< Deuteronomy 2 >
1 Nígbà náà ni a yípadà, tí a sì mú ọ̀nà wa pọ̀n lọ sí aginjù, a gba ọ̀nà Òkun Pupa, bí Olúwa ti darí mi. Ìgbà pípẹ́ ni a fi ń rìn kiri yíká agbègbè àwọn ìlú olókè Seiri.
Cathut ni kai koe bout a dei e patetlah kaimouh ni kamlang awh vaiteh, Tuipui paling kahrawng lahoi ka cei teh Seir mon hah moi ka saw lah ka lawngven awh.
2 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún mi pé,
Cathut nihai, nangmouh ni atueng akuep nahan hete mon hah na lawngven awh toe.
3 “Ẹ ti rìn yí agbègbè ilẹ̀ olókè yìí pẹ́ tó, nísinsin yìí, ẹ yípadà sí ìhà àríwá.
Atunglah bout cet awh ei.
4 Fún àwọn ènìyàn náà ní àwọn òfin wọ̀nyí: ‘Ẹ ti fẹ́ la ilẹ̀ àwọn arákùnrin yín kọjá, àwọn ọmọ Esau; àwọn ará Edomu tí ń gbé ní Seiri. Ẹ̀rù yín yóò bà wọ́n, ṣùgbọ́n ẹ ṣọ́ra gidigidi.
Nang ni tami pueng koe na dei pouh hane teh, na hmau Esaw miphunnaw a onae Seir ram teng vah, nangmouh na cei awh toteh ahnimouh ni a taki awh han. Hatdawkvah kâhruetcuet awh.
5 Ẹ má ṣe wá wọn níjà torí pé èmi kò ní fún un yín ní èyíkéyìí nínú ilẹ̀ wọn. Bí ó ti wù kí ó kéré mọ èmi kò ní fún un yín. Mo ti fi ilẹ̀ òkè Seiri fún Esau gẹ́gẹ́ bí ìní rẹ̀.
Rek saueng hanh awh. Ahnimae ram hah, kai ni nangmouh na poe hoeh. Na coungroenae khok hmuen tittouh hai na poe hoeh. Seir mon hateh Esaw yo ka poe toe.
6 Ẹ san owó oúnjẹ tí ẹ bá jẹ fún wọn àti omi tí ẹ bá mu.’”
Nangmouh ni na canei nahane bu hoi tui hai thoseh, ahnimouh koe tangka hoi na ran awh han.
7 Olúwa Ọlọ́run yín ti bùkún un yín nínú gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín. Ó ti mójútó ìrìnàjò yín nínú aginjù ńlá yìí. Olúwa Ọlọ́run yín wà pẹ̀lú u yín ní ogójì ọdún wọ̀nyí, dé bi pé ẹ̀yin kò ṣaláìní ohunkóhun.
Nangmouh ni na tawksaknae pueng dawk, nangmae Cathut ni yawhawinae a poe toe. Hete kahrawngpui dawk nangmouh na lawngven awh e a kongnaw a panue. A kum 40 touh thung nangmae BAWIPA Cathut ni nangmouh hoi cungtalah ao nah, banghai nangmouh dawk panki hoeh telah ati.
8 Bẹ́ẹ̀ ni a kọjá ọ̀dọ̀ àwọn arákùnrin wa, àwọn ọmọ Esau tí ń gbé ní Seiri. A yà kúrò ní ọ̀nà Arabah èyí tí ó wá láti Elati àti Esioni-Geberi, a sì rìn gba ọ̀nà aginjù Moabu.
Seir ram kaawm e maimae hmau Esaw miphun koe cei awh teh, Elath khopui Eziongeber khopui hoi ka cet e lam tâphai koe ka dawn awh teh, haw hoi bout kamlang awh teh Moab kahrawng lam lahoi ka cei awh.
9 Olúwa sì sọ fún mi pé, “Ẹ má ṣe dẹ́rùba àwọn ará Moabu bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má ṣe bá wọn jagun torí pé n kò ní fi èyíkéyìí nínú ilẹ̀ wọn fún un yín. Mo ti fi Ari fún àwọn ọmọ Lọti bí i ìní.”
BAWIPA Cathut nihai, Moab khocanaw rucat poe awh hanh, tuk awh hanh, ahnimae ram kai ni na poe awh hoeh. Arab ram teh Lot miphunnaw kai ni yo ka poe toe telah ti pouh.
