< Amos 9 >

1 Mo rí Olúwa, ó dúró ní ẹ̀bá pẹpẹ, ó sì wí pé: “Lu orí àwọn àtẹ́rígbà ìlẹ̀kùn kí àwọn òpó kí ó lè mì fọ́ wọn sí orí àwọn gbogbo ènìyàn àwọn tí ó ṣẹ́kù ni èmi yóò fi idà pa, ẹni tí ó sálọ nínú wọn kí yóò sá gbé, ẹni ti ó sá àsálà nínú wọn kí yóò gbàlà.
Na da Hina Gode oloda dafulili lelebe ba: i. E da amane hamoma: ne sia: i, “Debolo duni bugi amo gadodili, amo Debolo ea bai yaguguma: ne fama! Ilia da mugululi, dunu ilia dialumaga sa: ima: ne, fima! Na da dunu hame bogoi amo huluane gegesu ganodini fane legemu! Dunu afae da hobea: i dagoi hame ba: mu.
2 Bí wọ́n tilẹ̀ wa ilẹ̀ lọ sí ipò òkú, láti ibẹ̀ ni ọwọ́ mi yóò ti tẹ̀ wọ́n. Bí wọ́n tilẹ̀ gun òkè ọ̀run lọ, láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti mú wọn sọ̀kalẹ̀. (Sheol h7585)
Ilia da uli dogone, gudu sa: ili, bogoi sogega doaga: sea, Na da ili hogole ba: mu. Ilia da muagado heda: sea, Na da ili ba: mu. (Sheol h7585)
3 Bí wọ́n tilẹ̀ fi ara wọn pamọ́ ni orí òkè Karmeli, èmi yóò wá wọn rí, Èmi yóò si mú wọn kúrò níbẹ̀. Bí wọ́n tilẹ̀ fi ara pamọ́ fún mi sí ìsàlẹ̀ Òkun, láti ibẹ̀ ni Èmi yóò ti pàṣẹ fún ejò kí ó bù wọ́n ṣán.
Ilia da Gamele Goumi gadodili da: iya wamoaligisia, Na da ili hogoi helele lamu. Ilia da hano wayabo bagade hagududafa amoga Na ili mae ba: ma: ne, wamoaligisia, Na da gasonasu ohe bagade hano wayabo bagade ganodini esala, amo ili gasomoma: ne sia: mu.
4 Bí wọ́n tilẹ̀ lọ sí ìgbèkùn ní iwájú àwọn ọ̀tá wọn láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti pàṣẹ fún idà kí ó ṣá wọn pa. “Èmi yóò sì tẹ ojú mi mọ́ wọn fún ìbí, kì í sì í ṣe fún rere.”
Ilima ha lai da ili ga sogega mugululi ahoasea, Na da amo dunu ili fane legema: ne sia: mu. Na da ili mae fidili, udigili wadela: lesimu fawane ilegei dagoi.
5 Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ẹni ti ó fi ọwọ́ kan ilẹ̀ náà tí ó sì yọ́, tí àwọn olùgbé inú rẹ̀ yóò sì ṣọ̀fọ̀; gbogbo orílẹ̀-èdè yóò si ru sókè bí ríru odò Naili tiwọn yóò sì tẹ̀rì bí odò Ejibiti.
Ouligisudafa Hina Gode Bagadedafa da osobo bagade digili ba: sea, osobo bagade da yagugusa. Dunu huluane amogai esala da didigia: mu. Osobo bagade da Naile Hano defele, gado heda: sa amola gudu daha.
6 Òun ni ẹni tí ó kọ́ ìtẹ́ rẹ̀ nínú àwọn ọ̀run ti ó sì fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ ní ilé ayé, Ẹni ti ó pe àwọn omi Òkun ti ó sì tú wọn jáde si orí ilé ayé Olúwa ni orúkọ rẹ̀.
Hina Gode da Ea diasu muagado ganodini gagusa. E da mu dedebosu agoane osobo bagadega figisisa. E da hano wayabo bagade amo ea hano misa: ne sia: sea, osobo bagade da: iya sogadigisa. Ea Dio da Hina Godedafa!
7 “Àbá ẹ̀yin ọmọ Israẹli kò ha dàbí àwọn ọmọ Kuṣi sí mi?” ni Olúwa wí. “Èmi kò ha ti mú Israẹli gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti jáde wá àti àwọn Filistini láti ilẹ̀ Kafitori àti àwọn ará Aramu láti Kiri?
Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili fi dunu! Na da Suda: ne dunu ilima asigisa, dilima asigisu defele. Na da dili Idibidi sogega oule misi, amo defele Na da Filisidini dunu Galidi sogega gadili oule misi amola Na da Silia dunu Ge sogega gadili oule misi.
8 “Dájúdájú, ojú Olúwa Olódùmarè ń bẹ̀ lára ilẹ̀ ọba tó kún fún ẹ̀ṣẹ̀. Èmi yóò pa á run kúrò lórí ilẹ̀. Síbẹ̀, Èmi kò nípa ilé Jakọbu run pátápátá,” ni Olúwa wí.
