< Deuteronomy 25 >

1 Nígbà tí àwọn ènìyàn méjì bá ń jà, kí wọn kó ẹjọ́ lọ sí ilé ìdájọ́, kí àwọn onídàájọ́ dá ẹjọ́ náà, kí wọn dá àre fún aláre àti ẹ̀bi fún ẹlẹ́bi.
Кынд дой оамень вор авя о чартэ ынтре ей ши се вор ынфэциша ынаинтя жудекэций ка сэ фие жудекаць, челуй невиноват сэ-й дя друмул, яр пе чел виноват сэ-л осындяскэ.
2 Bí ó bá tọ́ láti na ẹlẹ́bi, kí onídàájọ́ dá a dọ̀bálẹ̀ kí a sì nà án ní ojú u rẹ̀ ní iye pàṣán tí ó tọ́ sí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó sẹ̀.
Дакэ чел виноват есте осындит сэ фие бэтут, жудекэторул сэ пунэ сэ-л ынтиндэ ла пэмынт ши сэ-й дя ын фаца луй ун нумэр де ловитурь потривит ку греутатя виней луй.
3 Ṣùgbọ́n kò gbọdọ̀ fún un ju ogójì pàṣán lọ. Bí ó bá nà án ju bẹ́ẹ̀ lọ, arákùnrin rẹ̀ yóò di ẹni ìrẹ̀sílẹ̀ ní ojú rẹ̀.
Сэ ну пунэ сэ-й дя май мулт де патрузечь де ловитурь, ка ну кумва, дынду-й май мулте ловитурь декыт атыт, фрателе тэу сэ фие ынжосит ынаинтя та.
4 Ìwọ kò gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu.
Сэ ну леӂь гура боулуй кынд треерэ грыул.
5 Bí àwọn arákùnrin bá ń gbé pọ̀, tí ọ̀kan nínú wọn bá sì kú, tí kò sí ní ọmọkùnrin, kí aya òkú má ṣe ní àlejò ará òde ní ọkọ rẹ̀. Arákùnrin ọkọ rẹ̀ ni kí ó wọlé tọ̀ ọ́, kí ó fi ṣe aya, kí ó sì ṣe iṣẹ́ arákùnrin ọkọ fún un.
Кынд фраций вор локуи ымпреунэ ши унул дин ей ва мури фэрэ сэ ласе копий, неваста мортулуй сэ ну се мэрите афарэ, ку ун стрэин, чи кумнатул ей сэ се дукэ ла еа, с-о я де невастэ ши сэ се ынсоаре ку еа ка кумнат.
6 Ọmọkùnrin tí ó bá kọ́ bí ni yóò máa jẹ́ orúkọ arákùnrin rẹ̀ tí ó kú náà, kí orúkọ rẹ̀ má ba á parẹ́ ní Israẹli.
Ынтыюл нэскут пе каре-л ва наште сэ моштеняскэ пе фрателе чел морт ши сэ-й поарте нумеле, пентру ка нумеле ачеста сэ ну фие штерс дин Исраел.
7 Ṣùgbọ́n bí ọkùnrin náà kò bá fẹ́ fi aya arákùnrin rẹ̀ ṣe aya rẹ̀, obìnrin náà yóò lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn àgbàgbà ní ẹnu-bodè ìlú láti sọ pé, “Arákùnrin ọkọ ọ̀ mi kọ̀ láti gbé orúkọ arákùnrin rẹ̀ ró ní Israẹli. Kò ní ṣe ojúṣe rẹ̀ bí arákùnrin ọkọ mi sí mi.”
Дакэ омул ачеста ну вря сэ я пе кумнатэ-са, еа сэ се суе ла поарта четэций, ла бэтрынь, ши сэ спунэ: ‘Кумнатул меу ну вря сэ ридиче ын Исраел нумеле фрателуй сэу, ну вря сэ мэ я де невастэ дупэ дрептул де кумнат.’
8 Nígbà náà ni àwọn àgbàgbà ìlú rẹ̀ yóò pè é, wọn yóò sì bá sọ̀rọ̀. Bí ó bá sì kọ̀ jálẹ̀ tí ó bá sọ pé, “Èmi kò fẹ́ láti fẹ́ ẹ,”
Бэтрыний четэций сэ-л кеме ши сэ-й ворбяскэ. Дакэ ел стэруеште ши зиче: ‘Ну вряу с-о яу’,
9 opó arákùnrin rẹ̀ yìí yóò lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ ní ojú àwọn àgbàgbà ìlú rẹ̀, yóò yọ bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀ kan, yóò sì tu itọ́ sí ọkùnrin náà lójú, yóò sì wí pé, “Èyí ni ohun tí a ṣe sí ọkùnrin tí kò jẹ́ kí ìdílé arákùnrin rẹ̀ wà títí ayé.”
