< Daniel 6 >

1 Ó dára lójú Dariusi láti yan ọgọ́fà àwọn baálẹ̀ sórí ìjọba,
Hina bagade Da: liase da ouligisu dunu 120 amo ea ouligisu fi amo ganodini fi dialu ouligimusa: ilegei.
2 pẹ̀lú alákòóso mẹ́ta, Daniẹli sì jẹ́ ọ̀kan nínú wọn, kí àwọn baálẹ̀ lè wá máa jẹ́ ààbọ̀ fún wọn, kí ọba má ba à ní ìpalára.
Amola e da amo ouligisu dunu boboga amo ilia hawa: hamosu amo ouligima: ne, e da Da: niele amola dunu aduna eno ilegei dagoi.
3 Daniẹli ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ láàrín àwọn alákòóso àti àwọn baálẹ̀ nítorí ẹ̀mí tí ó tayọ wà lára rẹ̀ dé bi pé ọba sì ń gbèrò láti fi ṣe olórí i gbogbo ìjọba.
Amola hina bagade, ea sodoloba, Da: niele ea hawa: hamosu da eno ouligisu ilia hawa: hamosu baligi dagoi. Amaiba: le, Da: liase da Da: niele ema Besia sogega ouligisu bisilua ilegemusa: dawa: i galu.
4 Nítorí èyí, gbogbo àwọn alákòóso àti àwọn baálẹ̀ ń gbèrò láti wá ẹ̀ṣẹ̀ kà sí Daniẹli lọ́rùn nínú ètò ìṣèjọba rẹ̀, ṣùgbọ́n wọn kò rí ẹ̀ṣẹ̀ kankan kà sí i lọ́rùn, wọn kò rí ìwà ìbàjẹ́ kankan tí ó ṣe, nítorí ó jẹ́ olóòtítọ́ kò sì ní ìwà ìjáfara.
Amalalu, ouligisu dunu eno ilia da mudale ba: i. Ilia da Da: niele amo dafama: ne adoba: su logo hogolalu. Be amo fofada: su, amo ganodini da Da: niele ea giadofai afae hame ba: i. Amola Da: niele e da moloidafa dunuba: le, ea hawa: hamosu da noga: idafa ba: i. Amola e da afae hamedafa giadofasu.
5 Nígbẹ̀yìn ni àwọn ọkùnrin wọ̀nyí sọ wí pé, “Àwa kò ní rí ìdí kankan láti kà ẹ̀ṣẹ̀ sí Daniẹli lọ́rùn, àfi èyí tí ó bá ní í ṣe pẹ̀lú òfin Ọlọ́run rẹ̀.”
Ilia ilisu amane sia: dasu, “Ninia da Da: niele ea hawa: hamosu amo ganodini giadofai hame ba: mu. Be Da: niele da Gode Ea sema amoga fa: no bobogesa. Amaiba: le, ninia da amo hou ganodini dafama: ne adoba: su hogomu da defea.”
6 Nígbà náà ni àwọn alákòóso àti àwọn baálẹ̀ lọ gẹ́gẹ́ bí ikọ̀ sí ọ̀dọ̀ ọba, wọ́n wí pé, “Ìwọ Dariusi ọba, kí o pẹ́!
Amaiba: le, ilia asili da hina bagade amo ba: la asili, ema amane sia: i, “Hina bagade, Da: liase! Di da eso huluane noga: le esalalalumu da defea!”
7 Àwọn alákòóso ọba, ìjòyè, baálẹ̀, olùdámọ̀ràn, àti àwọn olórí gbìmọ̀ pọ̀ wí pé kí ọba kéde òfin kan pé ẹnikẹ́ni tí ó bá gba àdúrà sí Ọlọ́run tàbí ènìyàn kankan fún ọgbọ̀n ọjọ́, yàtọ̀ fún ìwọ ọba, a ó ju ẹni náà sí inú ihò kìnnìún.
Ninia dia soge eagene dunu huluane, amo ninia da gilisili sia: dalu agoane sia: sa: i dagoi. Dia sema gasa bagade hamoma. Amola ninia hanai da dia dunu huluanema olelema. Dia sema agoane legema, amo eso 30 amoga, dunu huludafa da ‘gode’ huluane amola dunu huluane ilima mae sia: ne gadole esaloma: ne sia: ma. Ilia da dima fawane sia: ne gadoma: ne sia: ma. Amola dunu afaega, amo sema legebe go wadela: lisisia, dia dadi gagui dunu da amo dunu laione wa: me uli dogoi amo ganodini galagudumu, amo di sia: ne ilegema.”
