< Daniel 6 >

1 Ó dára lójú Dariusi láti yan ọgọ́fà àwọn baálẹ̀ sórí ìjọba,
Na rĩrĩ, Dario nĩonire athuure anene 120 nĩguo matuĩke a gwathanaga ũthamaki-inĩ wake wothe.
2 pẹ̀lú alákòóso mẹ́ta, Daniẹli sì jẹ́ ọ̀kan nínú wọn, kí àwọn baálẹ̀ lè wá máa jẹ́ ààbọ̀ fún wọn, kí ọba má ba à ní ìpalára.
Ningĩ agĩcooka akĩiga atongoria atatũ matuĩke anene a acio angĩ, na ũmwe wa acio atatũ aarĩ Danieli. Anene acio atatũ maigirwo nĩgeetha marehagĩrwo ũhoro nĩ anene acio angĩ a bũrũri, nĩgeetha indo cia mũthamaki itikoore.
3 Daniẹli ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ láàrín àwọn alákòóso àti àwọn baálẹ̀ nítorí ẹ̀mí tí ó tayọ wà lára rẹ̀ dé bi pé ọba sì ń gbèrò láti fi ṣe olórí i gbogbo ìjọba.
Nake Danieli akĩoneka arĩ wa mwanya harĩ atongoria acio angĩ othe o na anene nĩ ũndũ wa ũrĩa aarĩ kĩyo mũrutĩre-inĩ wake wa wĩra, na nĩ ũndũ ũcio mũthamaki agĩtanya kũmũtua mwathi wa ũthamaki ũcio wake wothe.
4 Nítorí èyí, gbogbo àwọn alákòóso àti àwọn baálẹ̀ ń gbèrò láti wá ẹ̀ṣẹ̀ kà sí Daniẹli lọ́rùn nínú ètò ìṣèjọba rẹ̀, ṣùgbọ́n wọn kò rí ẹ̀ṣẹ̀ kankan kà sí i lọ́rùn, wọn kò rí ìwà ìbàjẹ́ kankan tí ó ṣe, nítorí ó jẹ́ olóòtítọ́ kò sì ní ìwà ìjáfara.
Nĩ ũndũ ũcio atongoria na anene acio angĩ magĩcaria ũndũ mangĩcuukĩra Danieli wĩra-inĩ wake wa gwathana, no makĩaga ihĩtia. Nĩmagire ũndũ mangĩmũcuukĩra, tondũ aarĩ mwĩhokeku, akaaga ũcuuke kana ihĩtia mĩthiĩre-inĩ yake.
5 Nígbẹ̀yìn ni àwọn ọkùnrin wọ̀nyí sọ wí pé, “Àwa kò ní rí ìdí kankan láti kà ẹ̀ṣẹ̀ sí Daniẹli lọ́rùn, àfi èyí tí ó bá ní í ṣe pẹ̀lú òfin Ọlọ́run rẹ̀.”
Marigĩrĩrio-inĩ andũ acio makĩĩrana atĩrĩ, “Gũtirĩ hĩndĩ tũkoona ũndũ tũngĩcuukĩra Danieli, tiga ũkorirwo nĩ ũndũ ũkoniĩ watho wa Ngai wake.”
6 Nígbà náà ni àwọn alákòóso àti àwọn baálẹ̀ lọ gẹ́gẹ́ bí ikọ̀ sí ọ̀dọ̀ ọba, wọ́n wí pé, “Ìwọ Dariusi ọba, kí o pẹ́!
Nĩ ũndũ ũcio atongoria na anene a bũrũri magĩthiĩ marĩ gĩkundi kũrĩ mũthamaki, makĩmwĩra atĩrĩ: “Wee Mũthamaki Dario, ũrotũũra nginya tene!
7 Àwọn alákòóso ọba, ìjòyè, baálẹ̀, olùdámọ̀ràn, àti àwọn olórí gbìmọ̀ pọ̀ wí pé kí ọba kéde òfin kan pé ẹnikẹ́ni tí ó bá gba àdúrà sí Ọlọ́run tàbí ènìyàn kankan fún ọgbọ̀n ọjọ́, yàtọ̀ fún ìwọ ọba, a ó ju ẹni náà sí inú ihò kìnnìún.
