< Deuteronomy 21 >

1 Tí a bá rí ọkùnrin tí a pa, ní ìdùbúlẹ̀ ní pápá nínú ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ ń fún ọ láti jogún, tí a kò sì mọ ẹni tí ó pa á,
Mũndũ angĩkooneka oragĩtwo, na akorwo akomete gĩthaka-inĩ kũu bũrũri ũcio Jehova Ngai wanyu ekũmũhe mũwĩgwatĩre, na kwage kũmenyeka mũndũ ũrĩa ũmũũragĩte-rĩ,
2 àwọn àgbàgbà yín yóò jáde lọ láti wọn jíjìnnà ibi òkú sí ìlú tí ó wà nítòsí.
athuuri anyu na aciirithania nĩmakoimagara magathime itĩĩna rĩa kuuma harĩa mwĩrĩ ũrĩ nginya matũũra-inĩ marĩa marĩ hakuhĩ naguo.
3 Nígbà náà ni àwọn àgbàgbà ìlú tí ó wà nítòsí òkú yóò mú ẹgbọrọ abo màlúù tí kò ì ṣiṣẹ́ rí àti tí kò sì fà nínú àjàgà rí,
Ningĩ athuuri a itũũra rĩrĩa rĩkuhĩrĩirie mũno na harĩa mwĩrĩ ũcio ũrĩ nĩmakanyiita moori ĩtarĩ yarutithio wĩra na ĩtarĩ yohwo icooki,
4 kí àwọn àgbàgbà ìlú náà kí wọn mú ẹgbọrọ abo màlúù náà sọ̀kalẹ̀ wá sí àfonífojì tí ó ní omi ṣíṣàn kan, tí a kò ro, tí a kò sì gbìn, kí wọn kí ó sì ṣẹ́ ọrùn ẹgbọrọ màlúù náà níbẹ̀ ní àfonífojì náà.
nao mamĩikũrũkie gĩtuamba-inĩ gĩtarĩ kĩarĩmwo kana gĩkahaandwo, na kĩrĩ na karũũĩ gegũtherera. Nĩmakoinĩra moori ĩyo ngingo kũu gĩtuamba-inĩ kĩu.
5 Àwọn àlùfáà, ọmọ Lefi yóò wá síwájú, nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti yàn wọ́n láti ṣe ìránṣẹ́ fún un àti láti bùkún ní orúkọ Olúwa àti láti parí gbogbo ẹjọ́ àríyànjiyàn àti ọ̀rọ̀ ìlú.
Nao athĩnjĩri-Ngai, o acio ariũ a Lawi, nĩmakeyumĩria nĩgũkorwo Jehova Ngai wanyu nĩamathuurĩte nĩguo matungatage na makarathimana makĩgwetaga rĩĩtwa rĩa Jehova na magatuithanagia maciira ma andũ arĩa marĩ na ngarari o na ma andũ maangĩrũa.
6 Nígbà náà ni gbogbo àwọn àgbàgbà ìlú tí ó wà nítòsí yóò wẹ ọwọ́ wọn lórí ẹgbọrọ abo màlúù tí a ti kan ọrùn rẹ̀ ní àfonífojì,
Ningĩ athuuri othe a itũũra rĩrĩa rĩkuhĩrĩirie mũno harĩa mwĩrĩ ũcio ũrĩ nĩmagethamba moko igũrũ rĩa moori ĩyo yunĩtwo ngingo o kũu gĩtuamba-inĩ,
7 wọn yóò sì sọ pé, “Ọwọ́ wa kò ta ẹ̀jẹ̀ yìí sílẹ̀, tàbí kí ojú wa rí i ní títa sílẹ̀.”
na moige atĩrĩ, “Moko maitũ timo maaitire thakame ĩno, o na kana maitho maitũ makĩona ũndũ ũcio ũgĩĩkwo.
8 Dáríjì, Olúwa, àwọn ènìyàn rẹ ni Israẹli, tí ìwọ ti dá sílẹ̀, àti kí ìwọ má ṣe gba ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ ní àárín àwọn ènìyàn rẹ ní Israẹli. Ṣùgbọ́n kí a dárí ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ yìí jì.
Ĩtĩkĩra horohio ĩno nĩ ũndũ wa andũ aku a Isiraeli, arĩa Wee Jehova ũkũũrĩte, na ũtige kũmatua ahĩtia ũndũ-inĩ wa thakame ĩno ya mũndũ ũtarĩ na ũũru.” Nayo thakame ĩyo ĩitĩtwo nĩĩkahoroherio.
