< Daniel 5 >

1 Belṣassari, ọba ṣe àsè ńlá fún ẹgbẹ̀rún kan nínú àwọn ọlọ́lá rẹ̀, ó sì mu wáìnì pẹ̀lú u wọn.
Belesia: sa e da Ba: bilone amo ganodini hina bagade dunu esalu. E da lolo nasu bagade hamoi. E da ea lolo nasu amo ganodini ea ouligisu boboga amo 1000 agoane misa: ne wei. Amo gilisisu amo ganodini, ilia da waini hano manu.
2 Bí Belṣassari ṣe ń mu wáìnì, ó pàṣẹ pé kí wọn kó kọ́ọ̀bù wúrà àti ti fàdákà wá, èyí tí Nebukadnessari baba rẹ̀ kó wá láti inú tẹmpili ní Jerusalẹmu, kí ọba àti àwọn ọlọ́lá rẹ̀, àwọn ìyàwó àti àwọn àlè rẹ̀ kí ó ba à le fi mu wáìnì.
Ilia da waini nananoba, Belesia: sa da ea hawa: hamosu dunuma ilia da hano dili nasu faigelei gouli amola silifa amoga hamoi, amo liligi ea eda Nebiuga: denese ea da musa: Gode Ea diasu Yelusalemega lai, amo gaguli misa: ne sia: i. Belesia: sa ea hanai da e amola ea dunu boboga, ea udadafa ilia amola ea gidisedagi uda ili hulu gilisili manusa: dawa: i.
3 Wọ́n sì kó kọ́ọ̀bù wúrà àti fàdákà àti fàdákà èyí tí wọ́n kó jáde láti inú tẹmpili, ilé Ọlọ́run ní Jerusalẹmu, ọba àti àwọn ìjòyè rẹ̀, àwọn ìyàwó àti àwọn àlè rẹ̀, sì fi mu wáìnì.
Hawa: hamosu dunu da faigelei amola ofodo gouliga hamoi amo huluane gaguli misini, ilia huluane da amo faigelei amoga waini mai.
4 Bí wọ́n ṣe ń mu wáìnì bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń yin òrìṣà wúrà àti fàdákà, ti idẹ, irin, igi àti òkúta.
Ilia waini hano amo nanoba, ilia da ogogole ‘gode’ amo da gouli, silifa, balase, ifa amola igi amoga hamoi, amo loboga hamoi ogogosu ‘gode’ma nodosu.
5 Lójijì, ìka ọwọ́ ènìyàn jáde wá, ó sì ń kọ̀wé sára ẹfun ògiri ní ẹ̀gbẹ́ ibi tí fìtílà ń dúró ní ààfin ọba. Ọba ń wo ọwọ́ náà bí ó ṣe ń kọ ọ́.
Amola hedolodafa dunu ea lobo fawane (dunu da: i hodo hame) amo da misini, hina bagade ea diasu dobea amoga sia: dedenenebe ba: i. Amola gamali la: ididi nebeba: le, Belesia: sa da amo dunu ea lobo amo noga: le ba: i.
6 Ojú ọba sì yí padà, ẹ̀rù sì bà á, tó bẹ́ẹ̀ tí orúnkún ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèèjì rẹ̀ fi ń gbá ara wọn.
Belesia: sa da amo hou ba: beba: le bagadedafa beda: i. Amola ea odagi da afadenene haliga: i agoane ba: i. Amola ea muguni da bagadewane yagugui.
7 Ọba kígbe pé, kí wọn pe àwọn awòràwọ̀, àwọn onídán, àti àwọn aláfọ̀ṣẹ wá, ọba sì sọ fún àwọn amòye Babeli pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá lè ka àkọsílẹ̀ yìí kí ó sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀, ẹni náà ni a ó fi aṣọ elése àlùkò wọ̀ àti ẹ̀gbà wúrà ni a ó fi sí ọrùn un rẹ̀, òun ni yóò sì ṣe olórí kẹta ní ìjọba à mi.”
E da gasa bagade wele sia: i, “Ba: la: lusu dunu, gasumuni ba: su dunu amola fefedoasu dunu huluane misa: ne sia: ma.” Ilia da huluane gilisilalu, e da ilima amane sia: i, “Nowa da amo dedei ea bai nama adolalu, na da ema abula sesedado ouligisu dunu ilia salasu defele yoiyai imunu e sia: i. Amola sia: ine gouliga hahamoi ili asogoaga ligisisia, ea dio da bagade ba: mu. Amola e da Ba: bilone soge amo ganodini hina bagade osoda agoane ba: mu!”
8 Nígbà náà ni gbogbo àwọn amòye ọba wọ ilé, ṣùgbọ́n, wọn kò le è ka àkọsílẹ̀ náà tàbí sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún ọba.
