< Daniel 12 >
1 “Ní àkókò náà, ni Mikaeli, ọmọ-aládé ńlá, ẹni tí o ń dáàbò bo àwọn ènìyàn an rẹ̀ yóò dìde. Àkókò ìpọ́njú yóò wà, irú èyí tí kò tí ì ṣẹlẹ̀ rí láti ìbẹ̀rẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè títí di àkókò náà. Ṣùgbọ́n ní àkókò náà àwọn ènìyàn rẹ̀, gbogbo àwọn tí a bá ti rí orúkọ wọn nínú ìwé ni a ó gbàlà.
Amalalu, a:igele amo da abula noga: i amoga idiniginisi, e da nama amane sia: i, “Amo esoga, gasa bagade a: igele dunu amo da dia fi ilima sosodo aligisu dunu (ea dio da Maigele), amo da misini, ba: mu. Amalalu, osobo bagade fi da se nabasu eso ba: mu. Amo se nabasu da musa: se nabasu eso huluane baligimu. Amo eso doaga: lalu, nowa dunu amola uda ilia dio amo Gode Ea buga ganodini dedei dialebe ba: lalu, e da gaga: su ba: mu.
2 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn tí ó sùn nínú erùpẹ̀ ilẹ̀ ni yóò jí: àwọn mìíràn sí ìyè àìnípẹ̀kun, àwọn tókù sí ìtìjú àti sí ẹ̀gàn àìnípẹ̀kun.
Dunu bagohame da musa: bogoi, amo da bu wa: legadomu. Mogili da Fifi Ahoanusu lama: ne wa: legadomu. Be mogili da eso huluane gogosiane se nabawane esaloma: ne wa: legadomu.
3 Àwọn tí ó jẹ́ ọlọ́gbọ́n yóò máa tàn bí ìmọ́lẹ̀ ọ̀run, àti àwọn tí ó ń tọ́nisọ́nà sí òdodo, yóò máa tàn bí ìràwọ̀ láé àti láéláé.
Noga: idafa bagade dawa: su dunu da hadigi mu amo ea hadigi defele hadigimu. Amola nowa dunu da eno dunuma moloidafa hou olelei, amo ilia da gasumuni defele mae fisili eso huluane hadigilalumu.”
4 Ṣùgbọ́n ìwọ Daniẹli, pa ìwé náà dé kí o sì pa ọ̀rọ̀ ọ rẹ̀ mọ́ títí àkókò ìgbẹ̀yìn. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ yóò máa lọ sí ìhín sí ọ̀hún láti jẹ́ kí ìmọ̀ wọn di púpọ̀.”
Amola a: igele dunu da nama amane sia: i, “Da: niele! Di wali buga houga: i amo ga: sima. Amola amo buga bu mae houga: ma: ne, gobele legesu ga: su liligi amoga ga: sima. Amalalu, soge wadela: mu eso da doaga: lalu fawane, amo buga da bu houga: i dagoi ba: mu. Dunu mogili da hobea misunu hou dawa: musa: gini hogolalu, hamedei ba: mu,” a: igele da amane sia: i.
5 Nígbà náà, ni èmi Daniẹli, wò, ní iwájú mi àwọn méjì mìíràn dúró, ọ̀kan dúró sí apá ìhín ní etí bèbè odò ẹnìkan náà ní apá òdìkejì ọ̀hún etí i bèbè.
Amalalu, na da a: igele dunu aduna hano gadenene lelebe ba: i. Afae da hano na: iyado lelebe ba: i. Eno da na: iyadodili lelebe ba: i.
6 Ọ̀kan lára wọn sọ fún ọkùnrin tí ó wọ aṣọ àlà, ẹni tí ó wà lórí omi odò pé, “Báwo ni yóò ṣe pẹ́ tó kí àwọn nǹkan ìyanu wọ̀nyí tó wá sí ìmúṣẹ?”
Amo a: igele dunu afae da musa: a:igele dunu (amo da hano banugumadi lelebe ba: i) ema amane adole ba: i, “Amo dogoa gilula ahoasu hou di da Silia hina bagade ea hou olelei amo amola soge wadela: mu eso da habogala doaga: ma: bela: ?”
