< Deuteronomy 22 >

1 Bí o bá rí màlúù tàbí àgùntàn arákùnrin rẹ tí ó ń sọnù, má ṣe ṣé àìkíyèsí i rẹ̀ ṣùgbọ́n rí i dájú pé o mú padà wá fún un.
Ũngĩkoona ndegwa kana ngʼondu ya mũrũ wa ithe wanyu yũrĩte, ndũkamĩtiganĩrie, no tigĩrĩra wona nĩwamĩcookia kũrĩ we.
2 Bí ọkùnrin náà kì í bá gbé ní tòsí rẹ tàbí bí o kò bá mọ ẹni náà, mú un lọ ilé pẹ̀lú rẹ kí o sì fi pamọ́ títí yóò fi wá a wá. Nígbà náà ni kí o fi fún un.
Mũrũ wa ithe wanyu ũcio angĩkorwo ndaikaraga hakuhĩ nawe, kana ũngĩkorwo ndũmũĩ, ũkaamĩtwara gwaku mũciĩ nginya rĩrĩa agooka kũmĩcaria; hĩndĩ ĩyo ũmũcookerie.
3 Ṣe bákan náà tí o bá rí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ arákùnrin rẹ tàbí aṣọ ìlekè tàbí ohunkóhun rẹ̀ tí ó sọnù. Má ṣe ṣe àìkíyèsí i rẹ̀.
Ũgeeka o ũguo, ũngĩkoona ndigiri ya mũrũ wa thoguo, kana kabuti gake, kana o kĩndũ gĩothe atete, ndũkanetue ta ũtacionete.
4 Bí o bá rí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tàbí màlúù arákùnrin rẹ tí o dùbúlẹ̀ sójú ọ̀nà, má ṣe ṣàìfiyèsí i rẹ̀, ràn án lọ́wọ́ láti dìde dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ̀.
Ũngĩkoona ndigiri ya mũrũ wa thoguo, kana ndegwa yake ĩgũĩte njĩra-inĩ, ndũkanamĩtiganĩrie; mũteithĩrĩrie kũmĩrũgamia.
5 Obìnrin kò gbọdọ̀ wọ aṣọ ọkùnrin, tàbí kí ọkùnrin wọ aṣọ obìnrin, nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ kórìíra ẹnikẹ́ni tí ó ṣe èyí.
Mũndũ-wa-nja ndakanehumbe nguo cia arũme, kana mũndũ mũrũme ehumbe nguo cia andũ-a-nja, nĩgũkorwo Jehova Ngai wanyu nĩathũire mũndũ o wothe wĩkaga ũguo.
6 Bí ìwọ bá ṣe alábòápàdé ìtẹ́ ẹyẹ lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀nà, bóyá lára igi tàbí lórí ilẹ̀, tí ìyá wọn sì jókòó lórí àwọn ọmọ, tàbí lórí àwọn ẹyin, má ṣe gbé ìyá pẹ̀lú àwọn ọmọ.
Ũngĩgaakorerera gĩtara kĩa nyoni mũkĩra-inĩ wa njĩra, kĩrĩ mũtĩ igũrũ kana kĩrĩ thĩ, nayo nyoni ĩyo ĩkorwo ĩkomereirie tũcui twayo kana matumbĩ, ndũkanoe nyoni ĩyo na tũcui twayo.
7 Ìwọ lè gbé ọmọ, ṣùgbọ́n rí i dájú pé o jọ̀wọ́ ìyá lọ́wọ́ lọ, kí ó ba à lè dára fún ọ àti kí o lè ní ẹ̀mí gígùn.
No woe tũcui, no no nginya ũkaarekereria nyina yũmbũke, nĩgeetha wonage maũndũ mega na ũtũũre hĩndĩ ndaaya.
8 Nígbà tí o bá kọ́ ilé tuntun, mọ odi yí òrùlé rẹ̀ ká nítorí kí o má ba à mú ẹ̀bi ìtàjẹ̀ sílẹ̀ wá sórí ilẹ̀ rẹ bí ẹnikẹ́ni bá ṣubú láti òrùlé.