10 (Àwọn Emimu ti gbé ibẹ̀ rí, àwọn ènìyàn tó síngbọnlẹ̀ tó sì pọ̀, wọ́n ga bí àwọn Anaki.
Ayan vah Anakim miphun patetlah ka rasang kalen e Em miphunnaw teh hote ram dawk ao awh.
11 Gẹ́gẹ́ bí Anaki àwọn ènìyàn náà pè wọ́n ní ará Refaimu ṣùgbọ́n àwọn ará Moabu pè wọ́n ní Emimu.
Ahnimouh teh, Anakim miphunnaw patetlah ao e lah a pouk awh. Hatnavah Moab ram khocanaw ni ahnimanaw teh EM telah a kaw awh.
12 Àwọn ará Hori gbé ní Seiri, kí àwọn ọmọ Esau tó lé wọn kúrò níwájú wọn. Wọ́n sì gba ilẹ̀ wọn, wọ́n tẹ̀dó sí ààyè wọn gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ Israẹli tí ṣe ní ilẹ̀ tí Olúwa yóò fún wọn ní ìní wọn.)
Ayan vah Hor taminaw teh Seir ram vah ao awh. Ahnimouh hah Esaw miphunnaw ni a thei awh teh, ahnimouh onae hmuen dawk ao awh. Hot patetlah Cathut ni a poe e ram hah Isarel miphunnaw ni ati awh.
13 Olúwa sì wí pé, “Ẹ dìde, kí ẹ sì la àfonífojì Seredi kọjá.” Bẹ́ẹ̀ ni a la àfonífojì náà kọjá.
Atu cet awh nateh Zered tui rakat awh haw telah a dei e patetlah Ahnimouh ni Zered tui a raka awh.
14 Ó gbà wá ní ọdún méjìdínlógójì kí ó tó di wí pé a la àfonífojì Seredi kọjá láti ìgbà tí a ti kúrò ní Kadeṣi-Barnea. Nígbà náà gbogbo ìran àwọn tí ó jẹ́ jagunjagun láàrín àwọn ènìyàn náà ti ṣègbé kúrò láàrín àwọn ènìyàn náà ní àsìkò yìí bí Olúwa ti búra fún wọn.
Kadeshbarnea hmuen koe ahmaloe phanae tueng koehoi ka tâco awh teh Zered tui rakanae tueng totouh kum 38 touh a ro. Cathut ni lawk a kam e patetlah ahmaloe e taran ka tuk thai e ransanaw pueng teh taminaw thungup hoi a due awh.
15 Ọwọ́ Olúwa sì wà lòdì sí wọn nítòótọ́, láti run wọn kúrò nínú ibùdó, títí gbogbo wọn fi run tan.
Ahnimouh raphoe hoeh roukrak, Cathut ni ahnimouh koehoi pâmit hanelah a kut a dâw.
16 Lẹ́yìn tí ẹni tí ó gbẹ̀yìn pátápátá nínú àwọn jagunjagun àwọn ènìyàn wọ̀nyí ti kú,
Taran ka tuk thai e pueng tamihu thung e koung a pâmit sak hnukkhu,
Cathut ni nang teh Moab ram,
18 “Lónìí ni ẹ̀yin yóò la agbègbè Moabu kọjá ní Ari.
Ar ram a lungui vah sahnin na cei han.
19 Bí ẹ bá dé ọ̀dọ̀ àwọn ará Ammoni, ẹ má ṣe halẹ̀ mọ́ wọn, ẹ kò sì gbọdọ̀ bá wọn jagun, torí pé èmi kì yóò fi àwọn ilẹ̀ tí ó jẹ́ ti àwọn ará Ammoni fún un yín ní ìní. Mo ti fi fún àwọn ọmọ Lọti ní ìní.”
Ammon miphunnaw teng na pha torei teh ahnimouh rucatnae poe awh hanh, reksaueng awh hanh. Ammon miphunnaw a onae ram hah kai ni nangmouh koe na poe hoeh. Hote ram teh Lot miphunnaw kai ni ka poe toe telah kai koe a dei.
20 (A ka ilẹ̀ yìí sí ilẹ̀ àwọn Refaimu, tí wọ́n ti gbé níbẹ̀ rí, ṣùgbọ́n àwọn ará Ammoni ń pè wọ́n ní ará Samsummimu.
