< Deuteronomy 25 >

1 Nígbà tí àwọn ènìyàn méjì bá ń jà, kí wọn kó ẹjọ́ lọ sí ilé ìdájọ́, kí àwọn onídàájọ́ dá ẹjọ́ náà, kí wọn dá àre fún aláre àti ẹ̀bi fún ẹlẹ́bi.
Tami reira kâyue pawiteh, lawkcengim vah a cei awh vaiteh, lawkcengkung ni ahnimanaw hah lawk a ceng han. Kalan e tami hah yon hloutsak nahanelah thoseh, ka yon e teh sungsak nahanelah thoseh lawk na ceng han.
2 Bí ó bá tọ́ láti na ẹlẹ́bi, kí onídàájọ́ dá a dọ̀bálẹ̀ kí a sì nà án ní ojú u rẹ̀ ní iye pàṣán tí ó tọ́ sí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó sẹ̀.
Ka yon e hah hem kamcu pawiteh, lawkcengkung ni a hmalah ao sak vaiteh, a yon hoi kamcu lah nâyittouh tie hoi a hem han.
3 Ṣùgbọ́n kò gbọdọ̀ fún un ju ogójì pàṣán lọ. Bí ó bá nà án ju bẹ́ẹ̀ lọ, arákùnrin rẹ̀ yóò di ẹni ìrẹ̀sílẹ̀ ní ojú rẹ̀.
Hatei, avai 40 hlak kapap lah na hem mahoeh. Hot hlak kapap lah na hem pawiteh, na hmaunawngha teh na hmalah yeirai a phu han doeh.
4 Ìwọ kò gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu.
Cangkatin lahun e maito hah a pahni moum pouh hanh.
5 Bí àwọn arákùnrin bá ń gbé pọ̀, tí ọ̀kan nínú wọn bá sì kú, tí kò sí ní ọmọkùnrin, kí aya òkú má ṣe ní àlejò ará òde ní ọkọ rẹ̀. Arákùnrin ọkọ rẹ̀ ni kí ó wọlé tọ̀ ọ́, kí ó fi ṣe aya, kí ó sì ṣe iṣẹ́ arákùnrin ọkọ fún un.
Reirei kaawm e hmaunawnghanaw thung dawkvah, buetbuet touh ni ca sak laipalah dout pawiteh, hote napui teh alouke tamikathan hoi kâyuva mahoeh. A vâ e nawngha ni a paluen vaiteh, a yu lah awm khai naseh.
6 Ọmọkùnrin tí ó bá kọ́ bí ni yóò máa jẹ́ orúkọ arákùnrin rẹ̀ tí ó kú náà, kí orúkọ rẹ̀ má ba á parẹ́ ní Israẹli.
Isarel miphun dawk hmau min a kahma hoeh nahanelah, camin teh, kadout e na pa kacue e min a phu han.
7 Ṣùgbọ́n bí ọkùnrin náà kò bá fẹ́ fi aya arákùnrin rẹ̀ ṣe aya rẹ̀, obìnrin náà yóò lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn àgbàgbà ní ẹnu-bodè ìlú láti sọ pé, “Arákùnrin ọkọ ọ̀ mi kọ̀ láti gbé orúkọ arákùnrin rẹ̀ ró ní Israẹli. Kò ní ṣe ojúṣe rẹ̀ bí arákùnrin ọkọ mi sí mi.”
A nawngha ni a hmau e yu hah la hane ngai hoehpawiteh, napui ni kacuenaw onae koe, kho longkha koe a cei vaiteh, ka vâ e nawngha ni, a hmau e min hah Isarel miphun thung caksak hanelah ngai hoeh. A sak hane kawi hai sak hane ngai hoeh telah dei pawiteh,
8 Nígbà náà ni àwọn àgbàgbà ìlú rẹ̀ yóò pè é, wọn yóò sì bá sọ̀rọ̀. Bí ó bá sì kọ̀ jálẹ̀ tí ó bá sọ pé, “Èmi kò fẹ́ láti fẹ́ ẹ,”
khothung vah kacuenaw ni ahni hah a kaw awh vaiteh, a pacei awh han. Ahni ni hai hote napui hah ka lat ngai hoeh telah muentakuen lah awm pawiteh,
9 opó arákùnrin rẹ̀ yìí yóò lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ ní ojú àwọn àgbàgbà ìlú rẹ̀, yóò yọ bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀ kan, yóò sì tu itọ́ sí ọkùnrin náà lójú, yóò sì wí pé, “Èyí ni ohun tí a ṣe sí ọkùnrin tí kò jẹ́ kí ìdílé arákùnrin rẹ̀ wà títí ayé.”
a hmau e yu ni kacuenaw e hmalah, ahni koe rek a cei vaiteh, ahnie khokkhawm hah a rading pouh vaiteh, a minhmai dawk a tamthawi pouh vaiteh, hmau e im kangdue sak hanlah ka ngai e tami koe hettelah ti hanelah ao telah a dei pouh awh han.
