< Daniel 9 >

1 Ní ọdún kìn-ín-ní Dariusi ọmọ Ahaswerusi, ẹni tí a bí ní Media, òun ló jẹ ọba lórí ìjọba Babeli.
Khalden ram ah aka manghai Madai tiingan lamkah Ahasuerus capa Darius kah kum khat dongah om coeng.
2 Ní ọdún kìn-ín-ní ìjọba rẹ̀, èmi Daniẹli fi iyè sí i láti inú ìwé, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa tí wòlíì Jeremiah, wá pé, àádọ́rin ọdún ni Jerusalẹmu yóò fi wà ní ahoro.
Kum sawmrhih vaengah Jerusalem imrhong la a om ham BOEIPA loh tonghma Jeremiah taengah ol a paek bangla kum kah a tarhing tah a manghai nah kum khat vaengah kai Daniel loh cabu rhangneh ka yakming.
3 Nígbà náà, ni mo yípadà sí Olúwa Ọlọ́run, mo bẹ̀ ẹ́ pẹ̀lú àdúrà àti ẹ̀bẹ̀, pẹ̀lú àwẹ̀, aṣọ ọ̀fọ̀ àti eérú.
Te dongah Pathen tlap hamla thangthuinah, huithuinah, yaehnah, tlamhni, hmaiphu neh ka Boeipa taengla ka maelhmai te ka hoi.
4 Mo gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run mi, mo sì jẹ́wọ́ wí pé: “Ìwọ Olúwa, Ọlọ́run tí ó tóbi, tí ó sì ní ẹ̀rù, ẹni tí ń pa májẹ̀mú ìfẹ́ mọ́, pẹ̀lú àwọn tí ó ní ìfẹ́ rẹ̀ àti àwọn tí ó ń pa àwọn òfin rẹ̀ mọ́.
Ka Pathen BOEIPA taengah ka thangthui neh ka phoe tih, “Ka Boeipa aw Pathen tah boeilen tih a rhih om pai. Paipi te a ngaithuen dongah amah aka lungnah taeng neh a olpaek aka ngaithuen taengah sitlohnah a khueh.
5 Àwa ti ṣẹ̀, a sì ti ṣe búburú. Àwa ti hu ìwà búburú, a sì ti ṣe ọ̀tẹ̀, a ti yí padà kúrò nínú àwọn àṣẹ àti àwọn ìlànà rẹ̀.
Ka tholh uh tih ka paihaeh uh dongah ka boe rhoe ka boe uh coeng. Kan tloelh uh tih na olpaek lamkah neh na laitloeknah lamloh ka nong uh coeng.
6 Àwa kò fetí sí àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ, ẹni tí ó sọ̀rọ̀ ní orúkọ rẹ sí àwọn ọba wa, àwọn ọmọ-aládé àti àwọn baba wa, àti sí gbogbo ènìyàn ilẹ̀ náà.
Namah sal tonghma ol te ka hnatun uh moenih. Te rhoek loh namah ming neh ka manghai rhoek, ka mangpa, a pa rhoek taengah khaw khohmuen pilnam boeih taengah khaw a thui uh coeng.
7 “Olúwa ìwọ ni olódodo, ṣùgbọ́n báyìí ìtìjú dé bá àwọn ènìyàn Juda, àwọn ènìyàn Jerusalẹmu àti gbogbo Israẹli ní gbogbo orílẹ̀-èdè tí ìwọ ti fọ́n wa ká sí nítorí àìṣòótọ́ ọ wa sí ọ.
Duengnah he ka Boeipa nang kah ni. Tedae tihnin kah bangla maelhmai yahpohnah he kaimih taengah khaw, Judah hlang taengah khaw, Jerusalem khosa rhoek taengah khaw, Israel boeih taengah khaw, diklai pum kah a yoei a hla taengah om coeng. Amamih kah boekoeknah dongah nang taengah boe a koek vangbangla teah amih pahoi na heh coeng.
