< Deuteronomy 25 >

1 Nígbà tí àwọn ènìyàn méjì bá ń jà, kí wọn kó ẹjọ́ lọ sí ilé ìdájọ́, kí àwọn onídàájọ́ dá ẹjọ́ náà, kí wọn dá àre fún aláre àti ẹ̀bi fún ẹlẹ́bi.
Ki te mea he tautohe ta etahi, a ka haere mai kia whakawakia, a ka whakawakia e nga kaiwhakariterite; me whakatika e ratou ta te tika, me whakahe ta te he;
2 Bí ó bá tọ́ láti na ẹlẹ́bi, kí onídàájọ́ dá a dọ̀bálẹ̀ kí a sì nà án ní ojú u rẹ̀ ní iye pàṣán tí ó tọ́ sí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó sẹ̀.
A, ki te meinga te tangata kino kia whiua, na me mea ia e te kaiwhakariterite kia takoto, kia whiua ki mua i tona aroaro, kia rite ki tona kino te maha o nga whiu.
3 Ṣùgbọ́n kò gbọdọ̀ fún un ju ogójì pàṣán lọ. Bí ó bá nà án ju bẹ́ẹ̀ lọ, arákùnrin rẹ̀ yóò di ẹni ìrẹ̀sílẹ̀ ní ojú rẹ̀.
Kia wha tekau ana whakapanga ki a ia, kaua e maha ake: he mea hoki, ki te tuhene, a ka maha atu i enei nga whakapanga, na ka iti tou teina ki tau titiro.
4 Ìwọ kò gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu.
Kaua e whakamokatia te kau ina takahia e ia te witi.
5 Bí àwọn arákùnrin bá ń gbé pọ̀, tí ọ̀kan nínú wọn bá sì kú, tí kò sí ní ọmọkùnrin, kí aya òkú má ṣe ní àlejò ará òde ní ọkọ rẹ̀. Arákùnrin ọkọ rẹ̀ ni kí ó wọlé tọ̀ ọ́, kí ó fi ṣe aya, kí ó sì ṣe iṣẹ́ arákùnrin ọkọ fún un.
Ki te noho tahi te taina me te tuakana, a ka mate tetahi o raua, a kahore ana tama, kaua te wahine a te tangata i mate e marenatia ki waho, ki te tangata ke; me haere tona autane ki a ia, ka tango ai i a ia hei wahine mana, me mea ki a ia nga mea e tika ana ma te autane.
6 Ọmọkùnrin tí ó bá kọ́ bí ni yóò máa jẹ́ orúkọ arákùnrin rẹ̀ tí ó kú náà, kí orúkọ rẹ̀ má ba á parẹ́ ní Israẹli.
A, ka whanau tana matamua, ko ia hei whakarerenga iho mo te ingoa o tona tuakana, teina ranei, i mate nei, a ka kore tona ingoa e horoia atu i roto i a Iharaira.
7 Ṣùgbọ́n bí ọkùnrin náà kò bá fẹ́ fi aya arákùnrin rẹ̀ ṣe aya rẹ̀, obìnrin náà yóò lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn àgbàgbà ní ẹnu-bodè ìlú láti sọ pé, “Arákùnrin ọkọ ọ̀ mi kọ̀ láti gbé orúkọ arákùnrin rẹ̀ ró ní Israẹli. Kò ní ṣe ojúṣe rẹ̀ bí arákùnrin ọkọ mi sí mi.”
Ki te kahore taua tangata e pai ki te tango i tona auwahine, katahi ka haere tona auwahine ki te kuwaha, ki nga kaumatua, a ka mea, E kore toku autane e pai ki te whakatupu ingoa mo tona tuakana, teina ranei, i roto i a Iharaira, e kore e meatia e ia nga mea e tika ana ma toku autane.
8 Nígbà náà ni àwọn àgbàgbà ìlú rẹ̀ yóò pè é, wọn yóò sì bá sọ̀rọ̀. Bí ó bá sì kọ̀ jálẹ̀ tí ó bá sọ pé, “Èmi kò fẹ́ láti fẹ́ ẹ,”
Katahi ka karangatia ia e nga kaumatua o tona pa, a ka korero ratou ki a ia; a, ki te u tonu tana, a ka mea ia, E kore ahau e pai ki te tango i a ia;
9 opó arákùnrin rẹ̀ yìí yóò lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ ní ojú àwọn àgbàgbà ìlú rẹ̀, yóò yọ bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀ kan, yóò sì tu itọ́ sí ọkùnrin náà lójú, yóò sì wí pé, “Èyí ni ohun tí a ṣe sí ọkùnrin tí kò jẹ́ kí ìdílé arákùnrin rẹ̀ wà títí ayé.”
