< Deuteronomy 15 >

1 Ní òpin ọdún méje méje, ẹ̀yin gbọdọ̀ máa yọ̀ǹda àwọn gbèsè.
Saning sarihto boeng kruek, laiba tahmen oh.
2 Báyìí ni kí ẹ máa ṣe é. Gbogbo ẹni tí wọ́n jẹ ní gbèsè gbọdọ̀ fojú fo gbèsè tí ó ti yá ará Israẹli ènìyàn rẹ̀. Kò gbọdọ̀ béèrè ohun náà, lọ́dọ̀ ará Israẹli ènìyàn rẹ̀ tàbí lọ́dọ̀ arákùnrin rẹ̀: nítorí pé a ti kéde àkókò Olúwa láti fojú fo gbèsè.
Laiba tahmenhaih loklam loe hae tiah sah oh; Angraeng mah laiba tahmenhaih ni, tiah taphong ih atue ah oh pongah, phoisa coi kami mah a imtaeng kami hanah coisak ih phoisa loe azom ah ohsak han oh; a imtaeng kami khaeah maw, to tih ai boeh loe angmah ih nawkamyanawk khaeah maw, laiba to suk mak ai boeh.
3 Ẹ lè béèrè ìsanpadà lọ́dọ̀ àjèjì. Ṣùgbọ́n ẹ fa igi lé gbèsè yówù kó jẹ́ tí arákùnrin yín jẹ yín.
Prae kalah kaminawk khaeah loe, laiba to na suk o thaih; toe nam nawkamya khaeah loe laiba to azom ah ni om tih boeh;
4 Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí yóò tọ́ sí nínú yín, nítorí pé Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín lọ́pọ̀lọ́pọ̀ nínú ilẹ̀ náà tí ó ń mú un yín lọ láti gbà bí ìní yín.
na Angraeng Sithaw mah qawktoep hanah paek ih prae thungah, paroeai tahamhoihaih na hnuk o pongah, to tiah na sak o nahaeloe, nangcae salakah kamtang kami to om mak ai.
5 Kìkì bí ẹ bá gbọ́rọ̀ sí àṣẹ Olúwa Ọlọ́run yín tí ẹ sì kíyèsára láti máa rìn nínú gbogbo àṣẹ wọ̀nyí, tí èmi ń pa fún un yín lónìí.
Vaihniah kang paek o ih loknawk hae pazui moe, na sak o hanah, na Angraeng Sithawh ih lok to tahngai oh.
6 Nítorí pé Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín bí ó ti ṣèlérí, ẹ̀yin yóò sì máa yá ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ẹ kì yóò sì tọrọ. Ẹ ó ṣàkóso ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè, ṣùgbọ́n kò sí orílẹ̀-èdè tí yóò lè jẹ ọba lé e yín lórí.
A lokkam ih baktih toengah, na Angraeng Sithaw mah tahamhoihaih na paek o ueloe, paroeai prae kalah kaminawk to na coi o sak tih; toe nangcae loe mi khaeah doeh na coi o mak ai; kapop parai prae kaminawk to na uk o tih; toe nangcae loe mi mah doeh na uk o mak ai.
7 Bí tálákà kan bá wà láàrín àwọn arákùnrin yín ní èyíkéyìí àwọn ìlú, ilẹ̀ náà tí Olúwa yín yóò fún un yín. Ẹ má ṣe ṣe àìláàánú, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má ṣe háwọ́ sí arákùnrin yín tí ó jẹ́ tálákà.
Na Angraeng Sithaw mah nangcae khaeah paek ih prae ah kaom, na vangpui thungah kamtang nam nawkamyanawk maeto om nahaeloe, a nuiah palung thahsak hmah loe, nam nawkamya nuiah ban to tamuep o hmah;
8 Ṣùgbọ́n ẹ lawọ́ kí ẹ sì fi tọkàntọkàn yá wọn ní ohun tí wọ́n nílò.
a nuiah na ban kuuhoih o sak loe, anih angaihaih baktih toengah, anih angaih zetto azom ah coi o sak ah.