8 Háà! Olúwa, àwa àti àwọn ọba wa, àwọn ọmọ-aládé, àti àwọn baba wa, ìtìjú dé bá wa nítorí àwa ti dẹ́ṣẹ̀ sí ọ.
BOEIPA aw namah taengah ka tholh uh dongah kaimih ham tah maelhmai kah yahpohnah he ka manghai rhoek taeng neh ka mangpa rhoek taengah khaw, a pa rhoek taengah khaw om.
9 Olúwa Ọlọ́run wa ní àánú, ó sì ń dáríjì, bí àwa tilẹ̀ ti ṣe ọ̀tẹ̀ sí i;
Amah te ka tloelh lalah khaw ka Boeipa tah kaimih ham haidamnah neh khodawkngainah Pathen la om.
10 àwa kò gbọ́rọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run wa, a kò sì pa àwọn òfin rẹ mọ́, èyí tí ó fún wa nípasẹ̀ àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ̀.
A sal tonghma rhoek kut lamloh kaimih mikhmuh ah m'paek a olkhueng dongah pongpa ham kaimih kah Pathen BOEIPA ol te ka hnatun uh moenih.
11 Gbogbo Israẹli ti ṣẹ̀ sí òfin rẹ, wọ́n ti yípadà kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ, wọ́n kọ̀ láti ṣe ìgbọ́ràn sí ọ. “Nígbà náà ni ègún àti ìdájọ́ tí a kọ sílẹ̀ pẹ̀lú ìbúra nínú òfin Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run dà sórí i wa, nítorí tí àwa ti sẹ̀ sí ọ.
Israel pum long khaw na olkhueng te a poe uh tih a taengphael dongah na ol te hnatun uh pawh. A taengah ka tholh uh dongah ni Pathen kah Sal Moses olkhueng khuiah a daek bangla thaephoeinah neh olhlo te kaimih soah nan hawk.
12 Ìwọ ti mú ọ̀rọ̀ tí o sọ sí wa sẹ àti lórí àwọn alákòóso wa, nípa mímú kí ibi ńlá bá wa, irú èyí tí kò tí ì ṣẹlẹ̀ rí lábẹ́ ọ̀run, bí ó ti ṣẹlẹ̀ sí Jerusalẹmu yìí.
Te phoeiah a ol tah a ol bangla a thoh coeng. Te te kaimih taeng neh kaimih kah laitloek rhoek taengah a thui coeng. Kaimih sokah lai aka tloek loh kaimih soah yoethae a len hang khuen. Te dongah Jerusalem kah a saii bang te vaan boeih kah a hmuiah a saii noek moenih.
13 Bí a ti kọ ọ́ sínú òfin Mose bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ibi yìí ti dé bá wa, síbẹ̀ a kò bẹ̀bẹ̀ fún ojúrere Olúwa Ọlọ́run wa, nípa yíyí padà kí a kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ wa kí a sì mọ òtítọ́ rẹ.
Moses kah olkhueng dongah a daek bangla yoethae cungkuem he kaimih soah pai coeng. Tedae kaimih kah thaesainah lamloh mael ham neh na oltak dongah cangbam ham kaimih kah Pathen BOEIPA mikhmuh ah ka kothae uh pawh.
14 Olúwa kò jáfara láti mú ibi náà wá sórí wa, nítorí olódodo ni Olúwa Ọlọ́run wa nínú u gbogbo ohun tí ó ń ṣe; síbẹ̀ àwa kò ṣe ìgbọ́ràn sí i.
BOEIPA loh yoethae kawng dongah hak tih te te kaimih soah a pai sak. Ka Pathen BOEIPA loh a bibi boeih dongah a dueng la a saii dae a ol te ka hnatun uh moenih.
15 “Ní ìsinsin yìí, Olúwa Ọlọ́run wa, ẹni tí ó mú àwọn ènìyàn rẹ̀ jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá, pẹ̀lú ọwọ́ agbára, tí ó fún ara rẹ̀ ní orúkọ tí ó wà títí di òní, a ti ṣẹ̀, a sì ti ṣe búburú.
