< Daniel 7 >

1 Ní ọdún àkọ́kọ́ Belṣassari ọba Babeli, Daniẹli lá àlá kan, ìran náà sì wá sí ọkàn an rẹ̀ bí ó ṣe sùn sórí ibùsùn un rẹ̀, ó sì kọ àlá náà sílẹ̀.
Na rĩrĩ, mwaka-inĩ wa mbere wa Belishazaru mũthamaki wa bũrũri wa Babuloni, Danieli nĩarootire kĩroto, na akĩona cioneki meciiria-inĩ make akomete ũrĩrĩ-inĩ wake. Nake akĩandĩka ũhoro wa kĩroto kĩu.
2 Daniẹli sọ pé, “Nínú ìran mi lóru mo wò ó, mo sì rí afẹ́fẹ́ ọ̀run mẹ́rin tí ó ń ru omi Òkun ńlá sókè.
Danieli akiuga atĩrĩ: “Niĩ Danieli-rĩ, ũtukũ nĩndonire kĩoneki, na hau mbere yakwa ngĩona huho inya cia igũrũ ikĩhurutanĩra igũrũ wa iria rĩrĩa inene.
3 Ẹranko ńlá mẹ́rin tí ó yàtọ̀ sí ara wọn, jáde láti inú Òkun náà.
Naho hau hakiumĩra nyamũ inya ciarĩ nene kuuma iria-inĩ rĩu, na gũtirĩ yahanaga ĩrĩa ĩngĩ.
4 “Ẹranko kìn-ín-ní dàbí i kìnnìún, ó sì ní ìyẹ́ apá a idì, mo sì wò títí a fi fa ìyẹ́ apá rẹ̀ náà tu, a sì gbé e sókè kúrò ní ilẹ̀, a mú kí ó fi ẹsẹ̀ dúró bí ènìyàn, a sì fi àyà ènìyàn fún un.
“Nyamũ ya mbere yahaanaga ta mũrũũthi, na yarĩ na mathagu ta ma ndiiyũ. Ngĩikara ndorete nginya rĩrĩa njoya ciayo ciamunyirwo, nayo ĩgĩcooka ĩkĩoywo na igũrũ ĩkĩrũgamio na magũrũ mayo meerĩ ta mũndũ, na ĩkĩheo ngoro ta ya mũndũ.
5 “Mo sì tún rí ẹranko kejì, ó rí bí irú ẹranko ńlá beari kan tí ó ń gbé ilẹ̀ òtútù; o gbé ara sókè ní apá kan, ó sì ní egungun ìhà mẹ́ta láàrín ẹ̀yìn in rẹ̀, wọ́n sì sọ fún un pé, ‘Dìde kí o sì jẹ ẹran tó pọ̀!’
“Na hau mbere yakwa nĩ haarĩ na nyamũ ĩngĩ ya keerĩ, nayo yahaanaga ta nduba. Nayo nyamũ ĩyo nĩyambararĩtie mwena ũmwe wayo, na ĩkarũma mbaru ithatũ na kanua gatagatĩ ka magego mayo. Nayo ĩkĩĩrwo atĩrĩ, ‘Ũkĩra ũrĩe nyama nginya ũiganie!’
6 “Lẹ́yìn ìgbà náà, mo tún rí ẹranko kẹta ó rí bí àmọ̀tẹ́kùn. Ẹranko náà ní ìyẹ́ bí i ti ẹyẹ ní ẹ̀yìn, ó sì ní orí mẹ́rin, a sì fún un ní agbára láti ṣe ìjọba.
“Thuutha ũcio ngĩrora na ngĩona hau mbere yakwa nyamũ ĩngĩ, nayo yahaanaga ta ngarĩ. Mũgongo-inĩ wayo yarĩ na mathagu mana maahaanaga ta ma nyoni. Nyamũ ĩyo yarĩ na mĩtwe ĩna, na nĩyahetwo ũhoti wa gwathana.
7 “Lẹ́yìn èyí, nínú ìran mi ní òru mo tún rí ẹranko kẹrin, ó dẹ́rùbà ni, ó dáyà fo ni, ó sì lágbára gidigidi. Ó ní eyín irin ńlá; ó ń jẹ, ó sì ń fọ́ túútúú, ó sì fi ẹsẹ̀ tẹ èyí tókù mọ́lẹ̀. Ó yàtọ̀ sí gbogbo àwọn ẹranko ti ìṣáájú, ó sì ní ìwo mẹ́wàá.
“Thuutha ũcio niĩ Danieli-rĩ, ũtukũ nĩndonire kĩoneki, na hau mbere yakwa ngĩona nyamũ ya kana, nayo yarĩ ya kũmakania na ya gũtua mũndũ nda, na nĩ yarĩ na hinya mũno. Nyamũ ĩyo yarĩ na magego manene ma kĩgera; na yahehenjaga na ĩgatambuura kĩrĩa yooraga, na kĩrĩa gĩatigara ĩkarangĩrĩria na magũrũ. Yarĩ na ngũũrani na nyamũ icio ingĩ cionekete mbere yayo, na yarĩ na hĩa ikũmi.