Amalalu, bagade dawa: su dunu huluane da misini be dedei amo ilia da idimu gogolei amola bai Belesia: sama olelemu hamedeiwane ba: i.
9 Nígbà náà ni Belṣassari ọba bínú gidigidi, ojú u rẹ̀ sì túbọ̀ dàrú sí i. Ẹ̀rù sì ba àwọn ìjòyè Belṣassari.
Amola hina bagade Belesia: sa da bagadedafa beda: i. Amola ea odagi afadenene, baligili haliga: i agoane ba: i. Amola bagade dawa: su dunu ilia da adi hamoma: bela: le bagadewane dawa: lalu.
10 Nígbà tí ayaba gbọ́ ohùn ọba àti àwọn ọlọ́lá rẹ̀, ó wá ilé àsè wá. Ó wí pé, “Kí ọba kí ó pẹ́! Má ṣe jẹ́ kí inú rẹ bàjẹ́, má sì ṣe jẹ́ kí ojú u rẹ fàro.
Belesia: sa eme da hina bagade amola bagade dawa: su dunu ilia wele sia: su nababeba: le, e da ha: i nasu seseiga fila asi. Amalalu, e amane sia: i, “Hina bagade! Di eso huluane esalalalumu da defea. Bagadewane mae fofogadigima amola amo liligi bagade mae dawa: ma.
11 Ọkùnrin kan wà ní ìjọba à rẹ, ẹni tí ẹ̀mí ọlọ́run mímọ́ ń gbé inú rẹ̀. Ní ìgbà ayé e baba à rẹ, òun ni ó ní ojú inú, òye àti ìmọ̀ bí i ti ọlọ́run òun ni ọba Nebukadnessari, baba rẹ̀ fi jẹ olórí àwọn apidán, awòràwọ̀, apògèdè àti aláfọ̀ṣẹ.
Dunu afae da dia soge amo ganodini esala, amo ea dogo ganodini Gode Ea A: silibu da aligila sa: i dagoi. Amola dia ada da musa: hina bagade esaloba, amo eso galu, ea ba: lobada, amo dunu da ‘gode’ huluane ilia dawa: su noga: i amo defele dawa: i dagoi. Amaiba: le, dia ada Nebiuga: denese da amo dunu bagade dawa: su dunu fi amo ganodini bisilua hamoi dagoi.
12 Ọkùnrin náà ni Daniẹli ẹni tí ọba ń pè ní Belṣassari, ó ní ẹ̀mí tí ó tayọ, ìmọ̀ àti òye, àti agbára láti túmọ̀ àlá, ó máa ń ṣe àlàyé àlá àti àwọn ọ̀rọ̀ tí ó bá da ojú rú, ránṣẹ́ pè é, yóò sì sọ nǹkan tí àkọsílẹ̀ ìwé náà túmọ̀ sí.”
Bai amo dunu da dawa: su enoenoia dawa: su galu. Amola e da simasi ea bai olelesu dawa: , amola e da wamolegei liligi huluane dawa: Amo dunu ea dio da Da: niele, be hina bagade Nebiuga: denese da ema dio eno asuli amo Beledesia: sa. Amaiba: le, Da: niele amo dedei liligi ea bai huluane dima olelema: ne, e da dima misa: ne sia: ma!”
13 Nígbà náà ni a mú Daniẹli wá síwájú ọba, ọba sì sọ fún un wí pé, “Ṣé ìwọ ni Daniẹli, ọ̀kan lára àwọn tí baba mi mú ní ìgbèkùn láti Juda!
Amalalu ilia da hedolowane Da: niele oule misini, e da ganodini golili sa: ili hina bagade dunu amola dafulili fi. Hina bagade da ema amane sia: i, “Di da Da: niele, amo musa: na ada Nebiuga: denese da Yuda sogega lale guiguda: oule misi. Di da amo dunula: ?
14 Mo ti gbọ́ wí pé ẹ̀mí ọlọ́run ń gbé inú rẹ àti wí pé ìwọ ní ojú inú, òye, àti ọgbọ́n tí ó tayọ.
Na amane nabi, Gode Ea A: silibu da dia dogo ganodini aligila sa: i dagoi, amola di da bagade dawa: su dunu.
15 A ti mú àwọn amòye àti àwọn awòràwọ̀ wá sí iwájú mí kí wọn ba à le è wá ka àkọsílẹ̀ yìí kí wọn sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi, ṣùgbọ́n wọn kò le è sọ ìtumọ̀ ohun tí ó jẹ́.
Na da bagade dawa: su dunu ili da amo dedei idima: ne amola ea bai nama olelema: ne ili mafia: ma: ne wei. Be ilia da amo idimu amola bai olelemu hamedei agoane ba: i.