Ka Boeipa neh kaimih kah Pathen aw, na pilnam te Egypt khohmuen lamloh tlungluen kut neh na khuen. Tahae khohnin kah bangla namah ming ham na saii dongah ka tholh uh tih ka boe uh coeng.
16 Olúwa, ní ìbámu pẹ̀lú ìwà òdodo rẹ, yí ìbínú àti ìrunú rẹ padà kúrò ní Jerusalẹmu ìlú u rẹ, òkè mímọ́ rẹ. Ẹ̀ṣẹ̀ wa àti àìṣedéédéé àwọn baba wa ti mú Jerusalẹmu àti ènìyàn rẹ di ẹ̀gàn fún gbogbo àwọn tí ó yí wọn ká.
Ka Boeipa aw, na duengnah loh a cungkuem bangla na thintoek neh na kosi te na tlang cim neh na khopuei Jerusalem lamloh mael laeh saeh. Kaimih kah tholhnah dong neh a pa rhoek kah thaesainah dongah ni Jerusalem neh na pilnam ka kaepvai boeih taengah kokhahnah la a om.
17 “Nísinsin yìí, Ọlọ́run wa, gbọ́ àdúrà àti ẹ̀bẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ, nítorí i tìrẹ Olúwa, fi ojú àánú wo ibi mímọ́ rẹ tí ó ti dahoro.
Kaimih kah Pathen aw na sal kah thangthuinah neh a huithuinah he hnatun laeh. Na rhokso dingrhak soah khaw ka Boeipa hamla na maelhmai sae sak.
18 Tẹ́ etí rẹ sílẹ̀, Ọlọ́run, kí o gbọ́; ya ojú rẹ sílẹ̀, kí o sì wo ìdahoro ìlú tí a ń fi orúkọ rẹ pè. Àwa kò gbé ẹ̀bẹ̀ wa kalẹ̀ níwájú u rẹ nítorí pé a jẹ́ olódodo, bí kò ṣe nítorí àánú ńlá rẹ.
Ka Pathen aw na hna te kaeng lamtah han ya lah, na mik te dai rhoe dai lamtah kaimih neh khopuei a pong he hmu lah. Te te na ming la a khue dae ta. Na mikhmuh ah ka huithuinah kan tloeng he kaimih kah duengnah dongah pawt tih na haidamnah a yet dongah ni.
19 Olúwa, fetísílẹ̀! Olúwa, dáríjì! Olúwa, gbọ́ kí o sì ṣe é! Nítorí i tìrẹ, Ọlọ́run mi, má ṣe pẹ́ títí, nítorí ìlú rẹ àti àwọn ènìyàn rẹ ń jẹ́ orúkọ mọ́ ọ lára.”
Ka Boeipa hnatun dae, ka Boeipa khodawkngai dae, ka Boeipa hnatung dae. Ka Pathen namah ham uelh mueh la saii laeh. Na ming he na khopuei ham neh na pilnam ham ni a khue.
20 Bí mo ṣe ń sọ̀rọ̀, tí mo sì ń gba àdúrà, tí mo ń jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi àti ẹ̀ṣẹ̀ àwọn Israẹli ènìyàn mi, tí mo sì ń mú ẹ̀bẹ̀ mi tọ Olúwa Ọlọ́run mi nítorí òkè mímọ́ rẹ.
Ka thui li vaengah ka thangthui neh, ka tholhnah khaw, ka pilnam Israel kah tholhnah khaw ka phoe. Te phoeiah ka Pathen kah hmuencim tlang ham ka Pathen BOEIPA mikhmuh ah ka lungmacil loh koep.
21 Bí mo ṣe ń gba àdúrà náà lọ́wọ́, Gabrieli ọkùnrin tí mo rí nínú ìran ìṣáájú, yára kánkán wá sí ọ̀dọ̀ mi ní àkókò ẹbọ àṣálẹ́.
Thangthuinah neh ka thui li vaengah Gabriel hlang te lamhma kah mangthui neh ka hmuh. Anih te ding la ha ding tih hlaem kah khocang tue vaengah kai taengah ha pai.
22 Ó jẹ́ kí ó yé mi, ó sì wí fún mi pé, “Daniẹli, mo wá láti jẹ́ kí o mọ̀ kí o sì ní òye.