8 “Bí mo ṣe ń ronú nípa ìwo náà, nígbà náà ni mo rí ìwo mìíràn, tí ó kéré tí ó jáde wá ní àárín wọn; mẹ́ta lára àwọn ìwo ti àkọ́kọ́ sì fàtu níwájú u rẹ̀. Ìwo yìí ní ojú bí i ojú ènìyàn àti ẹnu tí ń sọ̀rọ̀ ìgbéraga.
“Rĩrĩa ndeciiragia ũhoro wa hĩa icio-rĩ, ngĩona hau mbere yakwa harĩ na rũhĩa rũngĩ, na rwarĩ rũnini, rũkĩmera gatagatĩ ka icio ingĩ; nacio hĩa ithatũ cia iria ciarĩ cia mbere ikĩmunyũka biũ, ikĩrweherera. Naruo rũhĩa rũu rwarĩ na maitho ta ma mũndũ na kanua kaaragia ndeto cia mwĩtĩĩo.
9 “Bí mo ṣe ń wò, “a gbé ìtẹ́ ọba kan kalẹ̀, ẹni ìgbàanì jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀. Aṣọ rẹ̀ funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú; irun orí rẹ̀ funfun bí òwú, ìtẹ́ ọba rẹ̀ rí bí ọwọ́ iná. Àwọn kẹ̀kẹ́ rẹ ń jó bí i iná.
“O ndorete ngĩona, “itĩ cia ũnene ikĩigwo handũ ha cio, nake Ũrĩa-Ũtũire-ho-kuuma-o-Tene agĩikarĩra gĩtĩ gĩake. Nacio nguo ciake cierũhĩte ta ira; na njuĩrĩ cia mũtwe wake ikerũha ta guoya wa ngʼondu. Gĩtĩ gĩake kĩa ũnene kĩarĩrĩmbũkaga nĩnĩmbĩ cia mwaki, namo magũrũ makĩo maarĩ ma mwaki ũgwakana.
10 Odò iná ń sàn, ó ń jáde ní iwájú rẹ̀ wá. Àwọn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rún ń ṣe ìránṣẹ́ fún un; ọ̀nà ẹgbẹẹgbàárùn-ún nígbà ẹgbàárùn-ún dúró níwájú rẹ̀. Àwọn onídàájọ́ jókòó, a sì ṣí ìwé wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀.
Rũũĩ rwa mwaki nĩ rwathereraga ruumĩte hau mbere yake. Nake agatungatĩrwo nĩ ndungata ngiri maita ngiri; na andũ ngiri ikũmi maita ngiri ikũmi makarũgama mbere yake. Igooti rĩgĩikara thĩ rĩciirithanie, namo mabuku makĩhingũrwo.
11 “Nígbà náà ni mo bẹ̀rẹ̀ sí ní wò, nítorí àwọn ọ̀rọ̀ ìgbéraga tí ìwo náà ń sọ, mo wò títí a fi pa ẹranko náà, a sì pa á run, a sì jù ú sínú iná tí ń jó.
“Ningĩ ngĩthiĩ na mbere gũcũthĩrĩria nĩ ũndũ wa ciugo cia mwĩgaatho iria rũhĩa rũu rwaragia. Ngĩikara ndorete nginya nyamũ ĩyo ĩkĩũragwo, na mwĩrĩ wayo ũkĩanangwo na ũgĩikio thĩinĩ wa mwaki ũcio wakanaga.
12 A sì gba ìjọba lọ́wọ́ àwọn ẹranko yòókù, ṣùgbọ́n a fún wọn láààyè láti wà fún ìgbà díẹ̀.
(Nyamũ icio ingĩ nĩciatuunyĩtwo ũhoti wacio wa gwathana, no nĩcietĩkĩrĩtio ciikarange muoyo kwa ihinda.)
13 “Nínú ìran mi ní òru mo wò, mo rí ẹnìkan tí ó dúró sí iwájú u mi, ó rí bí ọmọ ènìyàn, ó ń bọ̀ wá nínú àwọsánmọ̀ ọ̀run, ó ń bọ̀ wá sí ọ̀dọ̀ ẹni ìgbàanì, a sì mú u wá sí iwájú rẹ̀.
“Ningĩ-rĩ, ũtukũ nĩndonire kĩoneki, ngĩona hau mbere yakwa harĩ na mũndũ wahaanaga ta mũrũ wa mũndũ, agĩũka arĩ igũrũ rĩa matu. Nake agĩkuhĩrĩria Ũcio-Ũtũire-ho-kuuma-o-Tene na agĩtwarwo harĩa aarĩ.