7 Ọkùnrin tí ó wọ aṣọ àlà, ẹni tí ó wà lórí omi odò, gbé ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ àti ọwọ́ òsì rẹ̀, mo gbọ́ tí ó fi ẹni tí ó wà títí láé búra, ó sọ wí pé, “Yóò ṣe ní àkókò kan, àkókò méjì àti ààbọ̀. Nígbà tí agbára àwọn ẹni mímọ́ yóò ti fọ́ tán pátápátá, gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò sì parí.”
Amola musa: a:igele dunu da ea lobo aduna ligia gadole, na da ea sia: amane nabi, “Na da Eso Huluane Esalalalusu Gode amo Ea Dioba: le dafawane ilegele sia: sa. Ode udiana da gidigisia amola oubi eno gafeyale da udusia, amo hou da huluane dagoi ba: mu. Gode Ea fi dunu da se nabasu bagade ba: mu. Be amo se nabasu da dagolalu, amo hou huluane da dagoi ba: mu.”
8 Èmi gbọ́, ṣùgbọ́n kò yé mi. Nígbà náà ni mo béèrè pé, “Olúwa mi, kí ni yóò jẹ́ àbábọ̀ àwọn nǹkan wọ̀nyí?”
Na da ea sia: nabi dagoi be bai noga: le hame dawa: i galu. Amaiba: le, na da ema amane adole ba: i, “Hina! Amo liligi huluane da habodane dagoma: bela:”
9 Ó sì dáhùn pé, “Máa lọ ní ọ̀nà rẹ, Daniẹli nítorí tí a ti pa ọ̀rọ̀ náà dé, a sì ti fi èdìdì dì í di ìgbà ìkẹyìn.
Be e da nama bu adole i, “Defea, Da: niele, di waha masa. Bai amo sia: huluane da wamolegei dagoi. Soge wadela: mu eso da doaga: i dagoi ba: lalu fawane, noga: le ba: mu.
10 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni a ó fọ̀ mọ́, wọn yóò wà láìlábàwọ́n, a ó sì tún wọn ṣe, ṣùgbọ́n àwọn ẹni búburú yóò máa ṣe búburú lọ, kò sí ẹni búburú tí òye yóò yé ṣùgbọ́n òye yóò yé àwọn ọlọ́gbọ́n.
Dunu amola uda bagohame da sema defele dodofei dagoi ba: mu. Amola wadela: i hamosu dunu da amo hou hame dawa: mu. Be ilia da wadela: i hou mae fisili hamonanumu. Be bagade dawa: su dunu da amo hou dawa: mu.
11 “Láti àkókò tí a ó mú ẹbọ ojoojúmọ́ kúrò, tí a ó sì gbé ìríra tí ó ń fa ìsọdahoro kalẹ̀ yóò sì jẹ́ ẹgbẹ̀rún àti igba lé àádọ́rùn-ún ọjọ́.
Amo bai mui da ha lai dunu da Isala: ili dunu ilia eso huluane gobele salasu hou logo ga: si dagoi amola Wadela: idafa Liligi amo Debolo diasu ganodini sagasu, amalalu eso 1,290 da asili, amo hou da dagoi ba: mu.
12 Ìbùkún ni fún ẹni tí ó dúró, ti ó sì di òpin ẹgbẹ̀rún àti ọ̀ọ́dúnrún lé àrùndínlógójì ọjọ́.
Be Gode Ea fi dunu amola uda da eso 1,335 amoga lalegagui hou mae fisili esalea, amo da hahawane bagade ganumu.
13 “Ṣùgbọ́n ìwọ, máa lọ ní ọ̀nà rẹ, títí di òpin. Ìwọ yóò sinmi, àti ní òpin ọjọ́ ìwọ yóò dìde láti gba èrè rẹ.”
Amola, di, Da: niele! Di hahawane Gode Ea hou ganodini dafawaneyale dawa: iwane esaloma. Amalalu, di da bogomu. Be di da bu wa: legadomu. Amola soge wadela: mu esoga, di da Gode Ea loboga dia bidi ida: iwane lamu.” Sia: ama dagoi