Hote ram hai kalenpounge taminaw e hmuen doeh telah taminaw ni a pouk awh. Ayan e tueng dawk, hot patetlae taminaw ni ao awh. Ahnimouh hah Ammon ram khocanaw ni Zamzummim telah a kaw awh.
21 Wọ́n jẹ́ àwọn ènìyàn tó lágbára, wọ́n sì pọ̀, wọ́n sì ga gogoro bí àwọn ará Anaki. Olúwa run wọn kúrò níwájú àwọn ará Ammoni, tí wọ́n lé wọn jáde tí wọ́n sì gba ilẹ̀ wọn.
Hote miphun teh Anakim miphunnaw patetlah kalenpoung kapap poung e taminaw doeh.
22 Bákan náà ni Olúwa ṣe fún àwọn ọmọ Esau, tí wọ́n ń gbé ní Seiri, nígbà tí ó pa àwọn ará Hori run níwájú wọn. Wọ́n lé wọn jáde wọ́n sì ń gbé ní ilẹ̀ wọn títí di òní.
Hatei Seir ram dawk kaawm e Esaw miphun e hmalah Hor taminaw hah Cathut ni a raphoe dawkvah, ahnimae hmuen dawk Esaw miphunnaw ni sahnin totouh ao e patetlah koung a pâmit teh ahnimae hmuen dawk Arnonnaw ni ao awh.
23 Nípa ti àwọn ará Affimu, tí wọ́n ń gbé ní àwọn ìlú kéékèèké dé Gasa, àwọn ará Kaftorimu, tí wọ́n jáde láti Krete wá ni ó pa wọ́n run, wọ́n sì gba ilẹ̀ wọn.)
Hot patetlah Hazrim khopui koehoi Gaza khopui totouh ouk kaawm e naw Avvimnaw hai Kaptor khopui ka tâcawt e Kaptor taminaw ni a raphoe awh teh, ahnimanaw a onae hmuen dawk ao awh.
24 “Ẹ gbáradì, kí ẹ sì kọjá odò Arnoni. Kíyèsi, Mo ti fi Sihoni ará Amori, ọba Heṣboni àti ilẹ̀ rẹ̀ lé ọ lọ́wọ́. Ẹ bá ilẹ̀ náà jagun kí ẹ sì gbà á.
Nangmouh na thaw awh vaiteh cet awh haw, Arnon tuipui raka awh haw. Amor miphun, Heshbon siangpahrang Sihon hoi a talai hah nangmae kut dawk ka poe toung dawkvah, khosak awh nateh hote bawi hah tuk awh.
25 Èmi bẹ̀rẹ̀ sí ní fi ìbẹ̀rù àti ìfòyà yín sára gbogbo orílẹ̀-èdè lábẹ́ ọ̀run láti òní lọ. Wọn yóò gbọ́ ìròyìn in yín, wọn yóò sì wárìrì, wọn yóò sì wà nínú ìdààmú ọkàn torí i tiyín.”
Tâmai rahim kaawm e pueng, miphunnaw ni sahnin nangmouh tâsue taki laihoi ao nahan ka sak han. Nangmae kamthang a thai awh vaiteh, puennae, pâyawnae, runae puenghoi a kâhmo awh han telah ati.
26 Mo rán àwọn ìránṣẹ́ láti aginjù Kedemoti lọ́ sọ́dọ̀ Sihoni ọba Heṣboni pẹ̀lú ọ̀rọ̀ àlàáfíà wí pé,
Kai hai Kedemoth kahrawng hoi Heshbon siangpahrang Sihon koevah patounenaw ka patoun vaiteh,
27 “Jẹ́ kí a la ilẹ̀ ẹ yín kọjá. Àwa yóò gba ti òpópónà nìkan. A kò ní yà sọ́tùn tàbí sósì.
Aram lungui vah na cetsak haw, na lam dawk dueng ka dawn han. Avoilah aranglah ka phen mahoeh.
28 Ẹ ta oúnjẹ tí a ó jẹ àti omi tí a ó mu fún wa ní iye owó wọn. Kìkì kí ẹ sá à jẹ́ kí a rìn kọjá:
Seir ram kaawm e Esaw miphun, Ar ram dawk kaawm e Moab miphunnaw ni kai dawk a sak awh e patetlah ka ca hane rawca thoseh, nei hane tui hai thoseh, tangka hoi yawt lawih.