Ithuĩ tũrĩ atongoria a ũthamaki ũyũ, na anyabara, na anene a bũrũri, na andũ arĩa mataaraga mũthamaki o na abarũthi othe, nĩtũciirĩte tũkoona arĩ wega we mũthamaki ũrute watho naguo ũhinyĩrĩrio atĩ mũndũ o wothe ũrĩa ũngĩhooya ngai o na ĩrĩkũ kana mũndũ o na ũrĩkũ, tiga akũhooire wee mũthamaki, ihinda rĩa matukũ mĩrongo ĩtatũ rĩtanathira, no nginya aikio irima-inĩ rĩa mĩrũũthi.
8 Nísinsin yìí, ìwọ ọba, gbé òfin yìí jáde, kí o sì kọ ọ́ sínú ìwé kí a má ba à yí i padà ní ìbámu pẹ̀lú òfin àwọn Media àti Persia, èyí tí kò ní le è parẹ́.”
Na rĩrĩ, wee mũthamaki, athana watho ũcio ũgĩe ho na wandĩkwo, nawe ũwĩkĩre mũhũũri nĩgeetha ndũkagarũrwo, kũringana na mawatho ma Amedi na ma Aperisia marĩa matagarũragwo.”
9 Nígbà náà, ni Dariusi ọba fi ọwọ́ sí ìwé àṣẹ náà.
Nĩ ũndũ ũcio Mũthamaki Dario akĩandĩka watho ũcio na agĩĩkĩra mũhũũri.
10 Lóòótọ́, Daniẹli mọ̀ pé a ti fi ọwọ́ sí ìwé òfin náà, síbẹ̀ ó wọ ilé e rẹ̀ lọ, nínú yàrá òkè, ó ṣí fèrèsé èyí tí ó kọjú sí Jerusalẹmu sílẹ̀. Ó kúnlẹ̀ lórí orúnkún un rẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta lójoojúmọ́, ó gbàdúrà, ó fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run gẹ́gẹ́ bí ìṣe rẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Rĩrĩa Danieli aamenyire atĩ watho ũcio nĩ wandĩkĩtwo-rĩ, akĩinũka gwake, akĩhaica kanyũmba gake ka igũrũ harĩa ndirica cia nyũmba yake ciahingũragwo irorete mwena wa Jerusalemu. O mũthenya, nĩatuuragia ndu maita matatũ akahooya Ngai, akĩmũcookagĩria ngaatho o ta ũrĩa aamenyerete gwĩka hau kabere.
11 Nígbà náà ni, àwọn ọlọ̀tẹ̀ yìí kó ara wọn jọ, wọ́n sì rí Daniẹli tí ó ń gba àdúrà, ó sì ń bẹ̀bẹ̀ fún àánú lọ́dọ̀ Ọlọ́run.
Nao andũ acio magĩthiĩ marĩ hamwe, magĩkora Danieli akĩhooya agĩthaitha Ngai amũteithie.
12 Wọ́n lọ sí iwájú ọba, wọ́n sì rán ọba létí nípa òfin tí ó ṣe pé, “Ìwọ kò ha fi ọwọ́ sí òfin wí pé ní ìwọ̀n ọgbọ̀n ọjọ́ ẹnikẹ́ni tí ó bá gba àdúrà sí Ọlọ́run tàbí ènìyàn, láì bá ṣe ìwọ ọba, a ó gbé e jù sínú ihò kìnnìún?” Ọba sì dáhùn pé, “Àṣẹ náà dúró síbẹ̀, ní ìbámu pẹ̀lú òfin àwọn ará Media àti Persia, èyí tí a kò le è parẹ́.”
Nĩ ũndũ ũcio magĩthiĩ harĩ mũthamaki na makĩaria nake igũrũ rĩa uuge ũcio wa mũthamaki: Makĩmũũria atĩrĩ, “Githĩ ndwandĩkithirie watho atĩ handũ ha matukũ mĩrongo ĩtatũ, mũndũ ũngĩhooya ngai o na ĩrĩkũ kana ahooe mũndũ o na ũrĩkũ tiga o we mũthamaki, no nginya aikio irima-inĩ rĩa mĩrũũthi?” Mũthamaki agĩcookia atĩrĩ, “Watho ũcio ũrĩ o ho, kũringana na mawatho ma Amedi na Aperisia, marĩa matagarũragwo.”
13 Nígbà náà, ni wọ́n sọ fún ọba pé, “Daniẹli, ọ̀kan lára ìgbèkùn Juda, kò ka ìwọ ọba sí, tàbí àṣẹ ẹ̀ rẹ tí o fi ọwọ́ sí. Òun sì tún ń gba àdúrà ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta lójúmọ́.”