9 Ẹ ṣọ́ra kí èrò búburú kan má ṣe sí nínú àyà rẹ wí pé, “Ọdún keje tí í ṣe ọdún ìyọ̀ǹda gbèsè ti súnmọ́,” nípa bẹ́ẹ̀, ojú rẹ a sì burú sí arákùnrin rẹ tálákà, tí ìwọ kò sì fun ní nǹkan, o kò sì fun ní nǹkan kan. Òun a si kígbe pe Olúwa nítorí rẹ, a si di ẹ̀ṣẹ̀ fún ọ.
Hae baktih kasae poekhaih na tawnh o han ai ah acoe oh; saning sarihto boenghaih, laiba tahmenhaih atue loe zoi boeh, tiah na panoek o naah, kamtang kami nam nawkamya nuiah kasae poekhaih na tawnh o moe, anih han tidoeh na paek o ai, to naah anih mah Angraeng Sithaw khaeah na nuiah palung hoih aihaih hoiah lawkthui nahaeloe, na nuiah zaehaih om tih.
10 Fún un tọkàntọkàn, láìsí ìkùnsínú, nítorí èyí, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún fún ọ nínú iṣẹ́ ọwọ́ rẹ, àti gbogbo ìdáwọ́lé rẹ.
Anih han palung tang hoi paek ah, anih paek hanah hmuen paawthaih to tawn hmah; to tiah na sak nahaeloe na sak ih hmuen nuiah, Angraeng Sithaw mah, na toksakhaih boih ah maw, na ban hoi sui ih hmuennawk boih nuiah maw tahamhoihaih to paek tih.
11 A kò lè fẹ́ tálákà kù ní ilẹ̀ náà ní ìgbà gbogbo, mo pàṣẹ fún un yín láti lawọ́ sí àwọn arákùnrin yín, sí àwọn tálákà àti sí àwọn aláìní, ní ilẹ̀ ẹ yín.
Amtang kaminawk loe natuek naah doeh prae thung hoiah boeng o mak ai; to pongah na prae thungah kaom, nam nawkamya nui hoi kamtang moe, kavawt kaminawk khaeah na ban kuuhoih o sak ah.
12 Bí Heberu ara yín kan, yálà ọkùnrin tàbí obìnrin bá ta ara rẹ̀ fún ọ, tí ó sì sìn ọ́ fún ọdún mẹ́fà. Ní ọdún keje, jẹ́ kí ó di òmìnira.
Hebrai kami nongpa maw, to tih ai boeh loe nongpata maw, kami maeto nang khaeah zawh, anih mah na tok to saning tarukto thungah na sah pae boeh nahaeloe, saning sarihto naah loe anih to loisak ah.
13 Nígbà tí ó bá dá a sílẹ̀ má ṣe jẹ́ kí ó lọ lọ́wọ́ òfo.
Anih na loihsak naah, anih to bankrai ah caehsak hmah.
14 Fi tọkàntọkàn fún un láti inú agbo ewúrẹ́ rẹ, ilẹ̀ ìpakà rẹ, àti ibi ìfúntí rẹ. Fún un gẹ́gẹ́ bí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti bùkún fún ọ tó.
Anih na loihsak naah, na tawnh ih tuunawk, na hak ih cangnawk hoi na pasawh ih misurtuinawk to koeh zetto paawt ai ah phawsak ah; na Angraeng Sithaw mah tahamhoihaih paek baktih toengah, anih han doeh paek toeng ah.
15 Ẹ rántí pé ẹ ti fi ìgbà kan jẹ́ ẹrú ní Ejibiti, Olúwa Ọlọ́run yín sì rà yín padà, ìdí nìyí tí mo fi pa àṣẹ yìí fún un yín lónìí.
Izip prae thungah misong ah na oh o naah, Angraeng mah ang pahlong o, tito panoek oh; to pongah vaihniah hae loknawk hae kang paek o.
