< Daniel 10 >
1 Ní ọdún kẹta Kirusi ọba Persia, a fi ìran kan hàn Daniẹli (ẹni tí à ń pè ní Belteṣassari). Òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ ìran náà, ó sì ní í ṣe pẹ̀lú àsìkò ìpọ́njú ńlá, òye ọ̀rọ̀ náà wá bá a nínú ìran.
(Sailase da Besia soge amoga hina bagade galu. Ea ouligisu hou ode osoda amoga, Da: niele (ea dio eno da Beledesia: sa) da esala ba: i dagoi. Amo esala ba: i ea bai da dafawane be dawa: mu da gasa bagade ba: i. Be a: igele dunu da amo ea bai, Da: niele ea esala ba: su ganodini ema olelei.
2 Ní àsìkò náà, èmi Daniẹli ṣọ̀fọ̀ fún ọ̀sẹ̀ mẹ́ta.
Da: niele ea sia: ne iasu da agoane, “Amo esoga, na da hi udiana se nabawane disa esalu.
3 Èmi kì í jẹ oúnjẹ tí ó dára, èmi kò fi ẹran tàbí wáìnì kan ẹnu mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò fi òróró para títí ọ̀sẹ̀ mẹ́ta fi kọjá.
Amo hi udiana amoga, na da ha: i manu noga: i amola hu amola waini mae nawane esalu. Na busa hinabo amola na da hame gisu, udigili esalu.
4 Ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù àkọ́kọ́, bí mo ti dúró sí etí i bèbè odò ńlá Tigirisi,
Amo odega, oubi age amola amo ea eso 24 amoga, na da Daigalisi Hano bagade amo ea bega: lelebe ba: i.
5 mo wo òkè, mo rí ọkùnrin kan tí ó wọ aṣọ àlà, ẹ̀gbẹ́ ẹni tí a fi wúrà Upasi dáradára dì ní àmùrè.
Na da ba: le gadole, dunu afae amo abula noga: i ga: ne amola bulu gouliga hamoi idiniginisi amo lelebe ba: i.
6 Ara rẹ̀ dàbí berili, ojú u rẹ̀ dàbí mọ̀nàmọ́ná, ẹyin ojú u rẹ̀ dàbí iná àtẹ̀tàn, apá àti ẹsẹ̀ rẹ̀ dàbí ìtànná ìmọ́lẹ̀ tí o kún fún idẹ, àti ohùn rẹ̀ dàbí i ti ìjọ ènìyàn púpọ̀.
Ea da: i da igi ida: iwane agoane hadigi ba: i. Ea odagi da hadigidafa ha: ha: na ea bagele gala: i agoane ba: i. Ea si da lalu sawa: agoane ba: i. Ea lobo amola ea emo da balase ela: mei agoane ba: i. Amola ea sia: da dunu amola uda gilisisu bagadedafa amoga ilia ha: giwane sia: dasu defele nabi.
7 Èmi Daniẹli, ni ẹnìkan tí ó rí ìran náà, àwọn ọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú u mi, wọn kò rí i, ṣùgbọ́n ìpayà ńlá dà bò wọ́n, wọ́n sálọ wọ́n sì fi ara pamọ́.
Nisu ni fawane da esala ba: i liligi ba: i. Dunu eno da na gilisili esalu, amo da beda: iba: le, hobeale, wamoaligili, liligi hame ba: i.
8 Ó sì ku èmi nìkan, tí mo rí ìran ńlá yìí, kò sì ku okun kankan fún mi, ojú u mi sì rẹ̀wẹ̀sì gidigidi, n kò sì ní agbára mọ́.
Amaiba: le, na fawane da amo esala ba: i liligi ba: sawane esalu. Na gasa huluane fisi dagoi ba: i, amola na odagi da bagadewane afadeneiba: le, na sama da na dawa: mu da hamedei ba: la: loba.
9 Nígbà náà, ni mo gbọ́ tí ó ń sọ̀rọ̀, bí mo ṣe tẹ́tí sílẹ̀ sí i, mo sùn lọ fọnfọn, ní ìdojúbolẹ̀.
Na da amo dunu ea sia: nabalalu, na da osoboga sidina sa: ili, na odagi osoboga digili dialu.
10 Ọwọ́ kan kàn mí, ó gbé mi dìde ní ìwárìrì lórí ọwọ́ àti eékún mi.
Amalalu, a:igele dunu da na lobolele, hiougili gadole, na da muguni bugili amola lobo gagula sa: i dialu. Na da bagade beda: iba: le, fofogolalu.
11 Ó sọ pé, “Daniẹli ẹni tí a yàn fẹ́ gidigidi gba ọ̀rọ̀ tí mo fẹ́ bá ọ sọ yìí yẹ̀ wò dáradára, kí o sì dìde, nítorí tí a rán mi sí ọ.” Bí ó ṣe sọ èyí fún mi, mo dìde ní ìwárìrì.
A: igele dunu da nama amane sia: i, “Da: niele! Gode da dima bagadewane asigisa. Wa: legadoma! Na sia: noga: le nabima. Gode da na dima adoma: ne asunasi dagoi.” E da amo sia: beba: le, na da yaguguiwane, wa: legadole lelu.