9 Nígbà náà ni ìwọ wẹ̀ kúrò láàrín rẹ ẹ̀bi títa ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀, níwọ̀n ìgbà tí o ti ṣe èyí tí ó tọ́ níwájú Olúwa.
Nĩ ũndũ ũcio nĩmũgetheria ihĩtia-inĩ rĩu rĩa gũita thakame ya mũndũ ũtarĩ na ũũru, kuona atĩ nĩmwĩkĩte ũndũ ũrĩa wagĩrĩire maitho-inĩ ma Jehova.
10 Nígbà tí o bá lọ sí ogun sí àwọn ọ̀tá rẹ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ sì fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́ tí o sì mú àwọn ìgbèkùn,
Rĩrĩa mũngĩthiĩ kũrũa na thũ cianyu, nake Jehova Ngai wanyu acirekererie moko-inĩ manyu mũcitahe-rĩ,
11 tí o sì rí obìnrin tí ó dára lára àwọn ìgbèkùn, tí o sì ní ìfẹ́ sí i, o lè mu u gẹ́gẹ́ bí aya à rẹ.
mũngĩcooka muone thĩinĩ wa andũ acio atahe harĩ na mũndũ-wa-nja mũthaka na ũmwe wanyu aguucĩrĩrio nĩwe, no amũhikie atuĩke mũtumia wake.
12 Mú u wá sí ilé e rẹ kí o sì jẹ́ kí ó fá irun orí rẹ̀, gé èékánná an rẹ̀,
Nĩakamũinũkia gwake mũciĩ acooke atũme enjwo mũtwe na arenge ndwara
13 kí o sì mú aṣọ tí ó wọ̀ nígbà tí ó di ìgbèkùn sí ẹ̀gbẹ́ kan. Lẹ́yìn ìgbà tí ó ti ń gbé ilé rẹ tí ó sì ti ṣọ̀fọ̀ baba àti ìyá rẹ̀ fún odidi oṣù kan, nígbà náà ni o lè tọ̀ ọ́ lọ kí o sì ṣe ọkọ rẹ̀ kí ó jẹ́ aya rẹ.
na arute nguo iria eekĩrĩte rĩrĩa aatahagwo. Thuutha wa gũikara gwake mũciĩ na acakaĩre ithe na nyina ihinda rĩa mweri mũgima-rĩ, hĩndĩ ĩyo no athiĩ harĩ we, atuĩke mũthuuri wake nake atuĩke mũtumia wake.
14 Bí inú rẹ̀ kò bá sì dùn sí i, jẹ́ kí ó lọ sí ibikíbi tí ó bá fẹ́. O kò gbọdọ̀ tà á tàbí lò ó bí ẹrú, lẹ́yìn ìgbà tí o ti dójútì í.
Angĩkaaga gũkenio nĩwe, nĩakamwĩtĩkĩria athiĩ o kũrĩa guothe angĩenda. Ndakanamwendie kana amũtue ngombo, kuona atĩ nĩamwagithĩtie gĩtĩĩo.
15 Bí ọkùnrin kan bá ní ìyàwó méjì, tí ó sì fẹ́ ọ̀kan ṣùgbọ́n tí kò fẹ́ èkejì, tí àwọn méjèèjì sì bí àwọn ọmọkùnrin fún un ṣùgbọ́n tí àkọ́bí jẹ́ ọmọ ìyàwó rẹ̀ tí kò fẹ́ràn.
Mũndũ angĩkorwo na atumia eerĩ, na akorwo endete ũmwe na akaaga kwenda ũcio ũngĩ, na eerĩ mamũciarĩre ciana cia ihĩĩ, no mwana wa irigithathi akorwo nĩ wa mũtumia ũrĩa atendete-rĩ,
16 Nígbà tí ó bá ń pín ohun ìní rẹ̀ fún àwọn ọmọ rẹ̀, kò gbọdọ̀ fi ẹ̀tọ́ àkọ́bí fún ọmọ ìyàwó tí kò fẹ́ràn.
angĩkorwo akĩgaĩra ariũ ake indo, ndakanaheane kĩhooto kĩa irigithathi kũrĩ mũriũ wa mũtumia ũrĩa eendete, handũ ha kũhe mũriũ ũrĩa arĩ we irigithathi kũna, mũriũ ũcio wa mũtumia ũrĩa atendete.
