< Deuteronomy 27 >

1 Mose àti àwọn àgbàgbà Israẹli pàṣẹ fún àwọn ènìyàn pé, “Pa gbogbo àṣẹ tí mo fún ọ lónìí mọ́.
Hathnukkhu, Mosi hoi Isarel kacuenaw ni taminaw koe a dei awh e teh, sahnin kai ni ka hruek e kâpoelawk pueng hah tarawi awh.
2 Nígbà tí o bá ti kọjá a Jordani sí inú ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ ń fún ọ, gbé kalẹ̀ lára àwọn òkúta ńlá àti aṣọ ìlekè rẹ pẹ̀lú ẹfun.
Nang ni Jordan palang na raka teh, BAWIPA Cathut ni na poe e ram dawk na pha toteh, kalen e talungnaw hah ung nateh, thungpangaw hoi na hluk han.
3 Kí ìwọ kí ó kọ gbogbo ọ̀rọ̀ òfin yìí sára wọn nígbà tí ìwọ bá ti ń rékọjá láti wọ ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ ń fún ọ, ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin, gẹ́gẹ́ bí Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín ti ṣèlérí fún ọ.
Mintoenaw ni a bawk awh e Cathut BAWIPA ni a lawkkam ao e patetlah nang na poe e ram, khoitui hoi maitosanutui a lawngnae ram kâen hanelah na raka hnukkhu, hete kâlawk dawk e lawklung pueng hah hotnaw dawk na thut han.
4 Àti nígbà tí o bá ti kọjá a Jordani, kí o gbé òkúta yìí kalẹ̀ sórí i Ebali, bí mo ti pa à láṣẹ fún ọ lónìí, kí o sì wọ̀ wọ́n pẹ̀lú ẹfun.
Jordan palang raka hnukkhu, sahnin kai ni lawk na thui e talungnaw hah, Ebal mon dawk na ung vaiteh, mirangtalai hoi na kanan han.
5 Kọ́ pẹpẹ síbẹ̀ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, pẹpẹ òkúta. Má ṣe lo ohun èlò irin lórí wọn.
Hote hmuen koehai na BAWIPA Cathut hanelah,
6 Kí ìwọ kí ó mọ pẹpẹ pẹ̀lú òkúta àìgbẹ́ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, kí ìwọ kí ó sì máa rú ẹbọ sísun ni orí rẹ̀ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ.
thuengnae khoungroe hah talung hoi na sak awh han. Sum hno laipalah, pathei hoehe talung hoi na sak han. Nang BAWIPA Cathut hah hote khoungroe dawk hmaisawi thuengnae na thueng han.
7 Rú ẹbọ àlàáfíà níbẹ̀ kí o jẹ wọ́n, kí o sì yọ̀ níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ.
Roum thuengnae hai na thueng vaiteh, hote hmuen koe na canei awh vaiteh, a hmalah nawmnae na sak awh han.
8 Kí o sì kọ gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ òfin yìí ketekete sórí òkúta tí ó ti gbé kalẹ̀.”
Hote talung dawkvah, hete lawknaw hah kamcengcalah na thut han.
9 Nígbà náà ni Mose àti àwọn àlùfáà tí wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi, sọ fún Israẹli pé, “Ẹ dákẹ́ ẹ̀yin Israẹli, kí ẹ sì fetísílẹ̀! O ti wá di ènìyàn Olúwa Ọlọ́run rẹ báyìí.
Hathnukkhu, Mosi hoi vaihmanaw, Levihnaw niyah, Oe Isarel miphun, kâhruetcuet laihoi thai haw. Sahnin nang teh, BAWIPA Cathut e miphun lah na o toe.
10 Gbọ́rọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ kí o sì tẹ̀lé àṣẹ àti òfin rẹ̀ tí mo ń fi fún ọ lónìí.”
Hatdawkvah, na BAWIPA Cathut e lawknaw hah na tarawi han. Sahnin kaimouh ni patuen ka dei awh e kâpoelawknaw hoi phunglawknaw hah tarawi telah Isarelnaw pueng hah a dei pouh awh.
