< Deuteronomy 15 >

1 Ní òpin ọdún méje méje, ẹ̀yin gbọdọ̀ máa yọ̀ǹda àwọn gbèsè.
در پایان هر هفت سال، باید تمام قرضهای بدهکاران خود را ببخشید.
2 Báyìí ni kí ẹ máa ṣe é. Gbogbo ẹni tí wọ́n jẹ ní gbèsè gbọdọ̀ fojú fo gbèsè tí ó ti yá ará Israẹli ènìyàn rẹ̀. Kò gbọdọ̀ béèrè ohun náà, lọ́dọ̀ ará Israẹli ènìyàn rẹ̀ tàbí lọ́dọ̀ arákùnrin rẹ̀: nítorí pé a ti kéde àkókò Olúwa láti fojú fo gbèsè.
هر که از همسایه یا برادر یهودی خود طلبی داشته باشد باید آن طلب را لغو نماید. او نباید در صدد پس گرفتن طلبش باشد، زیرا خود خداوند این طلب را لغو نموده است.
3 Ẹ lè béèrè ìsanpadà lọ́dọ̀ àjèjì. Ṣùgbọ́n ẹ fa igi lé gbèsè yówù kó jẹ́ tí arákùnrin yín jẹ yín.
ولی این قانون شامل حال بدهکاران غیریهودی نمی‌شود.
4 Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí yóò tọ́ sí nínú yín, nítorí pé Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín lọ́pọ̀lọ́pọ̀ nínú ilẹ̀ náà tí ó ń mú un yín lọ láti gbà bí ìní yín.
اگر به دقت، تمام دستورهای خداوند، خدایتان را اطاعت کنید و اوامری را که امروز به شما می‌دهم اجرا نمایید در سرزمینی که خداوند به شما می‌دهد برکت زیادی خواهید یافت، به طوری که فقیری در میان شما نخواهد بود.
5 Kìkì bí ẹ bá gbọ́rọ̀ sí àṣẹ Olúwa Ọlọ́run yín tí ẹ sì kíyèsára láti máa rìn nínú gbogbo àṣẹ wọ̀nyí, tí èmi ń pa fún un yín lónìí.
6 Nítorí pé Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín bí ó ti ṣèlérí, ẹ̀yin yóò sì máa yá ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ẹ kì yóò sì tọrọ. Ẹ ó ṣàkóso ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè, ṣùgbọ́n kò sí orílẹ̀-èdè tí yóò lè jẹ ọba lé e yín lórí.
یهوه خدایتان چنانکه وعده داده است برکتتان خواهد داد، به طوری که به قومهای زیادی پول قرض خواهید داد، ولی هرگز احتیاجی به قرض گرفتن نخواهید داشت. بر قومهای بسیاری حکومت خواهید کرد، ولی آنان بر شما حکومت نخواهند نمود.
7 Bí tálákà kan bá wà láàrín àwọn arákùnrin yín ní èyíkéyìí àwọn ìlú, ilẹ̀ náà tí Olúwa yín yóò fún un yín. Ẹ má ṣe ṣe àìláàánú, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má ṣe háwọ́ sí arákùnrin yín tí ó jẹ́ tálákà.
وقتی به سرزمینی که یهوه خدایتان به شما می‌دهد وارد شدید، اگر در بین شما اشخاص فقیری باشند نسبت به آنان دست و دل باز باشید،
8 Ṣùgbọ́n ẹ lawọ́ kí ẹ sì fi tọkàntọkàn yá wọn ní ohun tí wọ́n nílò.
و هر قدر احتیاج دارند به ایشان قرض بدهید.
9 Ẹ ṣọ́ra kí èrò búburú kan má ṣe sí nínú àyà rẹ wí pé, “Ọdún keje tí í ṣe ọdún ìyọ̀ǹda gbèsè ti súnmọ́,” nípa bẹ́ẹ̀, ojú rẹ a sì burú sí arákùnrin rẹ tálákà, tí ìwọ kò sì fun ní nǹkan, o kò sì fun ní nǹkan kan. Òun a si kígbe pe Olúwa nítorí rẹ, a si di ẹ̀ṣẹ̀ fún ọ.
این فکر پلید را به خود راه ندهید که سال بخشیدن قرض به‌زودی فرا می‌رسد و در نتیجه از دادن قرض خودداری کنید؛ زیرا اگر از دادن قرض خودداری کنید و مرد محتاج پیش خداوند ناله کند این عمل برای شما گناه محسوب خواهد شد.
10 Fún un tọkàntọkàn, láìsí ìkùnsínú, nítorí èyí, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún fún ọ nínú iṣẹ́ ọwọ́ rẹ, àti gbogbo ìdáwọ́lé rẹ.
باید آنچه نیاز دارد، از صمیم قلب به او بدهید و یهوه خدایتان هم به خاطر این امر، شما را در هر کاری برکت خواهد داد.
11 A kò lè fẹ́ tálákà kù ní ilẹ̀ náà ní ìgbà gbogbo, mo pàṣẹ fún un yín láti lawọ́ sí àwọn arákùnrin yín, sí àwọn tálákà àti sí àwọn aláìní, ní ilẹ̀ ẹ yín.
در میان شما همیشه فقیر وجود خواهد داشت به همین دلیل است که به شما فرمان می‌دهم که با گشاده‌دستی به فقیران و برادران نیازمند خود قرض بدهید.