17 Ó ní láti fi ipò ọmọ ìyàwó rẹ̀ tí kò fẹ́ràn fun un gẹ́gẹ́ bí àkọ́bí i rẹ̀ nípa fífún un ní ìlọ́po ìpín gbogbo ohun tí ó ní. Ọmọ yẹn ni àmì àkọ́kọ́ agbára baba rẹ̀. Ẹ̀tọ́ àkọ́bí jẹ́ tirẹ̀.
No nginya onanie atĩ mũriũ ũcio wa mũtumia ũcio atendete nĩwe irigithathi na ũndũ wa kũmũhe indo maita meerĩ thĩinĩ wa indo iria ciothe arĩ nacio. Mũriũ ũcio nĩwe kĩonereria kĩa mbere kĩa hinya wa ithe. Kĩhooto kĩa mwana wa irigithathi nĩ gĩake.
18 Bí ọkùnrin kan bá ní aláìgbọ́ràn tàbí ọlọ̀tẹ̀ ọmọ tí kò gbọ́rọ̀ sí baba àti ìyá rẹ̀ tí kò sì ní í gbà tí wọ́n bá ń bá a wí,
Mũndũ angĩkaagĩa na mũriũ ũtangĩigua na mũremi, ũtaathĩkagĩra ithe na nyina, na ũtangĩmaigua o na mamũhũũra-rĩ,
19 baba àti ìyá rẹ̀ yóò gbá a mú, wọn yóò mu wá fún àwọn àgbàgbà ní ẹnu-bodè ìlú u rẹ̀.
ithe na nyina nĩmakamũnyiita mamũtware kũrĩ athuuri hau kĩhingo-inĩ gĩa itũũra.
20 Wọn yóò sì wí fún àwọn àgbàgbà pé, “Ọmọ wa yìí jẹ́ aláìgbọ́ràn àti ọlọ̀tẹ̀. Kò ní gbọ́rọ̀ sí wa lẹ́nu. Ọ̀jẹun àti ọ̀mùtípara ni.”
Nao meere athuuri atĩrĩ, “Mũriũ ũyũ witũ ndatũiguaga na nĩ mũremi, ndangĩtwathĩkĩra. Atũũraga arĩ mũmaramari na arĩ mũrĩĩu.”
21 Nígbà náà ni gbogbo ọkùnrin ìlú rẹ̀ yóò sọ ọ́ ní òkúta pa. Ìwọ yóò sì mú ìwà ibi kúrò láàrín yín, gbogbo Israẹli yóò gbọ́, ẹ̀rù yóò sì bà wọ́n.
Hĩndĩ ĩyo andũ othe a itũũra nao nĩmakamũhũũra na mahiga nyuguto nginya akue. No nginya mũniine ũũru ũcio wehere gatagatĩ-inĩ kanyu. Ũhoro ũcio nĩũkaiguuo nĩ andũ a Isiraeli othe nao meetigĩre.
22 Bí ọkùnrin kan tí ó jẹ̀bi ẹ̀sùn bá ní láti kú tí ó sì kú, tí a sì gbé òkú rẹ̀ kọ́ sára igi,
Mũndũ angĩĩhia wĩhia ũngĩtũma ooragwo, nake ooragwo na mwĩrĩ wake ũcuurio mũtĩ igũrũ-rĩ,
23 o kò gbọdọ̀ fi òkú rẹ̀ sílẹ̀ sára igi ní gbogbo òru. Gbìyànjú láti sin ín ní ọjọ́ náà gan an, nítorí ẹni tí a bá gbé kọ́ sórí igi wà lábẹ́ ègún Ọlọ́run. Ìwọ kò gbọdọ̀ ba ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ fún ọ gẹ́gẹ́ bí ogún jẹ́.
mũtikanareke mwĩrĩ ũcio ũraare mũtĩ igũrũ ũtukũ ũcio wothe. Tigĩrĩrai nĩ mwamũthika mũthenya o ro ũcio, tondũ mũndũ o na ũrĩkũ mũcuurie mũtĩ-inĩ nĩ mũrume nĩ Ngai. Mũtikanathaahie bũrũri ũrĩa Jehova Ngai wanyu ekũmũhe ũtuĩke igai rĩanyu.

< Deuteronomy 21 >