀ rẹ, àní àwọn ìyọnu ńlá èyí tí yóò pẹ́, àti ààrùn búburú èyí tí yóò pẹ́.
Jehova nĩagakũrehithĩria mĩthiro ya kũmakania, wee na njiaro ciaku, na thĩĩna mũnene na wa ihinda iraaya, o na mĩrimũ mĩũru na ya gũikara mũno.
60 Olúwa yóò mú gbogbo ààrùn Ejibiti tí ó mú ẹ̀rù bà ọ́ wá padà bá ọ, wọn yóò sì lẹ̀ mọ́ ọ.
Nĩagakũrehithĩria mĩrimũ yothe ya bũrũri wa Misiri ĩrĩa wetigĩrĩte, nayo nĩĩgakwĩgwatĩrĩra.
61 Olúwa yóò tún mú onírúurú àìsàn àti ìpọ́njú tí a kò kọ sínú ìwé òfin yìí wá sórí rẹ, títí ìwọ yóò fi run.
O na ningĩ Jehova nĩagakũrehithĩria mĩrimũ ya mĩthemba yothe o na mathĩĩna marĩa matarĩ maandĩke Ibuku-inĩ rĩĩrĩ rĩa Watho, nginya ũniinwo.
62 Ìwọ tí ó dàbí àìmoye bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run yóò ṣẹ́ku kékeré níye, nítorí tí o kò ṣe ìgbọ́ràn sí Olúwa Ọlọ́run rẹ.
Inyuĩ mwarĩ aingĩ ta njata cia igũrũ, mũgaatigara o andũ anini mũgĩtarwo, nĩ ũndũ wa kwaga gwathĩkĩra Jehova Ngai wanyu.
63 Gẹ́gẹ́ bí ó ti dùn mọ́ Olúwa nínú láti mú ọ ṣe rere àti láti pọ̀ si ní iye, bẹ́ẹ̀ ni yóò dùn mọ́ ọ nínú láti bì ọ́ ṣubú kí ó sì pa ọ́ run. Ìwọ yóò di fífà tu kúrò lórí ilẹ̀ tí ò ń wọ̀ lọ láti ní.
O ta ũrĩa Jehova aakeneire kũmũgaacĩrithia na kũmũingĩhia, noguo agaakena akĩmũharagania na akĩmũniina. Nĩmũkamunywo mweherio bũrũri ũrĩa mũrathiĩ mũwĩgwatĩre.
64 Nígbà náà ni Olúwa yóò fọ́n ọ ká láàrín gbogbo orílẹ̀-èdè, láti òpin kan ní ayé sí òmíràn. Níbẹ̀ ni ìwọ yóò ti sin ọlọ́run mìíràn: ọlọ́run igi àti ti òkúta. Èyí tí ìwọ àti àwọn baba rẹ kò mọ̀.
Ningĩ Jehova nĩagakũhurunja ndũrĩrĩ-inĩ ciothe, kuuma gĩturi kĩmwe gĩa thĩ nginya kĩrĩa kĩngĩ. Ũrĩ kũu ũkaahooyaga ngai ingĩ, ngai cia mĩtĩ na cia mahiga, iria wee o na maithe manyu mũtooĩ.
65 Ìwọ kì yóò sinmi láàrín àwọn orílẹ̀-èdè náà, kò sí ibi ìsinmi fún àtẹ́lẹsẹ̀ rẹ. Níbẹ̀ ni Olúwa yóò ti fún ọ ní ọkàn ìnàngà, àárẹ̀ ojú, àti àìnírètí àyà.
Ũrĩ gatagatĩ-inĩ ka ndũrĩrĩ icio ndũkoona ũndũ mwega, kana wone handũ ha kũhurũkia ikinya rĩa kũgũrũ gwaku. Mũrĩ kũu Jehova nĩagatũma ũtangĩke meciiria na maitho mage kuona, o na ũũrwo nĩ hinya.
66 Ìwọ yóò gbé ní ìdádúró ṣinṣin, kún fún ìbẹ̀rùbojo lọ́sàn án àti lóru, bẹ́ẹ̀ kọ́ láé ni ìwọ yóò rí i ní àrídájú wíwà láyé rẹ.
Ũgaatũũra na wagagu, ũiyũrĩtwo nĩ guoya ũtukũ na mũthenya, ũtarĩ na ma ya ũtũũro waku.
67 Ìwọ yóò wí ní òwúrọ̀ pé, “Bí ó tilẹ̀ lè jẹ́ pé ìrọ̀lẹ́ nìkan ni!” Nítorí ẹ̀rù tí yóò gba ọkàn rẹ àti ìran tí ojú rẹ yóò máa rí.
Rũciinĩ ũkoiga atĩrĩ, “Naarĩ korwo nĩ hwaĩ-inĩ!” Naguo hwaĩ-inĩ ũkoiga atĩrĩ, “Naarĩ korwo nĩ rũciinĩ!” Tondũ wa kĩmakania kĩrĩa gĩgaakorwo kĩmũiyũrĩte ngoro cianyu, na maũndũ marĩa maitho manyu makeyonera.
68 Olúwa yóò rán ọ padà nínú ọkọ̀ sí Ejibiti sí ìrìnàjò tí mo ní ìwọ kì yóò lọ mọ́. Níbẹ̀ ni ìwọ yóò tún fi ara rẹ fún àwọn ọ̀tá à rẹ gẹ́gẹ́ bí ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin, ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí yóò rà ọ́.
Jehova akaamũcookia bũrũri wa Misiri na meeri, rũgendo rũrĩa ndoigire mũtikanarũthiĩ rĩngĩ. Mũrĩ kũu nĩkuo mũkeneana mũgũrwo nĩ thũ cianyu, mũrĩ ngombo cia arũme na cia andũ-a-nja, no gũtirĩ mũndũ ũkaamũgũra.