16 Ṣùgbọ́n mo ti gbọ́ wí pé, ìwọ lè sọ ìtumọ̀, àti wí pé o lè yanjú àwọn ìṣòro tó lágbára. Tí o bá lè ka àkọsílẹ̀ ìwé yìí kí o sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀, a ó fi aṣọ elése àlùkò wọ̀ ọ́ pẹ̀lú ẹ̀gbà wúrà ni a ó fi sí ọ lọ́rùn, a ó sì fi ọ́ ṣe olórí kẹta ní ìjọba mi.”
Be na amane nabi, di da wamolegei liligi huluane dawa: mu defele esala. Di da amo dedei ea bai nama adolalu, na da dima abula sesedado ouligisu dunu ilia salasu defele yoiyai imunu. Amola sia: ine gouliga hahamoi dia asogoaga ga: sisia, dia dio da bagade ba: mu. Amola di da Ba: bilone hina bagade soge amo ganodini eagene hina bagade amo bagia osoda agoane ba: mu.”
17 Nígbà náà ni Daniẹli dá ọba lóhùn wí pé, “Fi ẹ̀bùn rẹ pamọ́ fún ara rẹ, tàbí kí o fún ẹlòmíràn. Síbẹ̀ èmi yóò ka àkọsílẹ̀ náà fún ọba, èmi yóò sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀.
Da: niele da dabe amane sia: i, “Mae dawa: ma! Dia liligi imunu dawa: i galea disu lamu da defea o amo liligi dunu enoma ima. Be amo dedei na da dima idimu amola ea bai dima olelemu.
18 “Ìwọ ọba, Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo fún Nebukadnessari baba rẹ ní ìjọba, títóbi ògo àti ọlá.
Nabima! Gode Gadodafa esala amo Ea da musa: dia ada Nebiuga: denese amo gasa bagade amola hadigi hamoi dagoi.
19 Nítorí ipò ńlá tí a fi fún un, gbogbo ènìyàn orílẹ̀-èdè àti èdè gbogbo fi ń páyà tí wọ́n sì ń bẹ̀rù rẹ̀. Ó ń pa àwọn tí ó bá wù ú, ó sì ń dá àwọn tí ó bá wù ú sí, ó ń gbé àwọn tí ó bá wù ú ga, ó sì ń rẹ àwọn tí ó bá wù ú sílẹ̀.
E da gasa bagadedafa hamoi galu. Amaiba: le, fifi asi gala dunu amola uda huluane amola sia: hisu hisu huluane da ema bagadewane beda: i. E da dunu afae medole legemusa: dawa: lalu, e da amo dunu medole legei. E da dunu eno gaga: musa: dawa: lalu, amo dunu da esalebe ba: i. E da dunu afae ea dio gaguia gadoma: ne dawa: lalu, e da amanewane hamoi. Amola e da dunu afae banenesili osa: la heda: musa: dawa: lalu, e da amanewane hamoi.
20 Ṣùgbọ́n nígbà tí ọkàn rẹ̀ ga, tí ó sì le koko. Ó bẹ̀rẹ̀ sí i hùwà ìgbéraga, a mú u kúrò lórí ìtẹ́ ọba rẹ̀, a sì gba ògo rẹ̀ kúrò.
Be dia ada ea hou da heda: le, e da gasa fi hou, hame asigi hou amola hame nabasu hou enoenoi amoga wadela: i hou hamosu. Amo hou Gode da ba: beba: le, E da ea hina bagade hou amola ea dio bagade huluane fadegale fasili, e da dafai dagoi.
21 A lé e kúrò láàrín ènìyàn, a sì fún un ní ọkàn ẹranko; ó sì ń gbé pẹ̀lú àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó sì ń jẹ koríko bí i ti màlúù; ìrì ọ̀run ṣì sẹ̀ sí ara rẹ̀, títí tó fi mọ̀ pé, Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ń jẹ ọba lórí ìjọba ọmọ ènìyàn, òun sì ń fi fún ẹni tí ó bá wù ú.
E da dunu amola uda ilia gilisisu amoga sefasi dagoi ba: i. Amola e da asili ohe sogega e amola ohe da gilisili esalu. Amola e da bulamagau agoane gisi nanu. Amola e da hamega gadili golai amola oubi baea da e da: iya sa: i. E da amanewane ode fesuale esalu. Amalalu e da Gode Gadodafa amo da fifi asi gala ilima Hinadafa esalebe, amo e da dafawaneyale dawa: i. Amola E da Hina hou Hi hanaiga hamosa amola E da fi ouligisu hou eso enoga dunu afae amoga fadegalalu, Ea hanaiga eno dunu ilima (dunu bagade o fonobahadi Hi fawane dawa: ) ilima iaha, amo e da dawa: i galu.
22 “Ṣùgbọ́n ìwọ ọmọ rẹ̀, Belṣassari, ìwọ kò rẹ ara à rẹ sílẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ mọ nǹkan wọ̀nyí.
