< Deuteronomy 17 >

1 Ẹ má ṣe fi màlúù tàbí àgùntàn tí ó ní àbùkù, tàbí àbàwọ́n rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run yín, nítorí ìríra ni èyí yóò jẹ́ fún un.
Mũtikanarutĩre Jehova Ngai wanyu igongona rĩa ndegwa kana rĩa ngʼondu ĩrĩ na kaũũgũ kana ũũgũ, nĩgũkorwo ũndũ ũcio ũrĩ thaahu harĩ Jehova.
2 Bí ọkùnrin tàbí obìnrin kan tó ń gbé láàrín yín ní èyíkéyìí ìlú wọ̀n-ọn-nì, tí Olúwa fún un yín bá ń ṣe ibi ní ojú Olúwa Ọlọ́run yín, ní ríré májẹ̀mú rẹ̀ kọjá,
Mũndũ mũrũme kana mũndũ-wa-nja ũtũũranagia na inyuĩ itũũra-inĩ rĩmwe rĩa kũrĩa Jehova ekũmũhe, angĩoneka agĩĩka ũũru maitho-inĩ ma Jehova Ngai wanyu na ũndũ wa gũthũkia kĩrĩkanĩro gĩake,
3 èyí tí ó lòdì sí òfin mi, ó ń sin ọlọ́run mìíràn, ó ń foríbalẹ̀ fún wọn: àní sí oòrùn, òṣùpá àti àwọn ìràwọ̀ ojú ọ̀run,
na agakararia rĩathani rĩakwa akahooya ngai ingĩ, na agaciinamĩrĩra kana akainamĩrĩra riũa, kana mweri, kana njata cia matu-inĩ,
4 tí èyí sì dé etí ìgbọ́ ọ yín, kí ẹ wádìí ọ̀rọ̀ náà dájúdájú. Bí ó bá jẹ́ òtítọ́ tí ó sì hàn gbangba pé ó ti ṣe ohun ìríra yìí, ní Israẹli.
na mũmenyithio ũhoro ũcio-rĩ, hĩndĩ ĩyo no nginya mũgaatuĩria ũhoro ũcio wega. Kũngĩkorwo ũhoro ũcio nĩ wa ma, na hakorwo na ũira atĩ ũndũ ũcio ũrĩ thaahu nĩwĩkĩtwo thĩinĩ wa Isiraeli,
5 Ẹ mú ọkùnrin tàbí obìnrin tí ó ti ṣe ibi yìí wá sí ẹnu-ọ̀nà ibodè ìlú u yín, kí ẹ sọ ọ́ ní òkúta pa.
oyai mũndũ mũrũme kana mũndũ-wa-nja ũcio wĩkĩte ũndũ ũcio mũũru mũmũtware kĩhingo-inĩ gĩa itũũra rĩanyu inene na inyuĩ mũmũhũre na mahiga nyuguto nginya akue.
6 Lénu ẹlẹ́rìí méjì tàbí mẹ́ta ni a ó pa ọkùnrin náà tí ó yẹ láti kú, ṣùgbọ́n ẹ má ṣe pànìyàn nípasẹ̀ ẹlẹ́rìí kan ṣoṣo.
Na ũndũ wa ũira wa andũ eerĩ kana atatũ, mũndũ no oragwo, no gũtirĩ mũndũ ũkooragwo na ũndũ wa ũira wa mũndũ ũmwe.
7 Àwọn ẹlẹ́rìí ni kí ó kọ́kọ́ gbọ́wọ́ lé e láti pa á. Lẹ́yìn èyí ni kí gbogbo ènìyàn dáwọ́jọ láti pa á. Nípa báyìí, ẹ̀yin yóò sì fọ ohun búburú náà mọ́ kúrò ní àárín yín.
Moko ma aira acio no nginya makorwo marĩ ma mbere ũhoro-inĩ ũcio wa kũmũũraga, na thuutha ũcio marũmĩrĩrwo nĩ moko ma andũ arĩa angĩ othe. No nginya mũniine ũũru ũcio wehere gatagatĩ-inĩ kanyu.
