< Deuteronomy 2 >
1 Nígbà náà ni a yípadà, tí a sì mú ọ̀nà wa pọ̀n lọ sí aginjù, a gba ọ̀nà Òkun Pupa, bí Olúwa ti darí mi. Ìgbà pípẹ́ ni a fi ń rìn kiri yíká agbègbè àwọn ìlú olókè Seiri.
ninia da sinidigili, wadela: i hafoga: i soge amoga asi. Gode da nama sia: beba: le, ninia da Maga: me Hano Wayabo ahoasu amoga asili, eso bagohame Idome agolo soge sisiga: le ahoanu.
2 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún mi pé,
Amola Hina Gode da nama amane sia: i,
3 “Ẹ ti rìn yí agbègbè ilẹ̀ olókè yìí pẹ́ tó, nísinsin yìí, ẹ yípadà sí ìhà àríwá.
‘Amo agolo soge sisiga: le bu udigili mae laloma. Sinidigili, gadili heda: ma.
4 Fún àwọn ènìyàn náà ní àwọn òfin wọ̀nyí: ‘Ẹ ti fẹ́ la ilẹ̀ àwọn arákùnrin yín kọjá, àwọn ọmọ Esau; àwọn ará Edomu tí ń gbé ní Seiri. Ẹ̀rù yín yóò bà wọ́n, ṣùgbọ́n ẹ ṣọ́ra gidigidi.
Isala: ili dunuma amane sia: ma, Dilia da dilia fi dunu, Iso egaga fi Idome agolo soge amo ganodini esala, ilia soge ganodini golili sa: ili, baligimu. Ilia da dilima beda: mu.
5 Ẹ má ṣe wá wọn níjà torí pé èmi kò ní fún un yín ní èyíkéyìí nínú ilẹ̀ wọn. Bí ó ti wù kí ó kéré mọ èmi kò ní fún un yín. Mo ti fi ilẹ̀ òkè Seiri fún Esau gẹ́gẹ́ bí ìní rẹ̀.
Be dilia da ilima mae gegema. Na da ilia soge fonobahadi fawane dilima hamedafa imunu. Amo Idome soge huluane Na da Iso egaga fi ilima i dagoi.
6 Ẹ san owó oúnjẹ tí ẹ bá jẹ fún wọn àti omi tí ẹ bá mu.’”
Be dilia da ha: i manu amola hano, ilima bidiga lamu da defea.’”
7 Olúwa Ọlọ́run yín ti bùkún un yín nínú gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín. Ó ti mójútó ìrìnàjò yín nínú aginjù ńlá yìí. Olúwa Ọlọ́run yín wà pẹ̀lú u yín ní ogójì ọdún wọ̀nyí, dé bi pé ẹ̀yin kò ṣaláìní ohunkóhun.
Mousese da eno amane sia: i, “Dilia mae gogolema! Hina Gode da dilia hou huluane hahawane fidi. Dilia da wadela: i hafoga: i soge amo ganodini ahoanoba, E da dili noga: le ouligi. Amo ode40wali gidigi amoga E da mae yolesili, dilia liligi huluane dilima i dagoi.
8 Bẹ́ẹ̀ ni a kọjá ọ̀dọ̀ àwọn arákùnrin wa, àwọn ọmọ Esau tí ń gbé ní Seiri. A yà kúrò ní ọ̀nà Arabah èyí tí ó wá láti Elati àti Esioni-Geberi, a sì rìn gba ọ̀nà aginjù Moabu.
Ninia Gode Ea sia: nababeba: le, asili, logo amo da Ila: de moilai amola Isionegiba moilai yolesili Maga: me Hanoga doaga: sa, amo logo ninia da yolesili guma: dini ahoanu, Moua: be sogega asi.
9 Olúwa sì sọ fún mi pé, “Ẹ má ṣe dẹ́rùba àwọn ará Moabu bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má ṣe bá wọn jagun torí pé n kò ní fi èyíkéyìí nínú ilẹ̀ wọn fún un yín. Mo ti fi Ari fún àwọn ọmọ Lọti bí i ìní.”
Hina Gode da nama amane sia: i, ‘Dilia da Moua: be dunu (Lode egaga fi) ilima mae gegema amola ilima se mae ima. Na da Aa moilai ilima i dagoi amola ilia soge Na da dilima hame imunu,’” Mousese da amane sia: i.