Di da Nebiuga: denese ea manoba: le, amo hou huluane dawa: le dagoi. Be di da gasa fi hamone amola dia hou da hame fonoboi ba: sa.
23 Dípò èyí, ìwọ gbé ara à rẹ ga sí Olúwa ọ̀run, a mú ohun èlò inú tẹmpili rẹ̀ wá sí iwájú rẹ, ìwọ àti àwọn ìjòyè rẹ, àwọn ìyàwó ò rẹ àti àwọn àlè rẹ fi ń mu wáìnì. Ìwọ ń yin àwọn òrìṣà fàdákà àti wúrà, idẹ, irin, igi àti ti òkúta, èyí tí kò lè ríran, tí kò le è gbọ́rọ̀ tàbí ní òye nǹkan kan. Ṣùgbọ́n ìwọ kò bu ọlá fún Ọlọ́run ẹni tó ni ẹ̀mí rẹ lọ́wọ́, tí ó sì mọ gbogbo ọ̀nà rẹ.
Be di da Gode Hebene amo ganodini esala, Ema hasalasimusa: dawa: i. Di da hano dili nasu faigelei gouli amola silifa amoga hamoi, amo liligi dia ada Nebiuga: denese ea da musa: Gode Ea diasu Yelusalemega lai, amo gaguli misa: ne sia: i. Amalalu di amola dia dunu boboga amola dia udadafa amola dia gidisedagi uda hulu gilisili amoga nasu. Amola dilia da waini hano amo nanoba, dilia da ogogole ‘gode’ amo da gouli, silifa, balase, ifa amola igi amoga hamoi, amo ogogosu ‘gode’, amo da hame naba, hame ba: sa amola hame dawa: sa, ilima dilia da nodosu. Godedafa da dilia esalusu logo amola dia bogosu logo amola hou huluanedafa ouesala. Be dilia da Ema hame nodosa amola Ea Dio hame gaguia gadosa.
24 Nítorí náà, ó rán ọwọ́ tí ó kọ àkọlé yìí.
Amaiba: le, Gode da amo sia: loboga dedema: ne asunasi dagoi.
25 “Èyí ni àkọlé náà tí a kọ: Mene, mene, tekeli, peresini.
Goe sia: da agoane dedei diala amo, ‘Idi, idi, dioi defei, afafasu.’
26 “Èyí ni nǹkan tí ọ̀rọ̀ náà túmọ̀ sí: “Mene: Ọlọ́run ti ṣírò ọjọ́ ìjọba rẹ. Ó sì ti mú u wá sí òpin.
Amola goe sia: bai da agoane. ‘Idi’ amo ea bai da Gode da dia ouligisu eso idi dagoi. Amola wali dia hina bagade dagosu eso da doaga: i dagoi.
27 “Tekeli: A ti gbé ọ lórí òsùwọ̀n, ìwọ kò sì tó ìwọ̀n.
‘Dioi defei’ amo ea bai da Gode da dia dioi defei ba: i dagoi amola E da dia dioi defei da haga: i amola defele hame ba: i.
28 “Peresini: A ti pín ìjọba rẹ a sì ti fi fún àwọn Media àti àwọn Persia.”
‘Afafasu’ amoea bai da Gode da dia ouligisu fi amola soge amo afafae dagoi. La: idi E da Midia fi ilima i dagoi. La: idi eno E da Besia fi ilima i dagoi.”
29 Nígbà náà ni Belṣassari pàṣẹ pé kí a wọ Daniẹli ní aṣọ elése àlùkò, kí a sì fi ẹ̀gbà wúrà sí i lọ́rùn, a sì kéde rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí olórí kẹta ní ìjọba rẹ̀.
Belesia: sa da amo sia: , nababeba: le, e da ea hawa: hamosu dunuma ilia da abula sesedado ouligisu dunu ilia salasu defele yoiyai Da: niele ema imunu sia: i. Amola sia: ine gouliga hahamoi ea asogoaga ga: sima: ne sia: i. Amola e da Ba: bilone soge amo ganodini Da: niele eagene hina bagade e bagia osoda agoane hamoi.
30 Ní alẹ́ ọjọ́ náà ni a pa Belṣassari, ọba àwọn ara Kaldea.
Amo gasi amoga, Midia fi dunu da misini, Belesia: sa (Ba: bilone hina bagade galu) amo medole legei dagoi.
31 Dariusi ará Media sì gba ìjọba nígbà tí ó di ọmọ ọdún méjìlélọ́gọ́ta.
Amola Midia hina bagade dunu amo Da: liase, e Ba: bilone soge huluane lai dagoi. Amo esoga, Da: liase ea esalebe ode gidigi da62 galu.

< Daniel 5 >