8 Nísinsin yìí, ìwọ ọba, gbé òfin yìí jáde, kí o sì kọ ọ́ sínú ìwé kí a má ba à yí i padà ní ìbámu pẹ̀lú òfin àwọn Media àti Persia, èyí tí kò ní le è parẹ́.”
“Defea, hina bagade! Di amo sema ilegema amola dia dio dedema. Amalalu, amo sema da Midia amola Besia amo dunu fi ilia sema bagade ba: mu. Amola amo sema afadenemu da hamedeiwane ba: mu.
9 Nígbà náà, ni Dariusi ọba fi ọwọ́ sí ìwé àṣẹ náà.
Amalalu, Da: liase da amo sema ilegei. Ilia da sema dedene amola Da: liase da amoma gasa ima: ne ea dio dedei dagoi.
10 Lóòótọ́, Daniẹli mọ̀ pé a ti fi ọwọ́ sí ìwé òfin náà, síbẹ̀ ó wọ ilé e rẹ̀ lọ, nínú yàrá òkè, ó ṣí fèrèsé èyí tí ó kọjú sí Jerusalẹmu sílẹ̀. Ó kúnlẹ̀ lórí orúnkún un rẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta lójoojúmọ́, ó gbàdúrà, ó fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run gẹ́gẹ́ bí ìṣe rẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Da: niele da amo sema legei nababeba: le, e da wale gadole asili, ea diasuga asi. Ea diasu ganodini amo sesei gadodili dialebe ba: i. Amo ganodini fo misa: ne agenesi amo da Yelusaleme moilai bai bagadega, ga ba: legai. Ea eso huluane hou amo defele, e da muguni bugili, Godema sia: ne gadosu. E da eso afae amoga udiana agoane sia: ne gadoi.
11 Nígbà náà ni, àwọn ọlọ̀tẹ̀ yìí kó ara wọn jọ, wọ́n sì rí Daniẹli tí ó ń gba àdúrà, ó sì ń bẹ̀bẹ̀ fún àánú lọ́dọ̀ Ọlọ́run.
Da: nielema ha lai dunu da Da: niele amo Godema sia: ne gadolalebe ba: loba,
12 Wọ́n lọ sí iwájú ọba, wọ́n sì rán ọba létí nípa òfin tí ó ṣe pé, “Ìwọ kò ha fi ọwọ́ sí òfin wí pé ní ìwọ̀n ọgbọ̀n ọjọ́ ẹnikẹ́ni tí ó bá gba àdúrà sí Ọlọ́run tàbí ènìyàn, láì bá ṣe ìwọ ọba, a ó gbé e jù sínú ihò kìnnìún?” Ọba sì dáhùn pé, “Àṣẹ náà dúró síbẹ̀, ní ìbámu pẹ̀lú òfin àwọn ará Media àti Persia, èyí tí a kò le è parẹ́.”
ilia da asili, ilia hina bagadema Da: niele ea hou fofada: musa: asi. Ilia da ema amane sia: i, “Hina bagade! Dia da sema legele, dio dedei dagoi. Di da sema agoane legei, amo eso 30 amoga, dunu huludafa da ‘gode’ huluane amola dunu huluane ilima mae sia: ne gadole esaloma: ne sia: i. Ilia da dima fawane sia: ne gadoma: ne sia: i. Amola dunu afaega, amo sema legebe go wadela: lisisia, dia dadi gagui dunu da amo dunu laione wa: me uli dogoi amo ganodini galagudumu, amo di sia: i,” ilia sia: i. Amo sia: nababeba: le, hina bagade da amane sia: i, “Dafawane! Amo sema hamoi da gasa bagadedafa. Amo da Midia amola Besia ninia sema. Amola afadenemu da hamedei.”
13 Nígbà náà, ni wọ́n sọ fún ọba pé, “Daniẹli, ọ̀kan lára ìgbèkùn Juda, kò ka ìwọ ọba sí, tàbí àṣẹ ẹ̀ rẹ tí o fi ọwọ́ sí. Òun sì tún ń gba àdúrà ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta lójúmọ́.”
