< Amos 8 >

1 Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè fihàn mi: agbọ̀n èso pípọ́n.
Mwathani Jehova aanyonirie ũũ: aanyonirie gĩkabũ kĩrĩ na matunda meeru.
2 Ó béèrè pé, “Amosi kí ni ìwọ rí.” Mo sì dáhùn pé, “Agbọ̀n èso pípọ́n.” Nígbà náà ni Olúwa wí fún mi pé, “Àsìkò náà pọ́n tó fún àwọn ènìyàn mi Israẹli; Èmi kì yóò dá wọn sí mọ́.”
Nake akĩnjũũria atĩrĩ, “Amosi, nĩ kĩĩ kĩu ũroona?” Ngĩmũcookeria atĩrĩ, “Ndĩrona gĩkabũ kĩrĩ na matunda meeru.” Ningĩ Jehova akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Ihinda rĩa mũthia nĩ ikinyu rĩa andũ akwa a Isiraeli; ndigacooka kũmaiguĩra tha rĩngĩ.”
3 Olúwa Olódùmarè wí pé, “Ní ọjọ́ náà, àwọn orin tẹmpili yóò yí padà sí ohùn réré ẹkún. Ọ̀pọ̀, àní ọ̀pọ̀ ara òkú ni yóò wà ni ibi gbogbo! Àní ni ìdákẹ́ jẹ́ẹ́!”
Mwathani Jehova ekuuga atĩrĩ, “Mũthenya ũcio-rĩ, nyĩmbo iria ciinagwo kũu hekarũ-inĩ ikaagarũrũka ituĩke kĩrĩro. Ciimba nyingĩ mũno igaateagwo kũndũ guothe gũkirĩtwo ki!”
4 Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yin tí ń tẹ aláìní lórí ba, tí ẹ sì ń sọ tálákà di ilẹ̀.
Iguai ũndũ ũyũ inyuĩ arĩa mũrangagĩrĩria abatari na mũkaniina athĩĩni a bũrũri,
5 Tí ẹ ń wí pé, “Nígbà wo ni oṣù tuntun yóò parí kí àwa bá à lè ta ọkà kí ọjọ́ ìsinmi kí ó lè dópin kí àwa bá à le ta jéró?” Kí a sì dín ìwọ̀n wa kù kí a gbéraga lórí iye tí a ó tà á kí a sì fi òsùwọ̀n èké yàn wọ́n jẹ,
mũkĩũragia atĩrĩ, “Karũgamo ka Mweri gagaathira-rĩ, nĩguo twendie irio, na Thabatũ ĩthire, nĩguo twendie ngano, tũkĩnyiihagia ithimi, tũkĩongagĩrĩra thogora, na tũkĩheenanagia na ratiri itarĩ cia ma;
6 kí àwa lè fi fàdákà ra àwọn tálákà, kí a sì fi bàtà ẹsẹ̀ méjèèjì ra aláìní, kí a sì ta jéró tí a kó mọ́ ilẹ̀.
tũgũrage athĩĩni na betha, nao arĩa abatari tũkamagũra na nyamũga igĩrĩ, o na twendagie magira hamwe na ngano.”
7 Olúwa ti fi ìgbéraga Jakọbu búra pé, “Èmi kì yóò gbàgbé ọ̀kan nínú ohun tí wọ́n ṣe.
Jehova o we ũrĩa Jakubu etĩĩagĩra, ehĩtĩte akoiga atĩrĩ, “Ndirĩ hĩndĩ ngariganĩrwo nĩ ciĩko ciothe iria maneeka.
8 “Ǹjẹ́ ilẹ̀ náà kì yóò ha wárìrì fún èyí? Àwọn tí ń gbé inú rẹ̀ kì yóò ha ṣọ̀fọ̀? Gbogbo ilẹ̀ yóò ru sókè bí omi Naili, yóò sì ru ú sókè pátápátá bí ìkún omi a ó sì tì í jáde, a ó sì tẹ̀ ẹ́ rì gẹ́gẹ́ bí odò Ejibiti.
