< Amos 9 >

1 Mo rí Olúwa, ó dúró ní ẹ̀bá pẹpẹ, ó sì wí pé: “Lu orí àwọn àtẹ́rígbà ìlẹ̀kùn kí àwọn òpó kí ó lè mì fọ́ wọn sí orí àwọn gbogbo ènìyàn àwọn tí ó ṣẹ́kù ni èmi yóò fi idà pa, ẹni tí ó sálọ nínú wọn kí yóò sá gbé, ẹni ti ó sá àsálà nínú wọn kí yóò gbàlà.
Mǝn Rǝbning ⱪurbangaⱨning yenida turƣinini kɵrdum; U mundaⱪ dedi: — — Tüwrüklǝrning baxlirini urunglar, bosuƣilar silkingiqǝ urunglar, Ularni [ibadǝthanidikilǝrning] baxliriƣa qüxürüp, parǝ-parǝ ⱪilinglar! Mǝn xu [butpǝrǝslǝr]din ǝng ahirda ⱪalƣanlirinimu ⱪiliq bilǝn ɵltürimǝn; Ulardin ⱪaqay degǝnlǝr ⱪaqalmaydu, Ulardin ⱪutulay degǝnlǝr ⱪutulup qiⱪalmaydu.
2 Bí wọ́n tilẹ̀ wa ilẹ̀ lọ sí ipò òkú, láti ibẹ̀ ni ọwọ́ mi yóò ti tẹ̀ wọ́n. Bí wọ́n tilẹ̀ gun òkè ọ̀run lọ, láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti mú wọn sọ̀kalẹ̀. (Sheol h7585)
Ular tǝⱨtisara iqigǝ texip kirsǝ, ⱪolum axu yǝrdin ularni tartip qiⱪiridu; Ular asmanƣa yamixip qiⱪsa, Mǝn xu yǝrdin ularni tartip qüxürimǝn; (Sheol h7585)
3 Bí wọ́n tilẹ̀ fi ara wọn pamọ́ ni orí òkè Karmeli, èmi yóò wá wọn rí, Èmi yóò si mú wọn kúrò níbẹ̀. Bí wọ́n tilẹ̀ fi ara pamọ́ fún mi sí ìsàlẹ̀ Òkun, láti ibẹ̀ ni Èmi yóò ti pàṣẹ fún ejò kí ó bù wọ́n ṣán.
Ular Karmǝl qoⱪⱪisiƣa mɵküwalsimu, Mǝn ularni izdǝp xu yǝrdin alimǝn; Ular dengiz tegidǝ nǝzirimdin yoxurunuwalƣan bolsimu, Mǝn yilanni buyruymǝn, u ularni qaⱪidu;
4 Bí wọ́n tilẹ̀ lọ sí ìgbèkùn ní iwájú àwọn ọ̀tá wọn láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti pàṣẹ fún idà kí ó ṣá wọn pa. “Èmi yóò sì tẹ ojú mi mọ́ wọn fún ìbí, kì í sì í ṣe fún rere.”
Düxmǝnlirigǝ ǝsirgǝ qüxkǝn bolsimu, Mǝn xu yǝrdǝ ⱪiliqni buyruymǝn, u ularni ɵltüridu; Mǝn yahxiliⱪni ǝmǝs, bǝlki yamanliⱪni yǝtküzüx üqün kɵzlirimni ularƣa tikimǝn.
5 Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ẹni ti ó fi ọwọ́ kan ilẹ̀ náà tí ó sì yọ́, tí àwọn olùgbé inú rẹ̀ yóò sì ṣọ̀fọ̀; gbogbo orílẹ̀-èdè yóò si ru sókè bí ríru odò Naili tiwọn yóò sì tẹ̀rì bí odò Ejibiti.
Samawi ⱪoxunlarning Sǝrdari bolƣan Rǝb Pǝrwǝrdigar, Zeminƣa tǝgküqi bolsa dǝl Uning Ɵzidur; U tegixi bilǝnla, zemin erip ketidu, uningda turuwatⱪanlarning ⱨǝmmisi matǝm tutidu; Zemin Nil dǝryasidǝk ɵrlǝp ketidu — Misirning dǝryasidǝk [ɵrkǝxlǝp], andin qɵküp ketidu.
6 Òun ni ẹni tí ó kọ́ ìtẹ́ rẹ̀ nínú àwọn ọ̀run ti ó sì fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ ní ilé ayé, Ẹni ti ó pe àwọn omi Òkun ti ó sì tú wọn jáde si orí ilé ayé Olúwa ni orúkọ rẹ̀.
Rawaⱪlirini ǝrxlǝrgǝ selip, asman gümbizini yǝr yüzigǝ bekitküqi Xudur; Dengizdiki sularni qaⱪirip, ularni yǝr yüzigǝ ⱪuyƣuqi Udur; Pǝrwǝrdigar Uning namidur.
7 “Àbá ẹ̀yin ọmọ Israẹli kò ha dàbí àwọn ọmọ Kuṣi sí mi?” ni Olúwa wí. “Èmi kò ha ti mú Israẹli gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti jáde wá àti àwọn Filistini láti ilẹ̀ Kafitori àti àwọn ará Aramu láti Kiri?
Silǝr Manga nisbǝtǝn Efiopiyǝ baliliriƣa ohxax ǝmǝsmu, i Israil baliliri? Mǝn Israilni Misirdin elip qiⱪarƣan ǝmǝsmu? Filistiylǝrni Kret arilidin, Suriyǝliklǝrni Kir xǝⱨiridin qiⱪarƣan ǝmǝsmu?