10 (Àwọn Emimu ti gbé ibẹ̀ rí, àwọn ènìyàn tó síngbọnlẹ̀ tó sì pọ̀, wọ́n ga bí àwọn Anaki.
(Dunu fi bagadedafa da Aa moilaiga esalu. Ilia fi dio da Imimi. Ilia sedade olei da dunu bagade eno amo A: nagimi fi ilia sedade olei defele ba: i.
11 Gẹ́gẹ́ bí Anaki àwọn ènìyàn náà pè wọ́n ní ará Refaimu ṣùgbọ́n àwọn ará Moabu pè wọ́n ní Emimu.
Eno dunu da Imimi amola A: nagimi gilisili da Lefa: ime [dunu sedade bagade] dio asuli. Be Moua: be dunu da ilima Imimi dio asuli.
12 Àwọn ará Hori gbé ní Seiri, kí àwọn ọmọ Esau tó lé wọn kúrò níwájú wọn. Wọ́n sì gba ilẹ̀ wọn, wọ́n tẹ̀dó sí ààyè wọn gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ Israẹli tí ṣe ní ilẹ̀ tí Olúwa yóò fún wọn ní ìní wọn.)
Musa: Holaide dunu da Idome soge ganodini esalu. Be Iso egaga fi da amo dunu sefasili, fane legei dagoi. Amalalu, ilisu da amo soge ganodini fi. Isala: ili dunu fi da fa: no Ga: ina: ne sogega [Gode da ilima i] ilima ha lai dunu sefasi, amo defele Iso egaga fi da Holaide dunu sefasi.)
13 Olúwa sì wí pé, “Ẹ dìde, kí ẹ sì la àfonífojì Seredi kọjá.” Bẹ́ẹ̀ ni a la àfonífojì náà kọjá.
Mousese da eno amane sia: i, “Amalalu, Gode Ea sia: beba: le ninia da Silede Hano amo degei dagoi.
14 Ó gbà wá ní ọdún méjìdínlógójì kí ó tó di wí pé a la àfonífojì Seredi kọjá láti ìgbà tí a ti kúrò ní Kadeṣi-Barnea. Nígbà náà gbogbo ìran àwọn tí ó jẹ́ jagunjagun láàrín àwọn ènìyàn náà ti ṣègbé kúrò láàrín àwọn ènìyàn náà ní àsìkò yìí bí Olúwa ti búra fún wọn.
Ninia da musa: Ga: idesie Bania fisili, ode38gidigili, amo hou ba: i. Amo ode ganodini Gode Ea sia: i defele ninia musa: dadi gagui amola asigilai gegesu dunu, huluane da bogoi dagoi ba: i.
15 Ọwọ́ Olúwa sì wà lòdì sí wọn nítòótọ́, láti run wọn kúrò nínú ibùdó, títí gbogbo wọn fi run tan.
Gode da ilima ha laiwane esalebeba: le, E da mae yolesili ili fane legelalu, huluane da hame ba: i.
16 Lẹ́yìn tí ẹni tí ó gbẹ̀yìn pátápátá nínú àwọn jagunjagun àwọn ènìyàn wọ̀nyí ti kú,
Amalalu, musa: asigilai gegesu dunu huluane ninia fi ganodini da bogoi dagoi ba: loba,
Hina Gode da nama amane sia: i,
18 “Lónìí ni ẹ̀yin yóò la agbègbè Moabu kọjá ní Ari.
‘Wali eso dilia Moua: be soge golili sa: ili, Aa moilai bai bagade ahoasu amoga baligima.
19 Bí ẹ bá dé ọ̀dọ̀ àwọn ará Ammoni, ẹ má ṣe halẹ̀ mọ́ wọn, ẹ kò sì gbọdọ̀ bá wọn jagun, torí pé èmi kì yóò fi àwọn ilẹ̀ tí ó jẹ́ ti àwọn ará Ammoni fún un yín ní ìní. Mo ti fi fún àwọn ọmọ Lọti ní ìní.”
Amalalu dilia da A: mone dunu (Lode egaga fi) ilia soge gadenene ba: mu. Be ilima mae gegema amola sia: ga mae gegema. Bai Na da amo soge Lode egaga fi ilima ia dagoiba: le, Na da amo soge dilima hame imunu.
20 (A ka ilẹ̀ yìí sí ilẹ̀ àwọn Refaimu, tí wọ́n ti gbé níbẹ̀ rí, ṣùgbọ́n àwọn ará Ammoni ń pè wọ́n ní ará Samsummimu.
