< Deuteronomy 23 >

1 Kí ẹnikẹ́ni tí a fọ́ ní kóró ẹpọ̀n nípa rírùn tàbí gígé má ṣe wọ inú ìjọ Olúwa wá.
Gũtirĩ mũndũ mũhakũre na ũndũ wa kũhihinywo kana gũtinio kĩĩga gĩake gĩa ũciari ũgaatoonya kĩũngano-inĩ kĩa Jehova.
2 Kí ọmọ àlè má ṣe wọ ìpéjọ Olúwa, pàápàá títí dé ìran kẹwàá.
Gũtirĩ mwana ũciarĩtwo kuuma ũhiki-inĩ mũgirie, kana mũndũ o wothe wa rũciaro rwake ũgaatoonya kĩũngano-inĩ kĩa Jehova, o nginya rũciaro rwa ikũmi.
3 Kí ọmọ Ammoni tàbí ọmọ Moabu, kì yóò wọ ìjọ Olúwa, àní títí dé ìran kẹwàá, ènìyàn wọn kan kì yóò wọ inú ìjọ ènìyàn Olúwa láéláé.
Gũtirĩ Mũamoni kana Mũmoabi, kana mũndũ o wothe wa rũciaro rwake, ũgaatoonya kĩũngano-inĩ kĩa Jehova, o nginya rũciaro rwa ikũmi.
4 Nítorí wọn kò fi àkàrà àti omi pàdé e yín lójú ọ̀nà nígbà tí ò ń bọ̀ láti Ejibiti àti nítorí wọ́n gba ẹ̀yà iṣẹ́ láti fi ọ́ gégùn ún Balaamu ọmọ Beori ará a Petori ti Aramu-Naharaimu.
Nĩgũkorwo matiigana gũũka kũmũtũnga na mĩgate na maaĩ mũrĩ njĩra mũkiuma bũrũri wa Misiri, na ningĩ nĩmarĩhire Balamu mũrũ wa Beori kuuma Pethori kũu Mesopotamia nĩguo oke amũrume.
5 Síbẹ̀síbẹ̀, Olúwa Ọlọ́run rẹ kò ní fetí sí Balaamu ṣùgbọ́n ó yí ègún sí ìbùkún fún ọ, nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ fẹ́ràn rẹ.
O na kũrĩ o ro ũguo-rĩ, Jehova Ngai wanyu ndaigana gũthikĩrĩria Balamu, no aagarũrire kĩrumi kĩu gĩgĩtuĩka kĩrathimo harĩ inyuĩ, nĩ ũndũ Jehova Ngai wanyu nĩamwendete.
6 Ìwọ kò gbọdọ̀ wá àlàáfíà, tàbí ire wọn níwọ̀n ìgbà tí o sì wà láààyè.
Mũtikanagĩe kĩrĩko gĩa gũtũũra ũrata nao hĩndĩ ĩrĩa yothe mũgũtũũra muoyo.
7 Ìwọ kò gbọdọ̀ kórìíra ará Edomu kan nítorí arákùnrin rẹ ni. Ìwọ kò gbọdọ̀ kórìíra ará Ejibiti, nítorí o gbé gẹ́gẹ́ bí àjèjì ní ilẹ̀ rẹ̀.
Mũtikanamene Mũedomu nĩgũkorwo nĩ mũrũ wa ithe wanyu. Mũtikanamene Mũmisiri, nĩ ũndũ nĩmwatũire mũrĩ ageni bũrũri wake.
8 Ìran kẹta àwọn ọmọ tí a bí fún wọn lè wọ ìpéjọ Olúwa.
Andũ a rũciaro rwa gatatũ arĩa magaaciarwo nĩo, no matoonye kĩũngano-inĩ kĩa Jehova.
9 Nígbà tí o bá dó ti àwọn ọ̀tá rẹ, pa gbogbo ohun àìmọ́ kúrò.
Hĩndĩ ĩrĩa mũngĩamba kambĩ mũngʼethanĩire na thũ cianyu, mũtikahutanie na kĩndũ kĩrĩ thaahu.
