< Deuteronomy 15 >

1 Ní òpin ọdún méje méje, ẹ̀yin gbọdọ̀ máa yọ̀ǹda àwọn gbèsè.
Na rĩrĩ, mĩaka mũgwanja yathira, no nginya mũkarekanagĩra mathiirĩ.
2 Báyìí ni kí ẹ máa ṣe é. Gbogbo ẹni tí wọ́n jẹ ní gbèsè gbọdọ̀ fojú fo gbèsè tí ó ti yá ará Israẹli ènìyàn rẹ̀. Kò gbọdọ̀ béèrè ohun náà, lọ́dọ̀ ará Israẹli ènìyàn rẹ̀ tàbí lọ́dọ̀ arákùnrin rẹ̀: nítorí pé a ti kéde àkókò Olúwa láti fojú fo gbèsè.
Ũndũ ũcio mũrĩwĩkaga ũũ: mũkombithania o wothe nĩarĩrekanagĩra thiirĩ o wothe ũrĩa akombeire Mũisiraeli ũrĩa ũngĩ. Ndakarandũra Mũisiraeli ũrĩa ũngĩ thiirĩ kana mũrũ wa ithe, nĩ ũndũ ihinda rĩa Jehova rĩa kũrekanĩra mathiirĩ nĩrĩhunjanĩirio.
3 Ẹ lè béèrè ìsanpadà lọ́dọ̀ àjèjì. Ṣùgbọ́n ẹ fa igi lé gbèsè yówù kó jẹ́ tí arákùnrin yín jẹ yín.
No mũrandũre mũndũ wa kũngĩ thiirĩ, no rĩrĩ, no nginya mũrekanĩre thiirĩ o wothe ũrĩa mũrũ wa thoguo arĩ naguo.
4 Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí yóò tọ́ sí nínú yín, nítorí pé Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín lọ́pọ̀lọ́pọ̀ nínú ilẹ̀ náà tí ó ń mú un yín lọ láti gbà bí ìní yín.
No rĩrĩ, gũtiagĩrĩire gũkorwo na mũndũ mũthĩĩni thĩinĩ wanyu, nĩgũkorwo mũrĩ bũrũri-inĩ ũcio Jehova Ngai wanyu ekũmũhe mũwĩgwatĩre ũtuĩke igai rĩanyu-rĩ, nĩakamũrathima mũno,
5 Kìkì bí ẹ bá gbọ́rọ̀ sí àṣẹ Olúwa Ọlọ́run yín tí ẹ sì kíyèsára láti máa rìn nínú gbogbo àṣẹ wọ̀nyí, tí èmi ń pa fún un yín lónìí.
angĩkorwo nĩmũgwathĩkĩra Jehova Ngai wanyu biũ, o na mũmenyagĩrĩre kũrũmagĩrĩra maathani maya mothe ngũmũhe ũmũthĩ.
6 Nítorí pé Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín bí ó ti ṣèlérí, ẹ̀yin yóò sì máa yá ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ẹ kì yóò sì tọrọ. Ẹ ó ṣàkóso ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè, ṣùgbọ́n kò sí orílẹ̀-èdè tí yóò lè jẹ ọba lé e yín lórí.
Nĩgũkorwo Jehova Ngai wanyu nĩakamũrathima ta ũrĩa eeranĩire, na nĩmũgakombagĩra ndũrĩrĩ nyingĩ, no inyuĩ mũtigaakombaga harĩ cio. Nĩmũgaathaga ndũrĩrĩ nyingĩ, no cio itikamwathaga.
7 Bí tálákà kan bá wà láàrín àwọn arákùnrin yín ní èyíkéyìí àwọn ìlú, ilẹ̀ náà tí Olúwa yín yóò fún un yín. Ẹ má ṣe ṣe àìláàánú, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má ṣe háwọ́ sí arákùnrin yín tí ó jẹ́ tálákà.
Kũngĩgaakorwo na mũndũ mũthĩĩni gatagatĩ-inĩ ka ariũ a ithe wanyu itũũra-inĩ o rĩothe kũu bũrũri-inĩ ũcio Jehova Ngai wanyu ekũmũhe-rĩ, mũtikanamũmĩrie ngoro, kana mũtuĩke akarĩ kũrĩ mũrũ wa ithe wanyu ũcio mũthĩĩni.
8 Ṣùgbọ́n ẹ lawọ́ kí ẹ sì fi tọkàntọkàn yá wọn ní ohun tí wọ́n nílò.