Nao magĩcookeria mũthamaki atĩrĩ, “Danieli, ũmwe wa andũ arĩa maatahĩtwo kuuma Juda, ndagwathĩkagĩra wee mũthamaki, kana agaathĩkĩra watho ũrĩa wee mwene wandĩkithĩtie. O na rĩu no ahooyaga Ngai wake maita matatũ o mũthenya.”
14 Nígbà tí ọba gbọ́ èyí, inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi; ó pinnu láti kó Daniẹli yọ, títí oòrùn fi rọ̀, ó sa gbogbo ipá a rẹ̀ láti gba Daniẹli sílẹ̀.
Rĩrĩa mũthamaki aaiguire ũhoro ũcio, akĩigua kĩeha mũno; agĩtua itua rĩa kũhonokia Danieli, na mũthenya ũcio wothe aatindire akĩgeria ũrĩa angĩhonokia Danieli o nginya riũa rĩgĩthũa.
15 Nígbà náà, ni àwọn ọlọ̀tẹ̀ wọ̀nyí kó ara wọn jọ wá sí ọ̀dọ̀ ọba, wọ́n sì wí fún un pé, “Ìwọ ọba rántí pé, ní ìbámu pẹ̀lú òfin àwọn Media àti Persia kò sí àṣẹ tàbí ìkéde tí ọba ṣe tí a le è yí i padà.”
Hĩndĩ ĩyo andũ acio makĩũngana rĩngĩ magĩthiĩ harĩ mũthamaki na makĩmwĩra atĩrĩ, “Ririkana, wee mũthamaki, atĩ kũringana na watho wa Amedi na Aperisia, watho ũrĩa mũrute kana mwandĩke nĩ mũthamaki ndũngĩgarũrwo.”
16 Nígbà náà, ni ọba pàṣẹ, wọ́n sì mú Daniẹli, wọ́n sì sọ ọ́ sínú ihò kìnnìún. Ọba sì sọ fún Daniẹli pé, “Kí Ọlọ́run rẹ tí ìwọ ń sìn nígbà gbogbo kí ó gbà ọ́!”
Nĩ ũndũ ũcio mũthamaki agĩathana, nao makĩrehe Danieli na makĩmũikia irima-inĩ rĩa mĩrũũthi. Mũthamaki akĩĩra Danieli atĩrĩ, “Ngai waku ũrĩa ũtungatagĩra hĩndĩ ciothe-rĩ, arogũteithũra!”
17 A sì gbé òkúta kan wá, wọ́n sì fi dí ẹnu ihò náà, ọba sì dì í pa pẹ̀lú òrùka èdìdì rẹ̀ àti pẹ̀lú òrùka àwọn ọlọ́lá rẹ̀, nítorí kí a má ṣe yí ohunkóhun padà nítorí i Daniẹli.
Ihiga rĩkĩreehwo, rĩkĩigwo mũromo-inĩ wa irima rĩu, nake mũthamaki agĩĩkĩra mũhũũri na gĩcũhĩ gĩake mwene na icũhĩ cia andũ ake arĩa marĩ igweta, nĩgeetha gũtikagĩe ũndũ ũngĩgarũrwo ũkoniĩ Danieli.
18 Nígbà náà ni ọba padà sí ààfin rẹ̀, ó sì lo gbogbo òru náà láì jẹun, kò sì gbọ́ orin kankan, bẹ́ẹ̀ ni kò sì le è sùn ní òru ọjọ́ náà.
Nake Mũthamaki agĩcooka nyũmba yake ya ũthamaki, nake akĩraara ehingĩte kũrĩa irio na atarĩ na maũndũ ma gwĩkenia. Na ũtukũ ũcio wothe ndaigana kuona toro.
19 Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù, ni ọba dìde ó sì sáré lọ sí ibi ihò kìnnìún náà.
Na kwarooka gũkĩa-rĩ, mũthamaki agĩũkĩra tene, agĩthiĩ ahiũhĩte erekeire irima-inĩ rĩa mĩrũũthi.
20 Nígbà tí ó súnmọ́ ibi ihò náà ní ibi tí Daniẹli wà, ó pe Daniẹli pẹ̀lú ìtara pé, “Daniẹli, ìránṣẹ́ Ọlọ́run alààyè, ṣé Ọlọ́run rẹ tí ìwọ ń sìn tọ̀sán tòru, lè gbà ọ́ lọ́wọ́ kìnnìún bí?”