14 A sì fi ìjọba, ògo àti agbára ilẹ̀ ọba fún un; gbogbo ènìyàn, orílẹ̀-èdè àti èdè gbogbo wọn wólẹ̀ fún un. Ìjọba rẹ̀, ìjọba ayérayé ni, èyí tí kò le è kọjá, ìjọba rẹ̀ kò sì le è díbàjẹ́ láéláé.
Nake akĩheo wathani, na riiri, na hinya wa gwathana; nacio iruka ciothe, na ndũrĩrĩ, na andũ a mĩario yothe makĩmũhooya. Wathani wake nĩ wathani wa gũtũũra tene na tene, na ndũgaathira, naguo ũthamaki wake ndũrĩ hĩndĩ ũkaanangwo.
15 “Ọkàn èmi Daniẹli, dàrú, ìran tí ó wá sọ́kàn mi dẹ́rùbà mí.
“Niĩ Danieli nĩndatangĩkire roho-inĩ, nacio cioneki iria ciahĩtũkĩire meciiria-inĩ makwa igĩĩthĩĩnia mũno.
16 Mo lọ bá ọ̀kan nínú àwọn tí ó dúró níbẹ̀, mo sì bi í léèrè òtítọ́ ìtumọ̀ nǹkan wọ̀nyí. “Ó sọ fún mi, ó sì túmọ̀ àwọn nǹkan wọ̀nyí fún mi:
Ngĩkuhĩrĩria ũmwe wa acio maarũngiĩ hau, ngĩmũũria andaarĩrie ma ya ũhoro ũcio wothe. “Nĩ ũndũ ũcio akĩndaũrĩra maũndũ macio mothe, akĩnjĩĩra atĩrĩ:
17 ‘Àwọn ẹranko ńlá mẹ́rin yìí, ni ìjọba mẹ́rin tí yóò dìde ní ayé.
‘Nyamũ icio inya nene nĩ mothamaki mana marĩa makaarahũka gũkũ thĩ.
18 Ṣùgbọ́n, ẹni mímọ́ ti Ọ̀gá-ògo ni yóò gba ìjọba náà, yóò sì jogún un rẹ títí láé àti títí láéláé.’
No rĩrĩ, andũ arĩa atheru a Ũrĩa-ũrĩ-Igũrũ-Mũno nĩo makaamũkĩra ũthamaki na matũũre naguo nginya tene, ĩĩ, ti-itherũ, matũũre naguo nginya tene na tene.’
19 “Nígbà náà, ni mo fẹ́ mọ ìtumọ̀ òtítọ́ ẹranko kẹrin, tí ó yàtọ̀ sí àwọn yòókù, èyí tí ó dẹ́rùba ni gidigidi, tí ó ní eyín irin àti èékánná idẹ, ẹranko tí ó ń run tí ó sì ń pajẹ, tí ó sì ń fi ẹsẹ̀ tẹ èyí tókù mọ́lẹ̀.
“Ningĩ ngĩenda kũmenya gĩtũmi kĩa nyamũ ĩyo ya kana ĩrĩa yarĩ na ngũũrani na icio ingĩ na yarĩ ya kũmakania mũno, ĩrĩ na magego mayo ma kĩgera na ndwara cia gĩcango, nyamũ ĩyo yahehenjaga na ĩgatambuuranga kĩrĩa yooraga, na ĩkarangĩrĩria na magũrũ kĩrĩa gĩatigara.
20 Bẹ́ẹ̀ ni mo sì fẹ́ mọ̀ nípa ìwo mẹ́wàá orí rẹ̀ àti nípa ìwo yòókù tí ó jáde, nínú èyí tí mẹ́ta lára wọn ṣubú, ìwo tí ó ní ojú, tí ẹnu rẹ̀ ń sọ̀rọ̀ ìgbéraga.
O na ningĩ ngĩenda kũmenya ũhoro wa hĩa icio ikũmi ciarĩ mũtwe wayo na wa rũhĩa rũu rũngĩ rwacookire kũmera, o na wa hĩa icio ithatũ ciamunyũkire rũu rũngĩ rwamera, menye ũhoro wa rũhĩa rũu ruonagwo ta rwarĩ rũnene gũkĩra icio ingĩ, na rwarĩ na maitho na kanua kaaragia ndeto cia mwĩgaatho.