16 Ṣùgbọ́n bí ìránṣẹ́ rẹ bá sọ fún ọ pé, “Èmi kò fẹ́ fi ọ́ sílẹ̀,” nítorí pé ó fẹ́ràn ìwọ àti ìdílé rẹ, tí ó sì tẹ́ ọ lọ́rùn,
Toe na tamna mah nangmah hoi na imthung takohnawk to palung moe, nang khaeah khosak loe hoih, tiah poek pongah, nang khaeah, Tacawt han ka koeh ai, tiah thui nahaeloe,
17 kí ìwọ kí ó mú ìlu kan lu etí rẹ̀ mọ́ ara ìlẹ̀kùn, yóò sì di ẹrú rẹ láéláé. Bẹ́ẹ̀ náà ni kí o ṣe sí ìránṣẹ́ ẹrúbìnrin rẹ.
sum kamsum to la ah loe, thok taengah anih ih naa to taqawt paeh; to pacoengah anih loe a hing thung na tamna ah om tih boeh; tamna nongpata doeh, to tiah sah ah.
18 Má ṣe kà á sí ohun ìnira láti dá ẹrú rẹ sílẹ̀, nítorí ìsìnrú rẹ̀ fún ọ, ní ọdún mẹ́fà náà tó ìlọ́po méjì iṣẹ́ alágbàṣe, Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò bùkún fún ọ nínú gbogbo ìdáwọ́lé rẹ.
Na misong loisakhaih to karai parai hmuen ah poek hmah; saning tarukto thung anih mah nang hanah ang sak pae ih tok loe, kami na tlai moe, saksak ih tok pongah, alet hnetto kamtlai ah hoih kue; to tiah na sak nahaeloe toksakhaih boih ah na Angraeng Sithaw mah tahamhoihaih na paek tih.
19 Gbogbo àkọ́bí tí o jẹ́ akọ nínú agbo màlúù rẹ ni kí o yà sọ́tọ̀ fún Olúwa, àti nínú agbo ewúrẹ́ bákan náà. Ẹ má ṣe fi àkọ́bí màlúù yín ṣiṣẹ́ rárá. Má ṣe rẹ́ irun àkọ́bí àgùntàn rẹ pẹ̀lú.
Tapen tangsuek maitaw hoi tuu caa to na Angraeng Sithaw hanah pahoe ah; tapen tangsuek maitaw caa to laikok atok han patoh hmah; tapen tangsuek tuu to amui aat hmah.
20 Ní ọdọọdún ni kí ìwọ àti ìdílé rẹ máa jẹ ẹ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín níbi tí Òun yóò yàn.
Angraeng mah qoih ih ahmuen ah, na Angraeng Sithaw hmaa ah, nangmah hoi na imthung takoh boih, saning kruek maitaw hoi tuu caa moi to caa oh.
21 Bí ẹran ọ̀sìn kan bá ní àbùkù: bóyá ó yarọ, tàbí fọ́jú, tàbí tí ó ní èyíkéyìí àbùkù tó burú. Ẹ kò gbọdọ̀ fi rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run yín.
Maitaw hoi tuu loe coek koiah oh; khokkhaem maw, to tih ai boeh loe mikmaeng moe, coek koi om nahaeloe, na Angraeng Sithaw khaeah angbawnhaih ah paek hmah.
22 Ẹ jẹ ẹ́ ní ìlú u yín. Àti ẹni tí a kà sí mímọ́ àti aláìmọ́ ni ó lè jẹ ẹ́ bí ìgbà tí a ń jẹ èsúró tàbí àgbọ̀nrín.
Moi to nangmacae khongkha thungah caa oh; kaciim doeh kaciim ai kami doeh, tasuk hoi sakhi moi caak baktih toengah caak thaih.
23 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀, ẹ dà á síta bí omi.
Toe athii loe caa o hmah; tui baktiah long ah krai oh.

< Deuteronomy 15 >