8 “Dájúdájú, ojú Olúwa Olódùmarè ń bẹ̀ lára ilẹ̀ ọba tó kún fún ẹ̀ṣẹ̀. Èmi yóò pa á run kúrò lórí ilẹ̀. Síbẹ̀, Èmi kò nípa ilé Jakọbu run pátápátá,” ni Olúwa wí.
Ⱪaranglar, Rǝb Pǝrwǝrdigarning kɵzi «gunaⱨkar padixaⱨliⱪ» üstigǝ qüxti — Mǝn yǝr yüzidin uni yoⱪitimǝn; Lekin Mǝn Yaⱪup jǝmǝtini toluⱪ yoⱪitiwǝtmǝymǝn, — dǝydu Pǝrwǝrdigar.
9 “Nítorí Èmi yóò pàṣẹ, Èmi yóò sì mi ilé Israẹli ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè bí a ti ń jọ nǹkan nínú ajọ̀ tí hóró kín ń kín kì yóò bọ́ sórí ilẹ̀.
Qünki ⱪaranglar, Mǝn buyruⱪ qüxürimǝn, Xuning bilǝn huddi birsi danni ƣǝlwirdǝ tasⱪiƣandǝk, Israil jǝmǝtini ǝllǝr arisida tasⱪaymǝn, Biraⱪ ulardin ǝng kiqikimu yǝrgǝ qüxüp kǝtmǝydu.
10 Gbogbo àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ láàrín àwọn ènìyàn mi ni yóò ti ipa idà kú gbogbo àwọn ti ń wí pé, ‘Aburú kì yóò lé wa bá, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò ká wa mọ́.’
[Ⱨalbuki], hǝlⱪimning barliⱪ gunaⱨkarliri, yǝni: «Külpǝt bizgǝ ⱨǝrgiz yeⱪinlaxmaydu, beximizƣa qüxmǝydu» degüqilǝr ⱪiliq tegidǝ ɵlidu.
11 “Ní ọjọ́ náà ní Èmi yóò gbé àgọ́ Dafidi tí ó wó ró, Èmi yóò dí odi rẹ̀ tí ó ya, Èmi yóò sì gbé ahoro rẹ̀ sókè, Èmi yóò sì kọ bí ti ọjọ́ ìgbàanì,
Xu küni Mǝn Dawutning yiⱪilƣan kǝpisini yengibaxtin tiklǝymǝn, Uning yeriⱪlirini etimǝn; Uni harabiliktin ongxap, Əyni zamandiki petidǝk ⱪurimǝn.
12 kí wọn le jogún ìyókù Edomu àti gbogbo àwọn kèfèrí, ti a ń pè nípa orúkọ mi,” ni Olúwa, ẹni tí yóò ṣe nǹkan wọ̀nyí wí.
Xuning bilǝn ular Edomning ⱪaldisiƣa ⱨǝmdǝ namim bilǝn atalƣan barliⱪ ǝllǝrgǝ igidarqiliⱪ ⱪilidu, — dǝydu buni bejirgüqi Pǝrwǝrdigar.
13 “Ọjọ́ náà ń bọ,” ni Olúwa wí, “tí ẹni tí ń tulẹ̀ yóò lé ẹni tí ń kórè bá. Tí ẹni tí ń fún èso àjàrà yóò lé ẹni tí ń gbìn bá. Àwọn òkè ńlá yóò sì kán ọtí wáìnì sílẹ̀, tí yóò sì sàn láti ara àwọn òkè kéékèèké.
Mana xundaⱪ künlǝr keliduki, — dǝydu Pǝrwǝrdigar, — Yǝr ⱨǝydigüqi ⱨosul yiƣⱪuqiƣa yetixiwalidu, Üzümlǝrni qǝyligüqi uruⱪ qaqⱪuqiƣa yetixiwalidu; Taƣlar yengi xarabni temitip, Barliⱪ dɵng-egizliklǝr erip ketidu.
14 Èmi yóò si tún mú ìgbèkùn Israẹli ènìyàn mi padà bọ̀. “Wọn yóò sì kọ́ ahoro ìlú, wọn yóò sì máa gbé inú wọn. Wọn yóò sì gbin ọgbà àjàrà, wọn yóò sì mu ọtí wáìnì wọn wọn yóò sì ṣe ọgbà pẹ̀lú, wọn yóò sì jẹ èso inú wọn.
Wǝ hǝlⱪim Israilni asarǝttin ⱪutuldurup, azadliⱪⱪa erixtürimǝn; Ular harab xǝⱨǝrlǝrni ⱪayta ⱪurup, ularda makanlixidu; Ular üzümzarlarni tikip, ularning xarabini iqidu; Ular baƣlarni bǝrpa ⱪilip, mewisini yǝydu.
15 Èmi yóò gbin Israẹli sí orí ilẹ̀ rẹ̀. A kì yóò sì fà wọn tu mọ́ láéláé kúrò ni orí ilẹ̀ ti mo fi fún wọn,” ni Olúwa Ọlọ́run rẹ wí.
Mǝn ularni ɵz zemini üstigǝ tikimǝn, Ular Mǝn ularƣa ata ⱪilƣan zemindin ⱨǝrgiz ⱪaytidin yuluwetilmaydu — dǝydu Pǝrwǝrdigar sening Hudaying.

< Amos 9 >