21 Bí mo ṣe ń wò, ìwo yìí ń bá àwọn ènìyàn mímọ́ jagun, ó sì borí i wọn,
O njũũthĩrĩirie-rĩ, rũhĩa rũu rũgĩtharĩkĩra andũ arĩa atheru, rũkĩrũa nao na rũkĩmahoota,
22 títí ẹni ìgbàanì fi dé, ó sì ṣe ìdájọ́ ìdáláre fún àwọn ẹni mímọ́ Ọ̀gá-ògo, àsìkò náà sì dé nígbà tí àwọn ẹni mímọ́ náà jogún ìjọba.
o nginya rĩrĩa Ũcio-Ũtũire-ho-kuuma-o-Tene ookire na agĩtuĩra andũ acio atheru a Ũrĩa-ũrĩ-Igũrũ-Mũno ciira wa kĩhooto, narĩo ihinda rĩgĩkinya makĩĩgwatĩra ũthamaki.
23 “Ó ṣe àlàyé yìí fún mi pé, ‘Ẹranko kẹrin ni ìjọba kẹrin tí yóò wà ní ayé. Yóò yàtọ̀ sí gbogbo àwọn ìjọba yòókù yóò sì pa gbogbo ayé run, yóò tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀, yóò sì fọ́ ọ́ sí wẹ́wẹ́.
“Ningĩ akĩndaarĩria akĩnjiguithia atĩrĩ: ‘Nyamũ ĩyo ya kana nĩ ũthamaki wa kana ũrĩa ũkaagĩa gũkũ thĩ. Ũgaakorwo ũrĩ na ngũũrani na mothamaki marĩa mangĩ mothe, na nĩũkaniina thĩ yothe, ũmĩrangĩrĩrie na ũmĩhehenje.
24 Ìwo mẹ́wàá ni ọba mẹ́wàá tí yóò wá láti inú ìjọba yìí. Lẹ́yìn tí wọn ní ọba mìíràn yóò dìde, ti yóò yàtọ̀ sí tí àwọn ti ìṣáájú, yóò sì borí ọba mẹ́ta.
Nacio hĩa icio ikũmi nĩ athamaki ikũmi arĩa makoima thĩinĩ wa ũthamaki ũcio. Na thuutha wao mũthamaki ũngĩ nĩakarahũka, ũrĩ na ngũũrani na arĩa angĩ maarĩ mbere yake; na nĩagatooria athamaki acio atatũ.
25 Yóò sọ̀rọ̀ odi sí Ọ̀gá-ògo, yóò sì pọ́n ẹni mímọ́ lójú, yóò sì gbèrò láti yí ìgbà àti òfin padà. A ó fi àwọn ẹni mímọ́ lé e lọ́wọ́ fún ìgbà díẹ̀, ní ọdún méjì àti ààbọ̀.
Nĩakaaria ndeto cia gũcambia Ũrĩa-ũrĩ-Igũrũ-Mũno, na ahinyĩrĩrie andũ ake arĩa atheru, o na agerie kũgarũra mahinda na mawatho marĩa matue. Nao andũ arĩa atheru nĩmakaneanwo moko-inĩ make kwa ihinda rĩmwe, na mahinda meerĩ, na nuthu ya ihinda.
26 “‘Ṣùgbọ́n àwọn onídàájọ́ yóò jókòó, nígbà náà ni a ó gba agbára rẹ̀, a ó sì pa á rùn pátápátá títí ayé.
“‘No igooti nĩrĩgaikara thĩ rĩciirithanie, na thuutha wa ũguo acooke atunywo wathani wake, na wanangwo biũ nginya tene.
27 Nígbà náà, ni a ó gba ìjọba, agbára àti títóbi ìjọba rẹ̀ ní abẹ́ gbogbo ọ̀run, a ó sì fi fún àwọn ẹni mímọ́, àwọn ènìyàn Ọ̀gá-ògo. Ìjọba rẹ̀ yóò jẹ́ ìjọba títí ayé, gbogbo aláṣẹ ni yóò máa ṣe ìgbọ́ràn sí i, wọn yóò sì máa sìn ín.’
Ningĩ wathani, na ũhoti, na ũnene wa mothamaki marĩa marĩ gũkũ thĩ guothe cinengerwo andũ arĩa atheru, andũ a Ũrĩa-ũrĩ-Igũrũ-Mũno. Ũthamaki wake nĩ ũthamaki wa gũtũũra nginya tene na tene, nao aathani othe nĩmakamũhooyaga na mamwathĩkagĩre.’
28 “Báyìí ni àlá náà ṣe parí, ọkàn èmi Daniẹli sì dàrú gidigidi, nítorí èrò ọkàn mi yìí, ojú mi sì yípadà ṣùgbọ́n mo pa ọ̀ràn náà mọ́ ní ọkàn mi.”
“Ũhoro ũcio ũgĩthirĩra hau. Niĩ Danieli-rĩ, nĩndatangĩkire mũno meciiria-inĩ makwa, na ngĩtukia gĩthiithi, no ngĩikara ngĩĩcũũranagia ũhoro ũcio ngoro-inĩ yakwa.”

< Daniel 7 >