10 A ó sì mọ ìdílé arákùnrin yìí ní Israẹli gẹ́gẹ́ bí “Ìdílé tí a yọ bàtà rẹ̀.”
A hnukkhu vah, ahni hah khokkhawm rading e miphun telah kaw lah ao han.
11 Bí ọkùnrin méjì bá ń jà, tí ìyàwó ọ̀kan nínú wọn bá sì wá láti gbèjà ọkọ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ọkùnrin tí ń lù ú, tí ó sì nawọ́ di nǹkan ọkùnrin abẹ́ ẹ rẹ̀ mú.
Tami reira a kâyue awh navah, buet touh e a yu ni amae vâ kabawp han a ngai dawkvah, alouke tongpa e minro hah sawn pouh boipawiteh,
12 Ìwọ yóò gé ọwọ́ rẹ̀ náà kúrò. Má ṣe ṣàánú fún un.
hote napui e kut hah tâtueng pouh han. Na pahren mahoeh.
13 Má ṣe ní oríṣìí ìtẹ̀wọ̀n méjì tó yàtọ̀ sí ara wọn nínú àpò rẹ, ọ̀kan wúwo àti ọ̀kan fífúyẹ́.
Na yawngya dawk kalen e khinglung, kathounge khinglung tie kâvan hoeh e khinglung na awm sak mahoeh.
14 Má ṣe ní oríṣìí ìwọ̀n méjì tí ó yàtọ̀ sí ara wọn ní ilé è rẹ: ọ̀kan fífẹ̀, ọ̀kan kékeré.
Nama im vah khingnae kalen kathoung na awm sak mahoeh.
15 O gbọdọ̀ ní ìtẹ̀wọ̀n àti òsùwọ̀n pípé àti ti òtítọ́ nítorí náà kí ìwọ kí ó lè pẹ́ ní ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ fún ọ.
Na BAWIPA Cathut ni na poe e ram dawk na hringyung a vang nahanelah, kahman e khinglung, kahman e yawcu dueng hah na hno han.
16 Nítorí Olúwa Ọlọ́run kórìíra ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe nǹkan wọ̀nyí, àní ẹnikẹ́ni tí ń ṣe àìṣòdodo.
Dei tangcoung e hno ka sak e tami pueng hoi kamsoum hoeh lah ka sak tami pueng teh, nange BAWIPA Cathut ni a panuet.
17 Rántí ohun tí àwọn ará Amaleki ṣe sí i yín ní ọ̀nà nígbà tí ẹ̀ ń jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá.
Nang teh Izip ram hoi na tâco teh kahlawng na cei toteh,
18 Nígbà tí àárẹ̀ mú un yín tí agara sì dá a yín, wọ́n pàdé e yín ní ọ̀nà àjò o yín, wọ́n gé àwọn tí ó rẹ̀yìn kúrò, wọn kò ní ìbẹ̀rù Ọlọ́run.
na tha a baw teh na tawn lahun nah, na hnukkâbangnaw, a thakayounnaw hah Amaleknaw ni lamthung dawkvah a thei awh e hai thoseh, Cathut hah a taki awh hoeh e hai thoseh, pouk la a.
19 Nígbà tí Olúwa Ọlọ́run yín bá fún un yín ní ìsinmi lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá yín tí ó yí i yín ká ní ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run ń fi fún yín láti ni ní ìní, ẹ̀yin yóò sì pa ìrántí Amaleki rẹ́ kúrò lábẹ́ ọ̀run. Má ṣe gbàgbé.
Hatdawkvah, BAWIPA Cathut ni râw lah na poe e ram dawk, na tengpam kaawm e taran pueng e kut dawk hoi na hlout sak teh yawhawi na poe toteh, Amaleknaw heh pouknae ao hoeh nahanelah, kalvan rahim vah na raphoe awh han. Hot hah na pahnim mahoeh.

< Deuteronomy 25 >