No rĩrĩ, nĩ kaba mũmũtambũrũkĩrie guoko, na mũmũkombithie kĩrĩa gĩothe akaabatario nĩkĩo.
9 Ẹ ṣọ́ra kí èrò búburú kan má ṣe sí nínú àyà rẹ wí pé, “Ọdún keje tí í ṣe ọdún ìyọ̀ǹda gbèsè ti súnmọ́,” nípa bẹ́ẹ̀, ojú rẹ a sì burú sí arákùnrin rẹ tálákà, tí ìwọ kò sì fun ní nǹkan, o kò sì fun ní nǹkan kan. Òun a si kígbe pe Olúwa nítorí rẹ, a si di ẹ̀ṣẹ̀ fún ọ.
Mwĩmenyererei mũtikanagĩe na meciiria mooru, mũkoiga atĩrĩ: “Mwaka wa mũgwanja, mwaka ũrĩa wa kũrekanĩra mathiirĩ ũrĩ hakuhĩ,” nĩguo mũtikagĩe na ngoro njũru, mwage gũtaanahĩra mũrũ wa ithe wanyu ũrĩa ũbataire, kana mwage kũmũhe kĩndũ. Nake hĩndĩ ĩyo no akaĩre Jehova nĩ ũndũ wanyu, na inyuĩ nĩmũkonwo mwĩhĩtie.
10 Fún un tọkàntọkàn, láìsí ìkùnsínú, nítorí èyí, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún fún ọ nínú iṣẹ́ ọwọ́ rẹ, àti gbogbo ìdáwọ́lé rẹ.
Heagai mũndũ ta ũcio na ũtaana, na mwĩkage ũndũ ũcio na ngoro itarĩ na ũũru; na nĩ ũndũ wa ũguo-rĩ, Jehova Ngai wanyu nĩarĩmũrathimaga mawĩra-inĩ manyu mothe, o na maũndũ-inĩ mothe marĩa mũrĩĩkaga.
11 A kò lè fẹ́ tálákà kù ní ilẹ̀ náà ní ìgbà gbogbo, mo pàṣẹ fún un yín láti lawọ́ sí àwọn arákùnrin yín, sí àwọn tálákà àti sí àwọn aláìní, ní ilẹ̀ ẹ yín.
Nĩkũrĩkoragwo na andũ athĩĩni hĩndĩ ciothe bũrũri-inĩ. Nĩ ũndũ ũcio ngũmwatha mũtuĩke ataana kũrĩ ariũ a ithe wanyu, na kũrĩ andũ arĩa athĩĩni o na abatari arĩa marĩkoragwo bũrũri-inĩ wanyu.
12 Bí Heberu ara yín kan, yálà ọkùnrin tàbí obìnrin bá ta ara rẹ̀ fún ọ, tí ó sì sìn ọ́ fún ọdún mẹ́fà. Ní ọdún keje, jẹ́ kí ó di òmìnira.
Mũrũ wa ithe wanyu Mũhibirania, arĩ mũndũ mũrũme kana mũndũ-wa-nja, angĩĩyendia kũrĩ we na agũtungatĩre mĩaka ĩtandatũ-rĩ, mwaka wa mũgwanja wakinya no nginya ũkaamũrekereria athiĩ.
13 Nígbà tí ó bá dá a sílẹ̀ má ṣe jẹ́ kí ó lọ lọ́wọ́ òfo.
Na rĩrĩa ũkaamũrekereria, ndũkanareke athiĩ moko matheri.
14 Fi tọkàntọkàn fún un láti inú agbo ewúrẹ́ rẹ, ilẹ̀ ìpakà rẹ, àti ibi ìfúntí rẹ. Fún un gẹ́gẹ́ bí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti bùkún fún ọ tó.
Nĩũkamũhe indo na ũtaana kuuma rũũru-inĩ rwaku, o na kuuma kĩhũrĩro-inĩ gĩaku kĩa ngano o na kĩhihĩro-inĩ kĩa ndibei. Ũkaamũhe indo kũringana na ũrĩa Jehova Ngai waku akũrathimĩte.
15 Ẹ rántí pé ẹ ti fi ìgbà kan jẹ́ ẹrú ní Ejibiti, Olúwa Ọlọ́run yín sì rà yín padà, ìdí nìyí tí mo fi pa àṣẹ yìí fún un yín lónìí.
Ririkanaga atĩ o na we warĩ ngombo kũu bũrũri wa Misiri, no Jehova Ngai waku agĩgũkũũra. Kĩu nĩkĩo gĩatũma ngũhe rĩathani rĩu ũmũthĩ.