29 gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ Esau tí ó ń gbé ní Seiri àti àwọn ará Moabu tí ó ń gbé ní Ari, ti gbà wá láààyè títí a fi la Jordani já dé ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run wa yóò fún wa.”
Kai teh Cathut ni na poe e ram lah Jordan palang ka raka vaiteh ka pha hoehroukrak Seir ram lungui dawk khok hoi ka cet haw nei telah kâhuikonae lawk hoi ka dei nakunghai,
30 Ṣùgbọ́n Sihoni ọba Heṣboni kò gbà fún wa láti kọjá. Torí pé Olúwa Ọlọ́run yín ti mú ọkàn rẹ̀ yigbì, àyà rẹ̀ sì kún fún agídí kí ó ba à le fi lé e yín lọ́wọ́, bí ó ti ṣe báyìí.
Kaimouh ka cei nahane Heshbon siangpahrang Sihon ni kâ na poe hoeh. Bangkongtetpawiteh, sahnin kamnue e patetlah nangmae Cathut ni hote siangpahrang nangmae kut dawk na poe hanelah, lung a tha o sak, lungpatanae lungthin a poe.
31 Olúwa sì bá mi sọ̀rọ̀ pé, “Kíyèsi i, mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ní fi Sihoni àti ilẹ̀ rẹ̀ lé e yín lọ́wọ́. Báyìí, ẹ máa ṣẹ́gun rẹ̀, kí ẹ sì gba ilẹ̀ rẹ̀.”
Cathut ni hai Sihon siangpahrang hoi a talai hah na poe han. Hote talai hah râw lah na pang hanelah lat lawih telah a dei.
32 Nígbà tí Sihoni àti gbogbo àwọn jagunjagun rẹ̀ jáde wá láti bá wa jagun ní Jahasi,
Hatnavah, Sihon siangpahrang teh amae tami puenghoi Jahaz vah maimanaw na tuk hanelah a tâco.
33 Olúwa Ọlọ́run wa fi lé wa lọ́wọ́ bẹ́ẹ̀ ni a ṣẹ́gun rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀ àti gbogbo ológun rẹ̀.
Maimae Cathut ni hote siangpahrang hah maimouh koe na poe teh, ama hoi a canaw hoi tami pueng ka thei awh.
34 Nígbà náà, gbogbo ìlú wọn ni a kó tí a sì pa wọ́n run pátápátá tọkùnrin, tobìnrin àti gbogbo ọmọ wọn. A kò sì dá ẹnikẹ́ni sí.
Hatnavah ahnie khopui pueng ka tuk awh teh, napui tongpa, camonaw buet touh hai hlung laipalah koung ka pâmit awh.
35 Ṣùgbọ́n a kó gbogbo ohun ọ̀sìn àti ìkógun àwọn ìlú tí a ṣẹ́gun fún ara wa.
Saringnaw, khopui dawk e hnopainaw dueng kamamouh hanlah ka la pouh awh.
36 Láti Aroeri, létí odò Arnoni àti láti àwọn ìlú tí ó wà lẹ́bàá odò náà títí ó fi dé Gileadi, kò sí ìlú tí ó lágbára jù fún wa, Olúwa Ọlọ́run wa fi gbogbo wọn fún wa.
Arnon tuipui teng kaawm e Aroer khopui hoi Gilead khopui totouh, tuipui teng kaawm e pueng khopuinaw thung, ka tâ thai hoeh e buet touh hai khopui awm hoeh. Maimae Cathut ni a cawngca pueng maimouh dawk na poe.
37 Ní ìbámu pẹ̀lú òfin Olúwa Ọlọ́run wa, ẹ kò súnmọ́ ọ̀kan nínú ilẹ̀ àwọn ará Ammoni, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò dé ilẹ̀ tí ó lọ sí Jabbok, tàbí ilẹ̀ tí ó yí àwọn ìlú òkè e nì ká.
Hatnavah Ammon miphunnaw a onae talai, Jabbok tuipui hoi talai, mon dawk e khopui hoi maimae Cathut ni na cakâ pouh e bang buet touh hai ka hnai awh hoeh.