Hĩndĩ ĩrĩa ũngĩaka nyũmba njerũ, ũkaamĩĩkĩra rũirigo rũmĩthiũrũrũkĩirie igũrũ nĩgeetha ndũkarehithĩrie andũ a nyũmba yaku ũũru wa ũiti wa thakame, mũndũ angĩkaagũa kuuma nyũmba igũrũ.
9 Má ṣe gbin oríṣìí èso méjì sínú ọgbà àjàrà rẹ; bí o bá ṣe bẹ́ẹ̀, kì í ṣe èso oko tí o gbìn nìkan ṣùgbọ́n èso ọgbà àjàrà pẹ̀lú yóò bàjẹ́.
Ndũkahaande mbegũ cia mĩthemba ĩĩrĩ mũgũnda waku wa mĩthabibũ; ũngĩgeeka ũguo nĩũgathaahia mĩmera ĩrĩa ũhaandĩte, o na maciaro ma mũgũnda ũcio wa mĩthabibũ.
10 Ìwọ kò gbọdọ̀ fi akọ màlúù àti akọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tulẹ̀ pọ̀.
Ndũkanarĩmithie ndegwa na ndigiri ciohanĩtio mũraũ ũmwe.
11 Ìwọ kò gbọdọ̀ wọ aṣọ onírun àgùntàn àti aṣọ funfun papọ̀.
Ndũkanehumbe nguo cia guoya wa ngʼondu na cia gatani ciogothanĩtio hamwe.
12 Kí o ṣe wajawaja sí etí igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin aṣọ ìlekè rẹ.
Ohagĩrĩra ciohe cia ndigi mĩthia-inĩ ĩrĩa ĩna ya kabuti karĩa wĩhumbaga.
13 Bí ọkùnrin kan bá mú ìyàwó àti, lẹ́yìn ìgbà tí ó ti dùbúlẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀, kórìíra rẹ̀,
Mũndũ angĩhikia mũtumia na thuutha wa gũkoma nake acooke amũthũũre,
14 tí ó ṣì sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ sì i, tí o sì fún un ní orúkọ búburú, wí pé, “Mo fẹ́ obìnrin yìí, ṣùgbọ́n nígbà tí mo súnmọ́ ọn. Èmi kò rí àmì ìbálé rẹ̀.”
na aarie ndeto cia kũmũcambia, nake amũthũkĩrie rĩĩtwa, oige atĩrĩ, “Ndahikirie mũtumia ũyũ, no rĩrĩ, ndamũkuhĩrĩria ndionire imenyithia cia atĩ nĩ mũirĩtu gathirange,”
15 Nígbà náà ni baba ọmọbìnrin náà àti ìyá rẹ̀ yóò mú ẹ̀rí pé, ó ti wà ní ìbálé tẹ́lẹ̀ wá sí ọ̀dọ̀ àwọn àgbàgbà ìlú ní ẹnu-bodè.
hĩndĩ ĩyo ithe na nyina nĩmagatwara maũndũ ma kuonania atĩ nĩ mũirĩtu gathirange harĩ athuuri hau kĩhingo-inĩ gĩa itũũra.
16 Baba obìnrin náà yóò wí fún àwọn àgbàgbà pé, “Mo fi ọmọbìnrin mi fún ọkùnrin yìí láti fẹ́ níyàwó, ṣùgbọ́n ó kórìíra rẹ̀.
Ithe wa mũirĩtu nĩakeera athuuri atĩrĩ, “Ndaheanire mũirĩtu wakwa ahikio nĩ mũndũ ũyũ, no rĩrĩ, rĩu nĩamũthuurĩte.