Katahi ka whakatata tona auwahine ki a ia i te tirohanga a nga kaumatua, a ka unu i tona hu i tona waewae, ka tuwha hoki ki tona mata, a ka korero ake, ka mea, Kia peneitia te tangata e kore e hanga i te whare o tona tuakana, teina ranei.
10 A ó sì mọ ìdílé arákùnrin yìí ní Israẹli gẹ́gẹ́ bí “Ìdílé tí a yọ bàtà rẹ̀.”
A ka huaina tona ingoa i roto i a Iharaira, Ko te whare o te tangata i unuhia nei tona hu.
11 Bí ọkùnrin méjì bá ń jà, tí ìyàwó ọ̀kan nínú wọn bá sì wá láti gbèjà ọkọ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ọkùnrin tí ń lù ú, tí ó sì nawọ́ di nǹkan ọkùnrin abẹ́ ẹ rẹ̀ mú.
Ki te whawhai etahi tangata ki a raua, a ka whakatata te wahine a tetahi ki te whakaora i tana tahu i te tangata e patu ana i a ia, a ka totoro tona ringa, ka mau hoki ki ona wahi ngaro;
12 Ìwọ yóò gé ọwọ́ rẹ̀ náà kúrò. Má ṣe ṣàánú fún un.
Me tapahi atu e koe tona ringa, kaua e tohu tou kanohi.
13 Má ṣe ní oríṣìí ìtẹ̀wọ̀n méjì tó yàtọ̀ sí ara wọn nínú àpò rẹ, ọ̀kan wúwo àti ọ̀kan fífúyẹ́.
Kaua e waiho i roto i tau kete nga kohatu pauna e kore e taurite, te mea nui, te mea iti.
14 Má ṣe ní oríṣìí ìwọ̀n méjì tí ó yàtọ̀ sí ara wọn ní ilé è rẹ: ọ̀kan fífẹ̀, ọ̀kan kékeré.
Kaua e waiho i roto i tou whare nga mehua e kore e taurite, te mea nui, te mea iti.
15 O gbọdọ̀ ní ìtẹ̀wọ̀n àti òsùwọ̀n pípé àti ti òtítọ́ nítorí náà kí ìwọ kí ó lè pẹ́ ní ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ fún ọ.
Hei te mea rite tonu, hei te mea tika, tau kohatu pauna; hei te mea rite tonu, hei te mea tika, tau mehua: kia roa ai ou ra ki te whenua e homai nei e Ihowa, e tou Atua, ki a koe.
16 Nítorí Olúwa Ọlọ́run kórìíra ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe nǹkan wọ̀nyí, àní ẹnikẹ́ni tí ń ṣe àìṣòdodo.
He mea whakarihariha hoki ki a Ihowa, ki tou Atua, te hunga katoa e pena ana, te hunga katoa e he ana te mahi.
17 Rántí ohun tí àwọn ará Amaleki ṣe sí i yín ní ọ̀nà nígbà tí ẹ̀ ń jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá.
Kia mahara ki ta Amareke i mea ai ki a koe i te ara, i to koutou putanga mai i Ihipa;
18 Nígbà tí àárẹ̀ mú un yín tí agara sì dá a yín, wọ́n pàdé e yín ní ọ̀nà àjò o yín, wọ́n gé àwọn tí ó rẹ̀yìn kúrò, wọn kò ní ìbẹ̀rù Ọlọ́run.
Ki tona tutakitanga ki a koe ki te ara, a patua iho tou hiku e ia, nga mea ngoikore katoa i muri i a koe, i a koe e hemo ana, e ngenge ana; a kihai ia i wehi ki te Atua.
19 Nígbà tí Olúwa Ọlọ́run yín bá fún un yín ní ìsinmi lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá yín tí ó yí i yín ká ní ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run ń fi fún yín láti ni ní ìní, ẹ̀yin yóò sì pa ìrántí Amaleki rẹ́ kúrò lábẹ́ ọ̀run. Má ṣe gbàgbé.
Mo reira e meinga koe e Ihowa, e tou Atua, kia okioki i ou hoariri katoa a tawhio noa, ki te whenua e homai nei e Ihowa, e tou Atua, ki a koe kia nohoia hei kainga tupu, me ukui rawa atu te maharatanga ki a Amareke i raro i te rangi; kei warewar e rawa koe.

< Deuteronomy 25 >