10 Bí ọ̀kan nínú àwọn ọkùnrin rẹ bá jẹ́ aláìmọ́ nítorí ìtújáde tí ó ní, o ní láti jáde kúrò nínú àgọ́, kí o má ṣe wọ inú àgọ́.
Mũndũ mũrũme ũmwe thĩinĩ wanyu angĩkorwo nĩathaahĩte nĩ ũndũ wa ũndũ ũrĩa ũmũkorete ũtukũ, nĩakoima na kũu nja ya kambĩ aikare kuo.
11 Ṣùgbọ́n nígbà tí ó bá di ìrọ̀lẹ́ o ní láti wẹ ara rẹ, àti ní àṣálẹ́ kí o padà sínú àgọ́.
No rĩrĩ, gwatua gũtuka nĩethambe, na riũa rĩgĩthũa no acooke kambĩ-inĩ.
12 Sàmì sí ibìkan lóde àgọ́, níbi tí o lè máa lọ láti dẹ ara rẹ lára.
Thondekai handũ nja ya kambĩ harĩa mũrĩthiiaga gwĩteithia.
13 Kí ìwọ kí ó sì mú ìwalẹ̀ kan pẹ̀lú ohun ìjà rẹ; yóò sì ṣe, nígbà tí ìwọ yóò bá gbọnṣẹ̀ lẹ́yìn ibùdó, kí ìwọ kí ó mú ìwalẹ̀, kí ìwọ kí ó sì yípadà, kí o sì bo ohun tí ó jáde láara rẹ.
Harĩ indo cianyu cia wĩra-rĩ, gĩagai na kĩndũ gĩa gũcimbaga nakĩo, na rĩrĩa mũndũ athiĩ gwĩteithia, akenja irima agathika kĩoro gĩake.
14 Nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ ń rìn láàrín àgọ́ láti dáàbò bò ọ́ àti láti fi àwọn ọ̀tá à rẹ lé ọ lọ́wọ́. Àgọ́ rẹ ní láti jẹ́ mímọ́, nítorí kí ó má ba à rí ohun àìtọ́ láàrín yín kí ó sì yípadà kúrò lọ́dọ̀ yín.
Nĩgũkorwo Jehova Ngai wanyu nĩaceraceeraga kũu kambĩ-inĩ yanyu nĩguo amũgitĩre na aneane thũ cianyu kũrĩ inyuĩ. Kambĩ yanyu no nginya ĩtuĩke theru, nĩgeetha ndakanoone ũndũ ũtagĩrĩire gatagatĩ-inĩ kanyu, nake amweherere.
15 Bí ẹrú kan bá ti gba ààbò lọ́dọ̀ rẹ, má ṣe fi lé ọ̀gá rẹ̀ lọ́wọ́.
Ngombo ĩngĩgakorwo yũrĩire gwaku, ndũkanamĩneane kũrĩ mwathi wayo.
16 Jẹ́ kí ó máa gbé láàrín rẹ níbikíbi tí ó bá fẹ́ àti èyíkéyìí ìlú tí ó bá mú. Má ṣe ni í lára.
Reke ĩtũũre gatagatĩ kanyu kũrĩa guothe ĩngĩenda na itũũra-inĩ o rĩothe rĩrĩa ĩngĩthuura. Ndũkanamĩhinyĩrĩrie.
17 Kí ọkùnrin tàbí obìnrin Israẹli má ṣe padà di alágbèrè ojúbọ òrìṣà.
Gũtirĩ Mũisiraeli, mũndũ mũrũme kana mũndũ-wa-nja, ũgaatuĩka mũmaraya wa ihooero.
18 Ìwọ kò gbọdọ̀ mú owó iṣẹ́ panṣágà obìnrin tàbí ọkùnrin wá sí ilé Olúwa Ọlọ́run rẹ láti fi san ẹ̀jẹ́ kankan; nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ kórìíra àwọn méjèèjì.