16 Ṣùgbọ́n bí ìránṣẹ́ rẹ bá sọ fún ọ pé, “Èmi kò fẹ́ fi ọ́ sílẹ̀,” nítorí pé ó fẹ́ràn ìwọ àti ìdílé rẹ, tí ó sì tẹ́ ọ lọ́rùn,
No rĩrĩ, ndungata yaku ĩngĩgakwĩra atĩrĩ, “Niĩ ndikwenda gũgũtiga,” nĩ ũndũ nĩĩkwendete na ĩkenda andũ a nyũmba yaku, na nĩ ũndũ nĩyonaga gwaku gwĩ kwega-rĩ,
17 kí ìwọ kí ó mú ìlu kan lu etí rẹ̀ mọ́ ara ìlẹ̀kùn, yóò sì di ẹrú rẹ láéláé. Bẹ́ẹ̀ náà ni kí o ṣe sí ìránṣẹ́ ẹrúbìnrin rẹ.
hĩndĩ ĩyo nĩũgakĩnyiita mũkuha, ũmĩtũrĩkie gũtũ ĩrĩ hau mũrango-inĩ, ĩtuĩke ndungata yaku mũtũũrĩre wayo wothe. Ũguo noguo ũgeeka ndungata yaku ya mũndũ-wa-nja.
18 Má ṣe kà á sí ohun ìnira láti dá ẹrú rẹ sílẹ̀, nítorí ìsìnrú rẹ̀ fún ọ, ní ọdún mẹ́fà náà tó ìlọ́po méjì iṣẹ́ alágbàṣe, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún fún ọ nínú gbogbo ìdáwọ́lé rẹ.
Ndũkone taarĩ ũndũ ũrĩ hinya kũrekereria ndungata yaku ĩthiĩ, nĩ ũndũ ũtungata ũrĩa ĩgũtungatĩire mĩaka ĩyo ĩtandatũ nĩ ta maita meerĩ ma mũcaara wa mũndũ wa kwandĩkwo. Nake Jehova Ngai waku nĩarĩkũrathimaga maũndũ-inĩ mothe marĩa ũrĩĩkaga.
19 Gbogbo àkọ́bí tí o jẹ́ akọ nínú agbo màlúù rẹ ni kí o yà sọ́tọ̀ fún Olúwa, àti nínú agbo ewúrẹ́ bákan náà. Ẹ má ṣe fi àkọ́bí màlúù yín ṣiṣẹ́ rárá. Má ṣe rẹ́ irun àkọ́bí àgùntàn rẹ pẹ̀lú.
Rutagĩra Jehova Ngai waku marigithathi mothe ma njamba kuuma ndũũru-inĩ ciaku cia ngʼombe na cia mbũri. Ndũkanatware marigithathi maku ma ndegwa wĩra-inĩ, na ndũkanamure marigithathi maku ma ngʼondu guoya.
20 Ní ọdọọdún ni kí ìwọ àti ìdílé rẹ máa jẹ ẹ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín níbi tí Òun yóò yàn.
O mwaka, wee na andũ a nyũmba yaku nĩmũgacirĩĩagĩra mbere ya Jehova Ngai waku handũ harĩa agaathuura.
21 Bí ẹran ọ̀sìn kan bá ní àbùkù: bóyá ó yarọ, tàbí fọ́jú, tàbí tí ó ní èyíkéyìí àbùkù tó burú. Ẹ kò gbọdọ̀ fi rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run yín.
Nyamũ ĩngĩgakorwo ĩrĩ na kaũũgũ, ĩkorwo ĩgĩthua kana ĩrĩ ndumumu, kana ĩkorwo na ũũgũ o na ũrĩkũ-rĩ, mũtikanamĩrutĩre Jehova Ngai wanyu igongona.
22 Ẹ jẹ ẹ́ ní ìlú u yín. Àti ẹni tí a kà sí mímọ́ àti aláìmọ́ ni ó lè jẹ ẹ́ bí ìgbà tí a ń jẹ èsúró tàbí àgbọ̀nrín.
Mũkaamĩrĩĩra o kũu matũũra-inĩ manyu. No ĩrĩĩo nĩ arĩa marĩ na thaahu na arĩa matarĩ na thaahu, o taarĩ thiiya kana thwariga maraarĩa.
23 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀, ẹ dà á síta bí omi.
No mũtikarĩĩage thakame; mĩitagei thĩ o ta maaĩ.

< Deuteronomy 15 >