8 Bí ẹjọ́ bá wá sí ilé ẹjọ́ èyí tí ó nira jù láti dá, yálà ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ni, ọ̀ràn dídá tàbí ìkanni-lábùkù, ẹ mú wọn lọ sí ibi tí Olúwa Ọlọ́run yín yóò yàn.
Kũngĩkaagĩa maciira magooti-inĩ manyu mũtangĩhota gũtua, marĩ ma ũiti wa thakame, o na ma gũtuithania mũndũ na mũndũ ũrĩa ũngĩ, kana mũndũ ũhũũrĩte ũrĩa ũngĩ, matwaragei handũ harĩa Jehova Ngai wanyu agaathuura.
9 Ẹ lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn àlùfáà tí í ṣe Lefi, àní sí ọ̀dọ̀ adájọ́ tí ó wà fún ìgbẹ́jọ́ ní ìgbà náà. Ẹ béèrè lọ́wọ́ wọn, wọn yóò sì ṣe ìdájọ́.
Thiĩi kũrĩ Alawii arĩa athĩnjĩri-Ngai, na kũrĩ mũtuithania ciira ũrĩa ũrĩ wĩra-inĩ ihinda rĩu. Mũmoorie ũhoro ũcio nao mamuonie ũrĩa ciira ũcio wagĩrĩire gũtuuo.
10 Kí ìwọ kí ó sì ṣe bí ọ̀rọ̀ ìdájọ́, ti àwọn ará ibi tí Olúwa yóò yàn náà yóò fihàn ọ, kí ìwọ kí ó sì máa kíyèsí àti máa ṣe gẹ́gẹ́ bi gbogbo èyí tí wọn kọ́ ọ.
No nginya mwĩke kũringana na matua marĩa makaamũhe mũrĩ handũ hau Jehova agaathuura. Menyagĩrĩrai mwĩkage ũrĩa wothe marĩmwathaga mwĩke.
11 Ẹ ṣe bí òfin tí wọ́n kọ́ ọ yín, àti ìpinnu tí wọ́n fún un yín. Ẹ má ṣe yípadà sọ́tùn tàbí sósì, kúrò nínú ohun tí wọ́n sọ fún un yín.
Ĩkagai kũringana na watho ũrĩa mamũrutĩte, na mũrũmĩrĩre matua mao marĩa mekũmũhe. Mũtikanehũgũre mwena wa ũrĩo kana wa ũmotho, mũtigane na ũrĩa mamwĩrĩte.
12 Ọkùnrin náà tí ó bá ṣe àìbọ̀wọ̀ fún adájọ́ tàbí àlùfáà tí ó ń ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ sí Olúwa Ọlọ́run yín, níbẹ̀ ni kí ẹ pa á. Nípa báyìí ẹ̀yin yóò sì fọ ohun búburú náà mọ́ kúrò ní Israẹli.
Mũndũ ũrĩa ũngĩonania kũnyarara mũtuithania ciira kana mũthĩnjĩri-Ngai, ũrĩa ũrũgamaga agĩtungatĩra Jehova Ngai wanyu, no nginya ooragwo. No nginya mũniine ũũru ũcio wehere Isiraeli.
13 Gbogbo ènìyàn ni yóò sì gbọ́, ẹ̀rù yóò sì bà wọ́n, wọn kò sì ní ṣe àìgbọ́ràn mọ́.
Andũ othe nĩmakaigua ũhoro ũcio nao metigĩre, na matigacooka gũkorwo marĩ na kĩnyararo rĩngĩ.
14 Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ náà tí Olúwa Ọlọ́run yín yóò fún un yín, tí ẹ sì ti gba ilẹ̀ náà, tí ẹ sì ń gbé inú rẹ̀, tí ẹ sì wá sọ pé, “Ẹ jẹ́ kí a yan ọba tí yóò jẹ lé wa lórí bí i ti àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí wa ká.”