Mũtikanarehe thĩinĩ wa nyũmba ya Jehova Ngai wanyu mbeeca ithũkũmĩtwo na njĩra ya ũmaraya wa andũ-a-nja kana wa arũme irĩ cia kũhingia mwĩhĩtwa o na ũrĩkũ, nĩ ũndũ Jehova Ngai wanyu nĩathũire maũndũ macio meerĩ.
19 Ìwọ kò gbọdọ̀ ka èlé sí arákùnrin rẹ lọ́rùn, bóyá lórí owó tàbí oúnjẹ tàbí ohunkóhun mìíràn tí ó lè mú èlé wá.
Ndũkanarĩhie mũrũ wa ithe wanyu uumithio wa kĩndũ ũmũheete, ũrĩ wa mbeeca kana irio kana wa kĩndũ kĩngĩ o gĩothe kĩngĩrehe uumithio.
20 Ìwọ lè ka èlé sí àlejò lọ́rùn, ṣùgbọ́n kì í ṣe arákùnrin ọmọ Israẹli, nítorí kí Olúwa Ọlọ́run rẹ lè bùkún ọ nínú ohun gbogbo tí o bá dáwọ́lé ní ilẹ̀ tí ò ń wọ̀ lọ láti ní.
No ũrĩhie mũndũ wa kũngĩ uumithio wa kĩndũ ũmuohoreire, no ti mũrũ wa ithe wanyu Mũisiraeli, nĩgeetha Jehova Ngai wanyu amũrathimage maũndũ-inĩ mothe marĩa mũrĩĩkaga bũrũri-inĩ ũrĩa mũrathiĩ mũwĩgwatĩre.
21 Bí o bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, má ṣe lọ́ra láti san án, nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò béèrè rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ, o sì máa jẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀.
Ũngĩkeehĩta mwĩhĩtwa kũrĩ Jehova Ngai waku, ndũgekĩre mũhũthia kũhingia mwĩhĩtwa ũcio, nĩgũkorwo Jehova Ngai waku ndarĩ hĩndĩ atagakũũria ũndũ ũcio, na nĩũgatuuo nĩwĩhĩtie.
22 Ṣùgbọ́n tí o bá fàsẹ́yìn láti jẹ́ ẹ̀jẹ́, o kò ní jẹ̀bi.
No ũngĩaga kwĩhĩta mwĩhĩtwa, ndũgaakorwo wĩhĩtie.
23 Rí i dájú pé o ṣe ohunkóhun tí o bá ti ètè rẹ jáde, nítorí pé ìwọ fi tinútinú rẹ jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀lú ẹnu ara rẹ.
Ũndũ ũrĩa wothe mĩromo yaku ĩriugaga no nginya ũũhingagie, nĩ ũndũ wehĩtire mwĩhĩtwa kũrĩ Jehova Ngai waku na kanua gaku wĩyendeire.
24 Bí ìwọ bá wọ inú ọgbà àjàrà aládùúgbò rẹ, o lè jẹ gbogbo èso àjàrà tí o bá fẹ́, ṣùgbọ́n má ṣe fi nǹkan kan sínú agbọ̀n rẹ.
Ũngĩtoonya mũgũnda wa mĩthabibũ wa mũndũ ũngĩ, no ũrĩe thabibũ nginya ũhũũne, no ndũgekĩre o na ĩmwe kĩondo-inĩ gĩaku.
25 Bí ìwọ bá wọ inú oko ọkà aládùúgbò rẹ, o lè fi ọwọ́ rẹ ya síírí rẹ̀, ṣùgbọ́n o kò gbọdọ̀ ki dòjé bọ ọkà tí ó dúró.
Ũngĩtoonya mũgũnda wa ngano wa mũndũ ũngĩ, no ũbute magira mayo na moko, no ndũkanagethe ngano ĩyo yake.

< Deuteronomy 23 >