Amalalu, ilia da Da: liase ema amane sia: i, “Yuda mugululi asi dunu afae amo Da: niele, amo dunu e da dia sia: amo gua: ne fasi dagoi. Amola eso huluane e da ea Godema eso afaega udiana agoane sia: ne gadolala.
14 Nígbà tí ọba gbọ́ èyí, inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi; ó pinnu láti kó Daniẹli yọ, títí oòrùn fi rọ̀, ó sa gbogbo ipá a rẹ̀ láti gba Daniẹli sílẹ̀.
Hina bagade da amo sia: nababeba: le, e da da: i dioi bagade ba: i. Amola e da Da: niele gaga: musa: dawa: i galu. E da Da: nielema fidisu logo eno olelemusa: dadawa: laloba, eso sa: i.
15 Nígbà náà, ni àwọn ọlọ̀tẹ̀ wọ̀nyí kó ara wọn jọ wá sí ọ̀dọ̀ ọba, wọ́n sì wí fún un pé, “Ìwọ ọba rántí pé, ní ìbámu pẹ̀lú òfin àwọn Media àti Persia kò sí àṣẹ tàbí ìkéde tí ọba ṣe tí a le è yí i padà.”
Amola daeya agoane Da: nielema ha lai dunu da ema misini, amane sia: i, “Hina bagade! Di dawa: ! Ninia Midia fi amola Besia fi amo ninia hou amo ganodini, adi sema amo hina bagade legemusa: dawa: lalu amo sema da mae afadenene amaiwane dialumu!”
16 Nígbà náà, ni ọba pàṣẹ, wọ́n sì mú Daniẹli, wọ́n sì sọ ọ́ sínú ihò kìnnìún. Ọba sì sọ fún Daniẹli pé, “Kí Ọlọ́run rẹ tí ìwọ ń sìn nígbà gbogbo kí ó gbà ọ́!”
Amaiba: le, Da: liase da ea dadi gagui ilima ilia Da: niele afugili oule asili, laione wa: me ilia diasu dogoi amo ganodini galaguduma: ne sia: i. Amola e da Da: nielema amane sia: i, “Di da dia Gode Ea hawa: hamosu hahawane hamonana. E da di gaga: mu da defea.”
17 A sì gbé òkúta kan wá, wọ́n sì fi dí ẹnu ihò náà, ọba sì dì í pa pẹ̀lú òrùka èdìdì rẹ̀ àti pẹ̀lú òrùka àwọn ọlọ́lá rẹ̀, nítorí kí a má ṣe yí ohunkóhun padà nítorí i Daniẹli.
Ilia da Da: niele amo laione wa: me uli dogoi amogili sanasi dagoi. Amalalu ilia igi bagade afae lale logo amoga ga: si dagoi. Amola, hina bagade da ea amola ea eagene ouligisu dunu ilia gobele ilegesu liligi amo igi da: iya ado ligisi. Dunu enoga wamo Da: niele fidisa: besa: le, agoane hamoi.
18 Nígbà náà ni ọba padà sí ààfin rẹ̀, ó sì lo gbogbo òru náà láì jẹun, kò sì gbọ́ orin kankan, bẹ́ẹ̀ ni kò sì le è sùn ní òru ọjọ́ náà.
Fa: no, hina bagade da hi diasuga bu ogobele misini, amo gasi ganodini e da ha: i mae nawane esalu. Amola dunu amola uda ema hahawane sia: mae sia: ma: ne sia: i. Amola e da afae hamedafa golale ba: i.
19 Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù, ni ọba dìde ó sì sáré lọ sí ibi ihò kìnnìún náà.
Hahabedafa hina bagade da wa: legadole, hedolodafa asili, laione wa: me uli dogoiga doaga: i.
20 Nígbà tí ó súnmọ́ ibi ihò náà ní ibi tí Daniẹli wà, ó pe Daniẹli pẹ̀lú ìtara pé, “Daniẹli, ìránṣẹ́ Ọlọ́run alààyè, ṣé Ọlọ́run rẹ tí ìwọ ń sìn tọ̀sán tòru, lè gbà ọ́ lọ́wọ́ kìnnìún bí?”
Amoga: i doaga: lalu, e da beda: iwane Da: nielema amane wei, “Da: niele! Di da eso huluane esalebe Gode amo Ea noga: i hawa: hamosu dunu. Gode da di amo laione wa: mega mae gasomoma: ne di gaga: musa: defele ba: bela: ?”