Na, Ouligisudafa Hina Gode, da wadela: i hamosu Isala: ili dunu fi amo ba: lala. Na da ili osobo bagadega bu hame ba: ma: ne dafawanedafa ili wadela: lesimu. Be Ya: igobe ea fi huluanedafa Na da hame wadela: lesimu. Dunu eno bagahame da esalumu.
9 “Nítorí Èmi yóò pàṣẹ, Èmi yóò sì mi ilé Israẹli ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè bí a ti ń jọ nǹkan nínú ajọ̀ tí hóró kín ń kín kì yóò bọ́ sórí ilẹ̀.
Na da wadela: musa: sia: ne, na da Isala: ili dunu amo gagoma gasa: le legesu ganodini igugusa amo defele ili igugumu. Na da wadela: i dunu fadegamusa: , ili fifi asi gala huluane amo ganodini Isala: ili dunu igugumu.
10 Gbogbo àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ láàrín àwọn ènìyàn mi ni yóò ti ipa idà kú gbogbo àwọn ti ń wí pé, ‘Aburú kì yóò lé wa bá, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò ká wa mọ́.’
Wadela: i hamosu dunu Na fi amo ganodini huluane da gegesu ganodini fane legei dagoi ba: mu. Amo wadela: i dunu da mae dawa: iwane amane sia: sa, “Hina Gode da ninia se nabasu mae ba: ma: ne, eso huluane nini gaga: mu.”
11 “Ní ọjọ́ náà ní Èmi yóò gbé àgọ́ Dafidi tí ó wó ró, Èmi yóò dí odi rẹ̀ tí ó ya, Èmi yóò sì gbé ahoro rẹ̀ sókè, Èmi yóò sì kọ bí ti ọjọ́ ìgbàanì,
Hina Gode da amane sia: sa, “Eso da misunu, amoga Na da Da: ibidi ea hina bagade hou amola ea fi (wali amo da diasu mugului dagoi agoane ba: sa) amo bu hahamomu. Na da ea dobea bu hahamomu amola amo fi da ilia musa: hou defele ba: mu.
12 kí wọn le jogún ìyókù Edomu àti gbogbo àwọn kèfèrí, ti a ń pè nípa orúkọ mi,” ni Olúwa, ẹni tí yóò ṣe nǹkan wọ̀nyí wí.
Amasea, Isala: ili dunu da Idome soge la: di diala amo hasalimu amola soge fi musa: Na gagui amoga hasalasimu,” Hina Gode E da amo hamomusa: amane sia: sa.
13 “Ọjọ́ náà ń bọ,” ni Olúwa wí, “tí ẹni tí ń tulẹ̀ yóò lé ẹni tí ń kórè bá. Tí ẹni tí ń fún èso àjàrà yóò lé ẹni tí ń gbìn bá. Àwọn òkè ńlá yóò sì kán ọtí wáìnì sílẹ̀, tí yóò sì sàn láti ara àwọn òkè kéékèèké.
Hina Gode da amane sia: sa, “Eso da misunu amoga widi amola gagoma amola ha: i manu huluane da hedolowane heda: le, yoi hamobeba: le, huluane faimu da hamedei ba: mu. Waini fage da hedolowane legele, yoi hamobeba: le, huluane amoga waini hamomu da hamedei ba: mu. Goumiga waini hano ea hedai da ula agoane dadadisa ahoanebe ba: mu. Agologa waini hano da hano nawa: li agoane ahoanebe ba: mu.
14 Èmi yóò si tún mú ìgbèkùn Israẹli ènìyàn mi padà bọ̀. “Wọn yóò sì kọ́ ahoro ìlú, wọn yóò sì máa gbé inú wọn. Wọn yóò sì gbin ọgbà àjàrà, wọn yóò sì mu ọtí wáìnì wọn wọn yóò sì ṣe ọgbà pẹ̀lú, wọn yóò sì jẹ èso inú wọn.
Na da Na fi dunu ilia sogega bu oule misunu. Ilia moilai bai bagade wadela: lesi amo ilia da bu hahamomu. Amola ilia da amo ganodini esalumu. Ilia da waini efe sagamu amola amoga waini hamoi manu. Ilia da ifabia sagamu amola amo ea ha: i manu fai manu.
15 Èmi yóò gbin Israẹli sí orí ilẹ̀ rẹ̀. A kì yóò sì fà wọn tu mọ́ láéláé kúrò ni orí ilẹ̀ ti mo fi fún wọn,” ni Olúwa Ọlọ́run rẹ wí.
Na da Na fi amo soge Na da ilima i, amoga Na da Na fi bu bugimu. Enoga bu fadegamu da bu hamedafa ba: mu.” Dilia Hina Gode da sia: i dagoi. Sia: ama dagoi

< Amos 9 >