(Amo soge ea dio eno da Lefa: ime [dunu sedade bagade musa: amoga esalu ilia dio]. Be A: monaide dunu da amo dunuma Sa: masamimi dio asuli.
21 Wọ́n jẹ́ àwọn ènìyàn tó lágbára, wọ́n sì pọ̀, wọ́n sì ga gogoro bí àwọn ará Anaki. Olúwa run wọn kúrò níwájú àwọn ará Ammoni, tí wọ́n lé wọn jáde tí wọ́n sì gba ilẹ̀ wọn.
Ilia sedade olei da A: nagimi dunu defele ba: i. Ilia da dunu bagohame amola bagade fi dialu. Be Gode da amo dunu fi fane legei dagoi. Amalalu, A:mone fi dunu da ilia soge gesowale fi galu.
22 Bákan náà ni Olúwa ṣe fún àwọn ọmọ Esau, tí wọ́n ń gbé ní Seiri, nígbà tí ó pa àwọn ará Hori run níwájú wọn. Wọ́n lé wọn jáde wọ́n sì ń gbé ní ilẹ̀ wọn títí di òní.
Hina Gode da amo hou defele Idome dunu (ilia da Iso egaga fi wali Idome agolo sogega esala) amo fidimusa: hamoi. E da Holaide dunu fane legei dagoi. Amalalu, Idome dunu da ilia soge gesowale fi galu. Ilia wali amola amogai esala.
23 Nípa ti àwọn ará Affimu, tí wọ́n ń gbé ní àwọn ìlú kéékèèké dé Gasa, àwọn ará Kaftorimu, tí wọ́n jáde láti Krete wá ni ó pa wọ́n run, wọ́n sì gba ilẹ̀ wọn.)
Soge amo da Medidela: inia Wayabo Bagade bega: diala, amoga dunu fi musa: Galidi Oga esalu ilia da fi galu. Musa: dunu fi amogai esalu da A: ifimi. Ilia da soge huluane asili, Ga: isa moilai bai bagadega doaga: le esalu. Be Galidi dunu da ili fane legele, ilia soge huluane gesowale fi galu.)
24 “Ẹ gbáradì, kí ẹ sì kọjá odò Arnoni. Kíyèsi, Mo ti fi Sihoni ará Amori, ọba Heṣboni àti ilẹ̀ rẹ̀ lé ọ lọ́wọ́. Ẹ bá ilẹ̀ náà jagun kí ẹ sì gbà á.
Mousese da eno amane sia: i, “Ninia da Moua: be soge golili sa: ili, baligili, Hina Gode da ninima amane sia: i, ‘Hadiga! Anone hano degema. Na da Saihone (A: moulaide ouligisu dunu ea soge da Hesiabone), e amola ea soge dilima i dagoi. Dilia ema doagala: ma amola ea soge gesowale fima.
25 Èmi bẹ̀rẹ̀ sí ní fi ìbẹ̀rù àti ìfòyà yín sára gbogbo orílẹ̀-èdè lábẹ́ ọ̀run láti òní lọ. Wọn yóò gbọ́ ìròyìn in yín, wọn yóò sì wárìrì, wọn yóò sì wà nínú ìdààmú ọkàn torí i tiyín.”
Na (Hina Gode) Na gasaga, dunu huluane da dilia fiba: le beda: mu. Dilia dio fawane sia: sea, dunu huluane da yaguguli beda: mu.’”
26 Mo rán àwọn ìránṣẹ́ láti aginjù Kedemoti lọ́ sọ́dọ̀ Sihoni ọba Heṣboni pẹ̀lú ọ̀rọ̀ àlàáfíà wí pé,
“Amalalu, ninia da Gedimode wadela: i soge amo ganodini esalu, na da Hesiabone hina bagade Saihone ema sia: adole iasu dunu asunasi. Ilia da ema olofomusa: amane sia: i,
27 “Jẹ́ kí a la ilẹ̀ ẹ yín kọjá. Àwa yóò gba ti òpópónà nìkan. A kò ní yà sọ́tùn tàbí sósì.
‘Ninia da dia soge baligili masusa: dawa: lala. Ninia da moloiwane baligimu amola logo hame yolesimu.