12 Bí Heberu ara yín kan, yálà ọkùnrin tàbí obìnrin bá ta ara rẹ̀ fún ọ, tí ó sì sìn ọ́ fún ọdún mẹ́fà. Ní ọdún keje, jẹ́ kí ó di òmìnira.
هرگاه یکی از برادران عبرانیِ شما، خواه مرد و خواه زن، به شما فروخته شود، و شش سال شما را خدمت کند، سال هفتم او را آزاد کرده، بگذارید از نزد شما برود.
13 Nígbà tí ó bá dá a sílẹ̀ má ṣe jẹ́ kí ó lọ lọ́wọ́ òfo.
او را دست خالی روانه نکنید،
14 Fi tọkàntọkàn fún un láti inú agbo ewúrẹ́ rẹ, ilẹ̀ ìpakà rẹ, àti ibi ìfúntí rẹ. Fún un gẹ́gẹ́ bí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti bùkún fún ọ tó.
بلکه هدیه‌ای از گله و غله و شراب مطابق برکتی که خداوند، خدایتان به شما بخشیده است به وی بدهید.
15 Ẹ rántí pé ẹ ti fi ìgbà kan jẹ́ ẹrú ní Ejibiti, Olúwa Ọlọ́run yín sì rà yín padà, ìdí nìyí tí mo fi pa àṣẹ yìí fún un yín lónìí.
به خاطر بیاورید که در سرزمین مصر بَرده بودید و خداوند، خدایتان شما را نجات داد. به همین دلیل است که امروز این فرمان را به شما می‌دهم.
16 Ṣùgbọ́n bí ìránṣẹ́ rẹ bá sọ fún ọ pé, “Èmi kò fẹ́ fi ọ́ sílẹ̀,” nítorí pé ó fẹ́ràn ìwọ àti ìdílé rẹ, tí ó sì tẹ́ ọ lọ́rùn,
ولی اگر غلام عبرانی شما نخواهد برود و بگوید شما و خانواده‌تان را دوست دارد و از بودن در خانهٔ شما لذت می‌برد،
17 kí ìwọ kí ó mú ìlu kan lu etí rẹ̀ mọ́ ara ìlẹ̀kùn, yóò sì di ẹrú rẹ láéláé. Bẹ́ẹ̀ náà ni kí o ṣe sí ìránṣẹ́ ẹrúbìnrin rẹ.
آنگاه او را کنار در خانه قرار دهید و با درفشی گوشش را سوراخ کنید تا از آن پس، همیشه غلام شما باشد. با کنیزان خود نیز چنین کنید.
18 Má ṣe kà á sí ohun ìnira láti dá ẹrú rẹ sílẹ̀, nítorí ìsìnrú rẹ̀ fún ọ, ní ọdún mẹ́fà náà tó ìlọ́po méjì iṣẹ́ alágbàṣe, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún fún ọ nínú gbogbo ìdáwọ́lé rẹ.
اما وقتی که برده‌ای را آزاد می‌کنید نباید ناراحت شوید، زیرا طیِ شش سال به اندازۀ دو برابر دستمزد یک کارگر شما را خدمت کرده است. یهوه خدایتان شما را در هر کاری که بکنید، برکت خواهد داد.
19 Gbogbo àkọ́bí tí o jẹ́ akọ nínú agbo màlúù rẹ ni kí o yà sọ́tọ̀ fún Olúwa, àti nínú agbo ewúrẹ́ bákan náà. Ẹ má ṣe fi àkọ́bí màlúù yín ṣiṣẹ́ rárá. Má ṣe rẹ́ irun àkọ́bí àgùntàn rẹ pẹ̀lú.
باید تمامی نخست‌زاده‌های نر گله‌ها و رمه‌هایتان را برای یهوه خدایتان وقف کنید. از نخست‌زاده‌های رمه‌هایتان جهت کار کردن در مزارع خود استفاده نکنید و پشم نخست‌زاده‌های گله‌های گوسفندتان را قیچی نکنید.
20 Ní ọdọọdún ni kí ìwọ àti ìdílé rẹ máa jẹ ẹ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín níbi tí Òun yóò yàn.
به جای آن، شما و خانواده‌تان هر ساله گوشت این حیوانات را در حضور خداوند، خدایتان در محلی که او تعیین خواهد کرد بخورید.
21 Bí ẹran ọ̀sìn kan bá ní àbùkù: bóyá ó yarọ, tàbí fọ́jú, tàbí tí ó ní èyíkéyìí àbùkù tó burú. Ẹ kò gbọdọ̀ fi rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run yín.
ولی اگر حیوان نخست‌زاده معیوب باشد، مثلاً لنگ یا کور بوده، یا عیب دیگری داشته باشد، نباید آن را برای یهوه خدایتان قربانی کنید.
22 Ẹ jẹ ẹ́ ní ìlú u yín. Àti ẹni tí a kà sí mímọ́ àti aláìmọ́ ni ó lè jẹ ẹ́ bí ìgbà tí a ń jẹ èsúró tàbí àgbọ̀nrín.
در عوض از آن برای خوراک خانوادهٔ خود در منزل استفاده کنید. هر کس می‌تواند آن را بخورد، حتی اگر نجس باشد، درست همان‌طور که غزال یا آهو را می‌خورد؛
23 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀, ẹ dà á síta bí omi.
ولی خون آن را نخورید، بلکه آن را مثل آب بر زمین بریزید.

< Deuteronomy 15 >