11 Ní ọjọ́ kan náà Mose pàṣẹ fún àwọn ènìyàn pé.
Mosi ni hot hnin vah, taminaw koe kâ a poe e teh,
12 Nígbà tí ìwọ bá ti kọjá a Jordani, àwọn ẹ̀yà yìí yóò dúró lórí òkè Gerisimu láti súre fún àwọn ènìyàn: Simeoni, Lefi, Juda, Isakari, Josẹfu àti Benjamini.
nangmouh ni Jordan palang na raka awh hnukkhu, taminaw yawhawi poe hanelah Gerizim mon dawk ka kangdout hane naw teh: Simeon, Levih, Judah, Issakhar, Joseph, hoi Benjamin tinaw doeh.
13 Àwọn ẹ̀yà yìí yóò dúró lórí òkè Ebali láti gé ègún: Reubeni, Gadi, àti Aṣeri, àti Sebuluni, Dani, àti Naftali.
Thoebo hanelah Ebal mon dawk ka kangdout hane naw teh: Gad, Reubeb, Asher, Zebulun, Dan, hoi Napthali tinaw doeh.
14 Àwọn ẹ̀yà Lefi yóò ké sí gbogbo ènìyàn Israẹli ní ohùn òkè:
Hatnavah, Levihnaw ni Isarelnaw koe puenghoi a hramkhai hane lawk teh,
15 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó fín ère tàbí gbẹ́ òrìṣà ohun tí ó jẹ́ ìríra níwájú Olúwa, iṣẹ́ ọwọ́ oníṣọ̀nà tí ó gbé kalẹ̀ ní ìkọ̀kọ̀.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
BAWIPA ni a panuet e hno, kutsak hlun e meikaphawk ka sak niteh, a kamnuehoehnae koe ka tat e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
16 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó dójútì baba tàbí ìyá rẹ̀.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Manu hoeh pawiteh na pa ka dudam e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
17 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó yí òkúta ààlà aládùúgbò o rẹ̀.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Imri e lawrilung ka puen e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
18 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó ṣi afọ́jú lọ́nà ní ojú ọ̀nà.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Mitdawn lam ka phen sak e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
19 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó yí ìdájọ́ po fún àlejò, aláìní baba tàbí opó.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Kalan lah lawkceng navah, miphun alouknaw, naranaw, lahmainunaw hah kamsoum hoeh lah ka sung sak e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
20 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó dùbúlẹ̀ pẹ̀lú ìyàwó baba rẹ̀, nítorí ó ti dójúti ibùsùn baba rẹ̀.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Na pa hoi dueng kâkuen e na pa e a yu hah ka ipkhai e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
21 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ẹranko.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Saringnaw buetbuet touh ka ipkhai e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
22 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó dùbúlẹ̀ pẹ̀lú arábìnrin rẹ̀, ọmọbìnrin baba rẹ̀ tàbí ọmọbìnrin ìyá rẹ̀.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Na pa e canu, manu e canu, mae tawncanu ka ipkhai e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
23 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó dùbúlẹ̀ pẹ̀lú ìyá ìyàwó o rẹ̀.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Yu e manu ka ipkhai e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
24 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó pa aládùúgbò rẹ̀ ní ìkọ̀kọ̀.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Imri hah arulahoi ka thet e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
25 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti pa ènìyàn láìjẹ̀bi.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Yon ka tawn hoehe tami thei hanelah aphu ka lat e tami teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.
26 “Ègún ni fún ọkùnrin náà tí kò gbé ọ̀rọ̀ òfin yìí ró nípa ṣíṣe wọ́n.” Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”
Hete kâlawk dawk e lawklungnaw ka cak sak hoehe teh yawthoenae awm lawiseh telah thoe a bo awh vaiteh, tami pueng ni Amen ati awh han.

< Deuteronomy 27 >