17 Ní ìsinsin yìí ó ti sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ sí i ó sì wí pé, ‘Èmi kò rí ọmọbìnrin rẹ kí ó wà ní wúńdíá.’ Ṣùgbọ́n níhìn-ín yìí ni ẹ̀rí ìbálé ọmọbìnrin mi.” Nígbà náà ni àwọn òbí rẹ̀ yóò fi aṣọ hàn níwájú àwọn àgbàgbà ìlú,
Nĩamũcambĩtie akoiga atĩrĩ, ‘Ndiakorire mwarĩguo arĩ mũirĩtu gathirange.’ No rĩrĩ, ici nĩcio imenyithia cia kuonania atĩ mũirĩtu wakwa arĩ mũirĩtu gathirange.” Hĩndĩ ĩyo aciari a mũirĩtu ũcio nĩmagatambũrũkia gĩtambaya kĩu mbere ya athuuri a itũũra,
18 àwọn àgbàgbà yóò sì mú ọkùnrin náà, wọn yóò sì jẹ ní yà.
nao athuuri acio nĩmakanyiita mũndũ ũcio mamũherithie.
19 Wọn yóò sì gba ìtánràn ọgọ́rùn-ún ṣékélì owó fàdákà fún baba ọmọbìnrin náà, nítorí ọkùnrin yìí ti fi orúkọ búburú fún wúńdíá Israẹli. Yóò sì máa ṣe ìyàwó rẹ̀; kò gbọdọ̀ kọ̀ ọ́ sílẹ̀ ní gbogbo ayé e rẹ̀.
Nĩmakamwĩtia thĩnjo ya cekeri igana rĩmwe cia betha, macineane kũrĩ ithe wa mũirĩtu, nĩ ũndũ mũndũ ũcio nĩacambĩtie mũirĩtu gathirange wa Isiraeli. Mũirĩtu ũcio agaathiĩ na mbere gũtuĩka mũtumia wake; ndakanamũte matukũ mothe marĩa egũtũũra muoyo.
20 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀sùn náà bá jẹ́ òtítọ́ tí a kò sí rí ẹ̀rí ìbálé obìnrin náà,
No rĩrĩ, kũngĩgaatuĩka atĩ thitango ĩyo nĩ ya ma, na kwage kĩmenyithia gĩa kuonania atĩ mũirĩtu ũcio aarĩ gathirange,
21 wọn yóò mú wá sí ẹnu-ọ̀nà ilé baba rẹ̀ níbẹ̀ sì ni àwọn ọkùnrin ìlú rẹ̀ yóò ti sọ ọ́ ní òkúta pa. Ó ti ṣe ohun ìtìjú ní Israẹli nípa ṣíṣe àgbèrè nígbà tí ó wà nílé baba rẹ̀. Ẹ ní láti pa ohun búburú kúrò láàrín yín.
nĩakarehwo mũrango-inĩ wa nyũmba ya ithe, nao arũme a itũũra rĩake nĩmakamũhũũra na mahiga nyuguto nginya akue. Nĩekĩte ũndũ wa thoni thĩinĩ wa Isiraeli nĩkũhũũra ũmaraya arĩ o nyũmba gwa ithe. No nginya mũniine ũũru ũcio wehere gatagatĩ-inĩ kanyu.
22 Bí o bá rí ọkùnrin kan tí ó bá ìyàwó ọkùnrin mìíràn lòpọ̀, àwọn méjèèjì ní láti kú. Ẹ ní láti pa ohun búburú kúrò láàrín Israẹli.
Mũndũ mũrũme angĩnyiitwo akomete na mũtumia wa mũndũ ũngĩ, o eerĩ, mũndũ mũrũme ũcio na mũtumia ũcio, no nginya makue. No nginya mũniine ũũru ũcio wehere Isiraeli.
23 Bí ó bá ṣẹlẹ̀ wí pé ọkùnrin kan pàdé wúńdíá tí a ti fi fún ni láti fẹ́ láàrín ìlú tí ó sì lòpọ̀ pẹ̀lú u rẹ̀,
Mũndũ angĩcemania na mũirĩtu gathirange itũũra-inĩ orĩtio ahikio, na mũndũ ũcio akome nake,
24 ìwọ yóò mú àwọn méjèèjì lọ sí ẹnu ibodè ìlú náà kí o sì sọ wọ́n ní òkúta pa nítorí ọmọbìnrin náà wà ní ìlú kò sì kígbe fún ìrànlọ́wọ́, àti ọkùnrin náà nítorí ó ba ìyàwó ọkùnrin mìíràn jẹ́. O ní láti wẹ búburú kúrò láàrín rẹ.