28 Ẹ ta oúnjẹ tí a ó jẹ àti omi tí a ó mu fún wa ní iye owó wọn. Kìkì kí ẹ sá à jẹ́ kí a rìn kọjá:
Ninia ha: i amola hano manu lamu amo bidi imunu. Ninia da dia soge baligili masunu fawane.
29 gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ Esau tí ó ń gbé ní Seiri àti àwọn ará Moabu tí ó ń gbé ní Ari, ti gbà wá láààyè títí a fi la Jordani já dé ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run wa yóò fún wa.”
Amalalu, ninia da Yodane Hano degele, soge amo ninia Hina Gode da ninima iaha amo ganodini fimu. Iso egaga fi Idome soge ganodini esalu amola Moua: be dunu Aa ganodini esalu, da mae higale, ninia da ilia soge baligili masunu da defea sia: i.’
30 Ṣùgbọ́n Sihoni ọba Heṣboni kò gbà fún wa láti kọjá. Torí pé Olúwa Ọlọ́run yín ti mú ọkàn rẹ̀ yigbì, àyà rẹ̀ sì kún fún agídí kí ó ba à le fi lé e yín lọ́wọ́, bí ó ti ṣe báyìí.
Be hina bagade Saihone da ninia baligili masunu logo ga: i dagoi. Ninia da Saihone fane legele ea soge lamusa: Hina Gode da ea hou gasa fi agoane hamoi. Ninia da wali ea soge amogai fi diala.
31 Olúwa sì bá mi sọ̀rọ̀ pé, “Kíyèsi i, mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ní fi Sihoni àti ilẹ̀ rẹ̀ lé e yín lọ́wọ́. Báyìí, ẹ máa ṣẹ́gun rẹ̀, kí ẹ sì gba ilẹ̀ rẹ̀.”
Amalalu, Hina Gode da nama amane sia: i, ‘Ba: ma! Na da hina bagade Saihone amola ea fi gasa hame agoane hamoi dagoi. Dilia ea soge gesowale fima.’
32 Nígbà tí Sihoni àti gbogbo àwọn jagunjagun rẹ̀ jáde wá láti bá wa jagun ní Jahasi,
Saihone amola ea dadi gagui dunu huluane da Ya: iha: se soge gadenene ninima gegemusa: misi.
33 Olúwa Ọlọ́run wa fi lé wa lọ́wọ́ bẹ́ẹ̀ ni a ṣẹ́gun rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀ àti gbogbo ológun rẹ̀.
Be Hina Gode da ninima gasa i. Ninia da Saihone amola egefe, ea dunu huluane medole legei dagoi.
34 Nígbà náà, gbogbo ìlú wọn ni a kó tí a sì pa wọ́n run pátápátá tọkùnrin, tobìnrin àti gbogbo ọmọ wọn. A kò sì dá ẹnikẹ́ni sí.
Amo esoga, ninia da moilai huluane lale mugului dagoi. Ninia da dunu, uda amola mano, huluane medole legei dagoi.
35 Ṣùgbọ́n a kó gbogbo ohun ọ̀sìn àti ìkógun àwọn ìlú tí a ṣẹ́gun fún ara wa.
Ninia ilia bulamagau huluane lai amola liligi huluane moilai ganodini amo lai dagoi.
36 Láti Aroeri, létí odò Arnoni àti láti àwọn ìlú tí ó wà lẹ́bàá odò náà títí ó fi dé Gileadi, kò sí ìlú tí ó lágbára jù fún wa, Olúwa Ọlọ́run wa fi gbogbo wọn fún wa.
Ninia Hina Gode da ninia logo fodoiba: le, ninia moilai huluane amo Aloua (amo da Anone fago bega: dialu) amola moilai eno Anone fago ganodini dogoa dialu amola eno moilai huluane asili, Gilia: de sogega doaga: le, huluane lai dagoi. Moilai huluane ilia sisiga: le gagoi da ninima gasa hame agoai ba: i.
37 Ní ìbámu pẹ̀lú òfin Olúwa Ọlọ́run wa, ẹ kò súnmọ́ ọ̀kan nínú ilẹ̀ àwọn ará Ammoni, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò dé ilẹ̀ tí ó lọ sí Jabbok, tàbí ilẹ̀ tí ó yí àwọn ìlú òkè e nì ká.
Be ninia A: monaide dunu ilia soge amola soge amo Ya: boge Hano bega: dialu amola moilai agolo soge ganodini dialu amola soge huluane Hina Gode da ninima mae masa: ne sia: i, amoga ninia da hame asi.”