Rĩrĩa mũgaathiĩ bũrũri ũrĩa Jehova Ngai wanyu ekũmũhe, na mũkorwo mũwĩgwatĩire na mũgaatũũra kuo, na muuge atĩrĩ, “Rekei tũgĩe na mũthamaki witũ ta ndũrĩrĩ iria ciothe itũthiũrũrũkĩirie,”
15 Ẹ rí i dájú pé ọba tí Olúwa Ọlọ́run yín yàn fún un yín ní ẹ yàn. Ó gbọdọ̀ jẹ́ láàrín àwọn arákùnrin yín. Ẹ má ṣe fi àjèjì jẹ ọba lórí i yín: àní ẹni tí kì í ṣe arákùnrin ní Israẹli.
Menyererai wega mũgaathuura mũthamaki ũrĩa Jehova Ngai wanyu amwamũrĩire. No nginya akoima gatagatĩ-inĩ ka ariũ a ithe wanyu. Mũtigathuure mũndũ wa kũngĩ atuĩke mũthamaki wanyu, mũndũ ũtarĩ mũrũ wa thoguo Mũisiraeli.
16 Síwájú sí i, ọba náà kò gbọdọ̀ kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹṣin jọ fún ara rẹ̀, tàbí kí ó rán àwọn ènìyàn náà padà sí Ejibiti láti wá àwọn ẹṣin sí i, nítorí pé Olúwa ti sọ fún un yín pé, “Ẹ kò gbọdọ̀ tún padà lọ ní ọ̀nà náà mọ́.”
Mũthamaki ũcio, o nake ndakaneingĩhĩrie mbarathi, kana atũme andũ macooke bũrũri wa Misiri makamũgĩĩrĩre ingĩ, nĩgũkorwo Jehova amwĩrĩte atĩrĩ, “Mũtikanacooke na thuutha, mũgere njĩra ĩyo rĩngĩ.”
17 Kò gbọdọ̀ kó aya jọ, kí ọkàn rẹ̀ má bá a yapa kúrò. Kò gbọdọ̀ kó fàdákà àti wúrà jọ fún ara rẹ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
Nake ndakanahikie atumia aingĩ, nĩguo ngoro yake ndĩkanagarũrũke. Ningĩ ndakaneingĩhĩrie betha na thahabu.
18 Nígbà tí ó bá jókòó lórí ìtẹ́ ìjọba rẹ̀, kí ó ṣe àdàkọ àwọn òfin wọ̀nyí sí inú ìwé fún ara rẹ̀, láti inú ti àlùfáà tí wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi.
Rĩrĩa agaikarĩra gĩtĩ gĩake kĩa ũthamaki, akoya ibuku rĩa gĩkũnjo, eyandĩkĩre watho ũyũ, aũrutĩte ibuku-inĩ rĩrĩa riumĩte harĩ athĩnjĩri-Ngai, arĩ o Alawii.
19 Èyí yóò sì wà lọ́dọ̀ rẹ̀, òun ó sì máa kà nínú rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀, kí ó lè máa kọ́ àti bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, láti máa tẹ̀lé gbogbo ọ̀rọ̀ inú òfin yìí àti àwọn ìlànà rẹ̀ tọkàntọkàn.
Narĩo ibuku rĩu nĩaikarage narĩo, arĩthomage matukũ marĩa mothe egũtũũra muoyo nĩguo erutage gwĩtigĩra Jehova Ngai, na arũmagĩrĩre wega ciugo ciothe cia watho ũyũ na irĩra cia watho wa kũrũmagĩrĩrwo,
20 Kí ó má ba à lérò pé òun sàn ju àwọn arákùnrin rẹ̀ yòókù lọ, kí ó sì ti ipa bẹ́ẹ̀ yípadà kúrò nínú òfin wọ̀nyí sí ọ̀tún tàbí sí òsì. Bẹ́ẹ̀ ni òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò jẹ ọba pẹ́ títí ní Israẹli.
na ndagetuage mwega gũkĩra ariũ a ithe agarũrũke mwena wa ũrĩo kana wa ũmotho atigane na watho. Hĩndĩ ĩyo, we na njiaro ciake nĩmagathamaka ihinda iraaya ũthamaki-inĩ wake kũu Isiraeli.

< Deuteronomy 17 >