21 Daniẹli sì dáhùn wí pé, “Ọba kí ẹ pẹ́!
Da: niele da laione wa: me uli dogoi ganodini esala, ema amane sia: i, “Hina bagade! Di eso huluane esalalalumu da defea.
22 Ọlọ́run mi rán angẹli i rẹ̀, ó sì dí àwọn kìnnìún lẹ́nu. Wọn kò le è pa mí lára, nítorí a rí mi gẹ́gẹ́ bí aláìlẹ́ṣẹ̀ ní iwájú rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni èmi kò hu ìwà ìbàjẹ́ kan níwájú rẹ ìwọ ọba.”
Gode Ea a: igele dunu asunasili amo misini, da laione wa: me ilia lafi ga: i. Gode da na hou amo ganodini, giadofai hame ba: beba: le, amola dima wadela: i hou hame hamoiba: le amoga E da na noga: le fidi.
23 Inú ọba dùn gidigidi, ó sì pàṣẹ kí a mú Daniẹli jáde wá láti inú ihò. Nígbà tí a mú Daniẹli jáde nínú ihò, kò sí ojú ọgbẹ́ kan ní ara rẹ̀, nítorí tí ó gbẹ́kẹ̀lé Ọlọ́run rẹ̀.
Hina bagade da hahawane bagadedafa ba: i. Amananoba, e da ilima amane sia: i, “Da: niele lale gadodili oule masa!” Ilia e gadodili oule asili, ea da: iga se lai ganabeya: le hogoi be hame ba: i. Bai e da Godema dafawaneyale dawa: beba: le, agoane hamoi.
24 Ọba pàṣẹ pé, kí a mú àwọn alátakò Daniẹli wá, kí a jù wọ́n sí inú ihò kìnnìún, pẹ̀lú ìyàwó àti àwọn ọmọ wọn. Kí wọn tó dé ìsàlẹ̀ ihò, kìnnìún lágbára lórí i wọn, wọ́n sì fọ́ gbogbo egungun wọn.
Amalalu, hina bagade da sia: beba: le, dadi gagui da dunu amo da Da: nielema fofada: i, amo amola ilia uda amola mano, huluane laione wa: me uli dogoiga galagudui. Amola sanasinanoba, uli dogoiga daloba, hedolodafa laione wa: me ilia da soaga: la: gadole, ilia gasa huluane goudane sasali.
25 Nígbà náà ni Dariusi ọba kọ̀wé sí gbogbo ènìyàn orílẹ̀-èdè, àti gbogbo jákèjádò ilẹ̀ náà: “Kí ìre yín máa pọ̀ sí i!
Amalalu, hina bagade Da: liase da dunu amola uda fifi asi gala amola sia: hisu hisu ilima meloa dedene i, amane, “Na dilima asigi sia: sia: sa.
26 “Mo gbé àṣẹ kan jáde wí pé, ní gbogbo agbègbè ìjọba mi, gbogbo ènìyàn gbọdọ̀ bẹ̀rù, kí wọn kí ó sì bọ̀wọ̀ fún Ọlọ́run Daniẹli.
Na ouligibiga esalebe fi dunu amola uda! Dilia na sia: goe noga: le nabima. Dilia da Da: niele ea Gode amo Ea Dio bagade nodone gaguia gadoma. Amo Gode da eso huluane esalalalumu. E da Hina Bagade eso huluane fifi ahoanumu. Amola Ea gasa da hamedafa fisili, eso huluane amanewane dialumu.
27 Ó ń yọ ni, ó sì ń gbani là;
E da dunu amola uda mae se lama: ne gaga: musa: dawa: E da Hebene amola osobo bagade amo ganodini musa: hame ba: su amola dawa: digima: ne olelesu gasa bagade hou hamonana. E da Da: niele amo laione wa: me amoga mae gasomoma: ne gaga: i dagoi.
28 Daniẹli sì ṣe rere ní àkókò ìjọba Dariusi àti àkókò ìjọba Kirusi ti Persia.
Amola Da: liase e hina bagade esalebe eso amogalu da Sailase (Besia dunu) da ea sogebi lai dagoi. Amo eso huluane ganodini Da: niele da hahawane ouligisu mimogo dunu bagadedafa esalu.

< Daniel 6 >