атунч кумнатэ-са сэ се апропие де ел ын фаца бэтрынилор, сэ-й скоатэ ынкэлцэминтя дин пичор ши сэ-л скуйпе ын фацэ. Ши луынд кувынтул, сэ зикэ: ‘Аша сэ се факэ омулуй каре ну воеште сэ ридиче каса фрателуй сэу.’
10 A ó sì mọ ìdílé arákùnrin yìí ní Israẹli gẹ́gẹ́ bí “Ìdílé tí a yọ bàtà rẹ̀.”
Ши каса луй се ва нуми ын Исраел ‘Каса челуй дескэлцат’.
11 Bí ọkùnrin méjì bá ń jà, tí ìyàwó ọ̀kan nínú wọn bá sì wá láti gbèjà ọkọ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ọkùnrin tí ń lù ú, tí ó sì nawọ́ di nǹkan ọkùnrin abẹ́ ẹ rẹ̀ mú.
Кынд дой оамень се вор черта унул ку алтул, ши неваста унуя се ва апропия сэ скоатэ пе бэрбатул сэу дин мына челуй че-л ловеште, дакэ ынтинде мына ши апукэ пе ачеста дин урмэ де пэрциле рушиноасе,
12 Ìwọ yóò gé ọwọ́ rẹ̀ náà kúrò. Má ṣe ṣàánú fún un.
сэ-й тай мына; сэ н-ай ничо милэ де еа.
13 Má ṣe ní oríṣìí ìtẹ̀wọ̀n méjì tó yàtọ̀ sí ara wọn nínú àpò rẹ, ọ̀kan wúwo àti ọ̀kan fífúyẹ́.
Сэ н-ай ын сакул тэу доуэ фелурь де греутэць, уна маре ши алта микэ.
14 Má ṣe ní oríṣìí ìwọ̀n méjì tí ó yàtọ̀ sí ara wọn ní ilé è rẹ: ọ̀kan fífẹ̀, ọ̀kan kékeré.
Сэ н-ай ын касэ доуэ фелурь де ефэ, уна маре ши алта микэ.
15 O gbọdọ̀ ní ìtẹ̀wọ̀n àti òsùwọ̀n pípé àti ti òtítọ́ nítorí náà kí ìwọ kí ó lè pẹ́ ní ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ fún ọ.
Чи сэ ай о греутате адевэратэ ши дряптэ, сэ ай о ефэ адевэратэ ши дряптэ, пентру ка сэ ай зиле мулте ын цара пе каре ць-о дэ Домнул Думнезеул тэу.
16 Nítorí Olúwa Ọlọ́run kórìíra ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe nǹkan wọ̀nyí, àní ẹnikẹ́ni tí ń ṣe àìṣòdodo.
Кэч орьчине фаче ачесте лукрурь, орьчине сэвыршеште о недрептате, есте о урычуне ынаинтя Домнулуй Думнезеулуй тэу.
17 Rántí ohun tí àwọn ará Amaleki ṣe sí i yín ní ọ̀nà nígbà tí ẹ̀ ń jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá.
Аду-ць аминте че ць-а фэкут Амалек пе друм, ла еширя воастрэ дин Еӂипт:
18 Nígbà tí àárẹ̀ mú un yín tí agara sì dá a yín, wọ́n pàdé e yín ní ọ̀nà àjò o yín, wọ́n gé àwọn tí ó rẹ̀yìn kúrò, wọn kò ní ìbẹ̀rù Ọlọ́run.
кум те-а ынтылнит пе друм ши, фэрэ ничо тямэ де Думнезеу, с-а арункат асупра та пе динапой, асупра тутурор челор че се тырау ла коадэ, кынд ерай обосит ши слеит де путерь.
19 Nígbà tí Olúwa Ọlọ́run yín bá fún un yín ní ìsinmi lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá yín tí ó yí i yín ká ní ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run ń fi fún yín láti ni ní ìní, ẹ̀yin yóò sì pa ìrántí Amaleki rẹ́ kúrò lábẹ́ ọ̀run. Má ṣe gbàgbé.
Кынд ыць ва да Домнул Думнезеул тэу одихнэ, дупэ че те ва избэви де тоць врэжмаший каре те ынконжоарэ, ын цара пе каре Домнул Думнезеул тэу ць-о дэ ка моштенире ши спре стэпынире, сэ штерӂь помениря луй Амалек де суб черурь – сэ ну уйць лукрул ачеста.

< Deuteronomy 25 >