A thuicaih tih kamah m'voek vaengah, “Daniel nang te yakmingnah neh cangbam ham ka lo coeng.
23 Bí o ṣe bẹ̀rẹ̀ sí nígbà àdúrà, a fún ọ ní ìdáhùn kan, èyí tí mo wá láti sọ fún ọ, nítorí ìwọ jẹ́ àyànfẹ́ gidigidi. Nítorí náà, gba ọ̀rọ̀ náà yẹ̀ wò kí ìran náà sì yé ọ:
Na huithuinah a moe vaengah ol ha pai. Te dongah nang kah sanaep te thui hamla ka lo. Te dongah ol te yakming lamtah a hmuethma te khaw yakming laeh.
24 “Àádọ́rin ọ̀sẹ̀ ni a pàṣẹ fún àwọn ènìyàn rẹ àti fún àwọn ìlú mímọ́ rẹ láti parí ìrékọjá, láti fi òpin sí ẹ̀ṣẹ̀, láti ṣe ètùtù sí ìwà búburú, láti mú òdodo títí ayé wá, láti ṣe èdìdì ìran àti wòlíì àti láti fi òróró yan Ibi Mímọ́ Jùlọ.
Na pilnam ham neh na hmuencim khopuei ham a yalh sawmrhih tloek pah. A boekoeknah bawt sak ham neh catui hnah ham khaw, tholhnah boirhaem cing sak ham neh thaesainah te dawth pah ham khaw, kumhal duengnah khuen ham neh mangthui te catui hnah ham khaw, tonghma neh hmuencim kah hmuencim koelh ham khaw om coeng.
25 “Nítorí náà, mọ èyí pé, láti ìgbà tí a ti gbé ọ̀rọ̀ náà jáde wí pé kí a tún Jerusalẹmu ṣe, kí a sì tún kọ́, títí dé ìgbà ọmọ-aládé, ẹni òróró náà, alákòóso wa yóò fi dé, ó jẹ́ ọ̀sẹ̀ méje àti ọ̀sẹ̀ méjìlélọ́gọ́ta, a ó sì tún ìgboro àti yàrá rẹ̀ mọ, ṣùgbọ́n ní àkókò wàhálà ni.
Te dongah ming lamtah Jerusalem thoh ham neh sak hamla ol aka thoeng te cangbam laeh. A koelh rhaengsang hil yalh rhih neh yalh sawmrhuk panit khuiah toltung neh imhlai khaw a thoh vetih a sak suidae khobing tue la om ni.
26 Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjìlélọ́gọ́ta, a ó ké Ẹni òróró náà kúrò, kò sì ní ní ohun kan. Àwọn ènìyàn ọmọ-aládé náà tí yóò wá ni yóò pa ìlú náà àti ibi mímọ́ run. Òpin yóò dé bí ìkún omi, ogun yóò máa jà títí dé òpin, a sì ti pàṣẹ ìdahoro.
Yalh sawmrhuk panit hnuk lamtah a koelh te a hnawt vetih anih te om voel mahpawh. Pilnam rhaengsang aka pai loh khopuei neh hmuencim te a phae ni. Anih bawtnah tah lungpook bangla caemtloek a bawt hil cu tih pong.
27 Yóò sì fi ìdí i májẹ̀mú kan múlẹ̀ pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ fún ọ̀sẹ̀ kan. Ní àárín ọ̀sẹ̀ ni yóò mú òpin bá ẹbọ àti ọrẹ ẹbọ. Àti lórí apá kan ni yóò dà ìríra tí ó mú ìdahoro wá, títí tí òpin tí a ti pàṣẹ lórí asọnidahoro yóò fi padà fi dé bá a.”
Paipi te a yet neh yalh khat a len sak ni. Tedae yalh rhakthuem vaengah hmueih neh khocang a paa sak ni. Te vaengah a phae dongkah sarhingkoi te a boeinah hil a pong sak. Te phoeiah a tloek bangla aka pong soah a hawk

< Daniel 9 >