12 Nígbà náà ni ó tẹ̀síwájú, pé, “Má ṣe bẹ̀rù Daniẹli. Láti ọjọ́ àkọ́kọ́ tí ìwọ ti fi ọkàn rẹ sílẹ̀ níwájú Ọlọ́run rẹ, a gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ, mo sì wá nítorí ọ̀rọ̀ náà.
Amalalu, e da nama amane sia: i, “Da: niele! Di mae beda: ma! Di da Gode Ea hou hobea misunu amo dawa: ma: ne dia hou fonoboi, amo eso age amola fa: no, Gode da dia sia: ne gadosu nabi dagoi. Na da dia sia: ne gadosu adole ba: su amo adole imunusa: misi dagoi.
13 Ṣùgbọ́n ọmọ-aládé ìjọba Persia dá mi dúró fún ọjọ́ mọ́kànlélógún. Nígbà náà ni Mikaeli, ọ̀kan lára ìjòyè àwọn ọmọ-aládé, wá láti ràn mi lọ́wọ́, nítorí a dá mi dúró níbẹ̀ pẹ̀lú ọba Persia.
Na da hedolo misunu hanai galu. Be a: igele ouligisu amo da Besia fi ouligisa, e da eso21 amoga na misunu logo hedofai. Na da Besia soge ganodini, nisu udigili esalebeba: le, Gode Ea bisili bagade a: igele ouligisu fi amo ganodini a: igele afae amo ea dio da Maigele da na fidimusa: misi.
14 Ní ìsinsin yìí mo wá láti ṣàlàyé ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn ènìyàn rẹ ní ọjọ́ iwájú, nítorí ìran náà ń sọ nípa ọjọ́ iwájú.”
Di da hou amo da dia fi dunu amola uda ilima hobea doaga: mu, amo noga: le dawa: ma: ne, na da dima olelemusa: misi. Amo esala ba: i ea bai da hobea misunu hou.
15 Bí ó sì ti ń sọ nǹkan wọ̀nyí fún mi, mo sì dorí kodò mo sì dákẹ́.
Ea sia: nababeba: le, na da osoba ba: le guduli, mae sia: baouni lelu.
16 Nígbà náà, ni ẹnìkan tí ó rí bí ènìyàn fi ọwọ́ kan ètè mi, mo la ẹnu mi, mo sì bẹ̀rẹ̀ sí ní sọ ọ̀rọ̀, mo sọ fún ẹni tí ó dúró níwájú mi, “Ìrònú sì mú mi, nítorí ìran náà, olúwa mi, n kò sì ní okun.
Amalalu, a:igele (e da dunu agoane ba: i) ea lobo molole, na lafi gadofo digili ba: i. Amalalu, na da ema amane sia: i, “Hina! Na da amo esala ba: i dawa: beba: le, gasa hamedafa. Gasa hameba: le, na da yagugui fisimu gogolei.
17 Ǹjẹ́ báwo ni èmi ìránṣẹ́ ẹ̀ rẹ ṣe lè bá ọ sọ̀rọ̀, olúwa mi? Agbára mi ti lọ, agbára káká ni mo fi ń mí.”
Na da udigili hawa: hamosu dunu amo ea hina ea midadini lela, amo defele lela. Na da habodane dima sia: ma: bela: ? Na da gasa hamedafa amola na da helega ha: ha: i.”
18 Ẹ̀wẹ̀, ẹnìkan tí ó rí bí ènìyàn fi ọwọ́ kàn mí, ó sì fún mi ní agbára.
Amo dunu da nama bu gagulaligiliba, na gasa bu lai dagoi.
19 Ó sì wí pé, “Má ṣe bẹ̀rù, ìwọ ọkùnrin olùfẹ́ gidigidi. Àlàáfíà ni fún ọ, mú ara le, àní mú ara le.” Nígbà tí ohun bá mi sọ̀rọ̀, a sì mú mi lára le. “Mo sì wí pé, kí olúwa mi kí ó máa sọ̀rọ̀, níwọ̀n ìgbà tí ìwọ ti mú mi ní ara le.”
E nama amane sia: i, “Gode da dima bagade asigisa. Amaiba: le, di mae beda: ma. Amola dia dogo denesini aligima.” E da amo sia: beba: le, na gasa da bu baligili sinidigi. Na da ema amane sia: i, “Hina! Di nama sia: musa: misi sia: nama adoma. Dia da na gasa nama bu i dagoi.”
20 Nígbà náà, ni ó wí pé, “Ṣé o mọ ìdí tí mo fi tọ̀ ọ́ wá? Láìpẹ́ èmi yóò yípadà lọ bá àwọn ọmọ-aládé Persia jà, nígbà tí mo bá lọ àwọn ọmọ-aládé Giriki yóò wá;
21 ṣùgbọ́n ní àkọ́kọ́, èmi yóò sọ ohun tí wọ́n kọ sínú ìwé òtítọ́ fún ọ. (Kò sí ẹni tí ó kún mi lọ́wọ́ fún nǹkan wọ̀nyí bí kò ṣe Mikaeli, ọmọ-aládé e yín.
E amane sia: i. “Na da dima sia: amo Dafawane Sia: Buga amo ganodini dedei liligi, dima adola misi. Wali na da Besia ouligisu a: igele, ema gegemusa: masunu. Amalalu, Galigi fi ouligisu a: igele da misunu. (Na da amoga gegemusa: fidisu dunu eno hame ba: sa. Isala: ili fi ouligisu a: igele noga: i, amo Maigele, hi fawane da na fidisa).