nĩmũkamanyiita eerĩ, mũmoimagarie kĩhingo-inĩ gĩa itũũra rĩu, mũmahũũre na mahiga nyuguto nginya makue; mũirĩtu ũcio akooragwo tondũ aarĩ thĩinĩ wa itũũra na ndoigire mbu nĩguo ateithio, nake mũndũ mũrũme ũcio akooragwo tondũ wa gũthũkia mũtumia wa mũndũ ũngĩ. No nginya mũniine ũũru wehere gatagatĩ-inĩ kanyu.
25 Ṣùgbọ́n bí ó bá ṣe ìgbẹ́ ní ó ti ṣẹlẹ̀ pé ọkùnrin kan ti pàdé ọmọbìnrin tí a ti fẹ́ ṣọ́nà tí o sì fi tagbára tagbára bá a ṣe, ọkùnrin náà nìkan tí ó ṣe èyí ni yóò kú.
No rĩrĩ, mũndũ mũrũme angĩcemania na mũirĩtu ũrĩĩtio ahikio arĩ na kũu nja ya itũũra, na amũnyiite na hinya, mũndũ mũrũme ũcio wĩkĩte ũguo nowe wiki ũgaakua.
26 Má ṣe fi ohunkóhun ṣe ọmọbìnrin náà; kò ṣẹ ẹ̀ṣẹ̀ tí ó tọ́ sí ikú. Ẹjọ́ yìí rí bí i ti ẹnìkan tí a gbámú tí ó pa aládùúgbò rẹ̀.
No rĩrĩ, mũirĩtu ũcio mũtikanamwĩke ũndũ; ndeekĩte rĩhia rĩa gũtũma ooragwo. Ũndũ ũcio nĩ ta wa mũndũ ũrĩa ũtharĩkagĩra akooraga mũndũ wa itũũra rĩake,
27 Nítorí ọkùnrin náà rí ọmọbìnrin náà ní ìta ibodè, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọmọbìnrin àfẹ́sọ́nà kígbe, kò sí ẹnìkankan níbẹ̀ láti gbà á kalẹ̀.
nĩgũkorwo mũndũ ũcio aacemanirie na mũirĩtu ũcio na kũu nja ya itũũra, o na gũtuĩka mũirĩtu ũcio ũrĩĩtio nĩoigire mbu, hatiarĩ na mũndũ wakũmũteithũra.
28 Bí ó bá ṣẹlẹ̀ pé ọkùnrin pàdé wúńdíá tí kò ì tí ì ní àfẹ́sọ́nà tí ó sì fi tipátipá bá a ṣe tí a gbá wọn mú.
Mũndũ angĩgacemania na mũirĩtu gathirange ũtoorĩtio ahikio, amũnyiite na hinya nao mamenyeke-rĩ,
29 Ó ní láti san àádọ́ta fàdákà fún baba obìnrin náà, nítorí tí ó ti bà á jẹ́. Kò lè kọ̀ ọ́ sílẹ̀ níwọ̀n ìgbà tí ó sì wà láààyè.
mũndũ ũcio nĩakarĩha ithe wa mũirĩtu ũcio cekeri mĩrongo ĩtano cia betha. Mũndũ ũcio no nginya ahikie mũirĩtu ũcio, nĩgũkorwo nĩamũthũkĩtie. Ndakanamũte matukũ mothe marĩa egũtũũra muoyo.
30 Ọkùnrin kò gbọdọ̀ fẹ́ ìyàwó baba rẹ̀; kò gbọdọ̀ sọ ìtẹ́ baba rẹ̀ di àìlọ́wọ̀.
Mũndũ mũrũme ndagĩrĩirwo nĩkũhikia mũtumia wa ithe; ndakanaconorithie ũrĩrĩ wa ithe.

< Deuteronomy 22 >