Na aakuhĩrĩria irima rĩu, agĩĩta Danieli na mũgambo ũrĩ na ruo rũnene, akĩmũũria atĩrĩ, “Danieli, wee ndungata ya Ngai ũrĩa ũrĩ muoyo, Ngai waku ũrĩa ũtungatagĩra hĩndĩ ciothe nĩakũhonoketie kuuma kũrĩ mĩrũũthi?”
21 Daniẹli sì dáhùn wí pé, “Ọba kí ẹ pẹ́!
Nake Danieli agĩcookeria mũthamaki atĩrĩ, “Wee mũthamaki, ũrotũũra nginya tene!
22 Ọlọ́run mi rán angẹli i rẹ̀, ó sì dí àwọn kìnnìún lẹ́nu. Wọn kò le è pa mí lára, nítorí a rí mi gẹ́gẹ́ bí aláìlẹ́ṣẹ̀ ní iwájú rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni èmi kò hu ìwà ìbàjẹ́ kan níwájú rẹ ìwọ ọba.”
Ngai wakwa nĩarandũmĩire mũraika wake, nake arahinga mĩrũũthi tũnua. Ndĩrĩ ũndũ mũũru ĩnjĩkĩte, tondũ nĩnyonetwo itarĩ na mahĩtia njĩkĩte maitho-inĩ make. Ningĩ o na wee mũthamaki ndirĩ ndaakũhĩtĩria.”
23 Inú ọba dùn gidigidi, ó sì pàṣẹ kí a mú Daniẹli jáde wá láti inú ihò. Nígbà tí a mú Daniẹli jáde nínú ihò, kò sí ojú ọgbẹ́ kan ní ara rẹ̀, nítorí tí ó gbẹ́kẹ̀lé Ọlọ́run rẹ̀.
Nake mũthamaki agĩkena mũno na agĩathana Danieli arutwo irima rĩu rĩa mĩrũũthi. Nake Danieli aarutwo irima-inĩ rĩu rĩa mĩrũũthi, ndaarĩ na handũ aagurarĩtio, tondũ we nĩehokete Ngai wake.
24 Ọba pàṣẹ pé, kí a mú àwọn alátakò Daniẹli wá, kí a jù wọ́n sí inú ihò kìnnìún, pẹ̀lú ìyàwó àti àwọn ọmọ wọn. Kí wọn tó dé ìsàlẹ̀ ihò, kìnnìún lágbára lórí i wọn, wọ́n sì fọ́ gbogbo egungun wọn.
Nake Mũthamaki agĩathana, akiuga atĩ andũ arĩa maathitangĩte Danieli manyiitwo, macooke marehwo na maikio irima-inĩ rĩu rĩa mĩrũũthi, hamwe na atumia ao, na ciana ciao. Na rĩrĩ, o na matanakinya irima gĩtina-rĩ, mĩrũũthi ĩyo ĩkĩmakĩria hinya, na ĩkĩhehenja mahĩndĩ mao mothe.
25 Nígbà náà ni Dariusi ọba kọ̀wé sí gbogbo ènìyàn orílẹ̀-èdè, àti gbogbo jákèjádò ilẹ̀ náà: “Kí ìre yín máa pọ̀ sí i!
Mũthamaki Dario agĩcooka akĩandĩkĩra andũ othe, na ndũrĩrĩ, na andũ a mĩario yothe bũrũri-inĩ guothe marũa, akĩmeera atĩrĩ: “Mũrogaacĩra mũno makĩria!
26 “Mo gbé àṣẹ kan jáde wí pé, ní gbogbo agbègbè ìjọba mi, gbogbo ènìyàn gbọdọ̀ bẹ̀rù, kí wọn kí ó sì bọ̀wọ̀ fún Ọlọ́run Daniẹli.
“Nĩndahĩtũkia watho, atĩ kũrĩa guothe ũthamaki ũyũ wakwa wakinya-rĩ, andũ no nginya metigagĩre na matĩĩage Ngai wa Danieli.
27 Ó ń yọ ni, ó sì ń gbani là;
Nĩwe ũteithũranaga na akahonokania;
28 Daniẹli sì ṣe rere ní àkókò ìjọba Dariusi àti àkókò ìjọba Kirusi ti Persia.
Nĩ ũndũ ũcio Danieli akĩgaacĩra hĩndĩ ya wathani wa Dario, o na wathani-inĩ wa Kurusu ũrĩa Mũperisia.

< Daniel 6 >