“Githĩ bũrũri ndũkainaina nĩ ũndũ wa ũguo, na arĩa othe matũũraga kuo macakae? Bũrũri wothe nĩkũiyũra ũkaiyũra ta Rũũĩ rwa Nili, ũhũũrane, na ũcooke ũhũũcũke ta rũũĩ rwa Misiri.”
9 “Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa Olódùmarè wí, “Èmi yóò mú oòrùn wọ̀ ní ọ̀sán, Èmi yóò mú kí ayé ṣókùnkùn ní ọ̀sán gangan.
Mwathani Jehova ekuuga atĩrĩ, “Mũthenya ũcio-rĩ, “nĩngatũma riũa rĩthũe mĩaraho, na ndũme thĩ kũgĩe nduma mũthenya barigici.
10 Èmí yóò yí àsè ẹ̀sìn yín padà sí ọ̀fọ̀, gbogbo orin yín ni èmi yóò sọ di ẹkún. Èmi yóò mú kí gbogbo yín wọ aṣọ ọ̀fọ̀, kí a sì fá orí yín. Èmi yóò mú kí ìgbà náà rí bí ìṣọ̀fọ̀ fún ọmọkùnrin kan ṣoṣo tí a bí àti òpin rẹ̀ bí ọjọ́ kíkorò.
Nĩngagarũra ciathĩ cianyu ituĩke macakaya, na kũina kwanyu guothe gũtuĩke kĩrĩro. Nĩngatũma inyuothe mwĩhumbe makũnia, na ndĩmwenje mĩtwe. Nĩngatũma ihinda rĩu rĩhaane ta hĩndĩ ya macakaya ma mwana wa mũmwe, naguo mũthia warĩo ũtuĩke ta mũthenya mũrũrũ.”
11 “Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa Olódùmarè wí, “nígbà tí èmi yóò rán ìyàn sí ilẹ̀ náà, kì í ṣe ìyàn oúnjẹ tàbí òǹgbẹ fún omi. Ṣùgbọ́n ìyàn gbígbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
Mwathani Jehova ekuuga atĩrĩ: “Matukũ nĩmarooka, rĩrĩa ngaatũma ngʼaragu bũrũri-inĩ, na ti ngʼaragu ya irio kana nyoota wa maaĩ, no nĩ ngʼaragu ya kũigua ciugo cia Jehova.
12 Àwọn ènìyàn yóò rìn kiri láti Òkun dé Òkun wọn yóò sì máa rìn ká láti gúúsù sí àríwá, wọn yóò máa wá ọ̀rọ̀ Olúwa ṣùgbọ́n wọn kì yóò rí i.
Andũ magaatũgũũgaga kuuma iria-inĩ rĩmwe nginya rĩrĩa rĩngĩ, na morũũrage kuuma gathigathini nginya irathĩro, magĩcaria kiugo kĩa Jehova, no matigakĩona.
13 “Ní ọjọ́ náà “àwọn arẹwà wúńdíá àti àwọn alágbára ọ̀dọ́mọkùnrin yóò dákú fún òǹgbẹ omi.
“Mũthenya ũcio-rĩ, “airĩtu arĩa ciĩrorerwa na aanake arĩa marĩ hinya nĩmakaringĩka nĩ nyoota.
14 Àwọn tí ó fi ẹ̀ṣẹ̀ Samaria búra, tí wọ́n sì wí pé, ‘Bí ó ti dájú pé ọlọ́run rẹ ń bẹ láààyè, ìwọ Dani,’ bí ó ti dájú pè ọlọ́run rẹ ń bẹ láààyè, ìwọ Beerṣeba, wọ́n yóò ṣubú, wọn kì yóò si tún dìde mọ.”
Acio mehĩtaga na thoni cia Samaria, kana makoiga atĩrĩ, ‘Ti-itherũ o ta ũrĩa ngai ĩyo yaku ĩtũũraga muoyo wee Dani’, o na kana makoiga atĩrĩ, ‘Ti-itherũ o ta ũrĩa ngai ĩyo ya Birishiba itũũraga muoyo’: nĩmakaagũa, na maticooke gũũkĩra rĩngĩ.”

< Amos 8 >