< Amos 8 >

1 Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè fihàn mi: agbọ̀n èso pípọ́n.
Ka Boeipa Yahovah loh kai te n'tueng vaengah khohal kam boem tarha om.
2 Ó béèrè pé, “Amosi kí ni ìwọ rí.” Mo sì dáhùn pé, “Agbọ̀n èso pípọ́n.” Nígbà náà ni Olúwa wí fún mi pé, “Àsìkò náà pọ́n tó fún àwọn ènìyàn mi Israẹli; Èmi kì yóò dá wọn sí mọ́.”
Te vaengah, “Amos balae na hmuh?” a ti tih, “Khohal boem,” ka ti nah. Te dongah BOEIPA loh kai taengah, “Ka pilnam Israel kah a bawtnah a pha coeng, anih te poeng hamla koep ka koei mahpawh.
3 Olúwa Olódùmarè wí pé, “Ní ọjọ́ náà, àwọn orin tẹmpili yóò yí padà sí ohùn réré ẹkún. Ọ̀pọ̀, àní ọ̀pọ̀ ara òkú ni yóò wà ni ibi gbogbo! Àní ni ìdákẹ́ jẹ́ẹ́!”
Khothaih ah bawkim kah laa neh rhung uh ni. Te tah ka Boeipa Yahovah kah olphong ni. Hmuen takuem ah rhok te a huep la muep a voeih ni.
4 Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yin tí ń tẹ aláìní lórí ba, tí ẹ sì ń sọ tálákà di ilẹ̀.
Khodaeng aka hloem tih khohmuen kah mangdaeng kodo aka kangkuen te he he hnatun uh.
5 Tí ẹ ń wí pé, “Nígbà wo ni oṣù tuntun yóò parí kí àwa bá à lè ta ọkà kí ọjọ́ ìsinmi kí ó lè dópin kí àwa bá à le ta jéró?” Kí a sì dín ìwọ̀n wa kù kí a gbéraga lórí iye tí a ó tà á kí a sì fi òsùwọ̀n èké yàn wọ́n jẹ,
“Me vaengah nim hla a boeih vetih cangtham n'yoih ve. Sabbath laeh vetih cangpai n'ong laeh mako. Cangnoek khaw rhaidaeng la, shekel khaw a puehkan mai la, thailatnah te cooi aka khun mai la.
6 kí àwa lè fi fàdákà ra àwọn tálákà, kí a sì fi bàtà ẹsẹ̀ méjèèjì ra aláìní, kí a sì ta jéró tí a kó mọ́ ilẹ̀.
Tattloel te tangka neh, khodaeng khaw khokhom neh lai ham tih cang hi yoih ham,” a thui.
7 Olúwa ti fi ìgbéraga Jakọbu búra pé, “Èmi kì yóò gbàgbé ọ̀kan nínú ohun tí wọ́n ṣe.
BOEIPA loh Jakob kah hoemdamnah neh a toemngam coeng. Amih kah khoboe boeih te a yoeyah la ka hnilh mahpawh.
8 “Ǹjẹ́ ilẹ̀ náà kì yóò ha wárìrì fún èyí? Àwọn tí ń gbé inú rẹ̀ kì yóò ha ṣọ̀fọ̀? Gbogbo ilẹ̀ yóò ru sókè bí omi Naili, yóò sì ru ú sókè pátápátá bí ìkún omi a ó sì tì í jáde, a ó sì tẹ̀ ẹ́ rì gẹ́gẹ́ bí odò Ejibiti.
He dongah nim diklai a tlai pawt eh? A khuikah khosa boeih loh nguekcoi vetih a pum la sokko bangla phul ni. A samboek tih a sul phoeiah tah Egypt sokko bangla rhaeng ni.
9 “Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa Olódùmarè wí, “Èmi yóò mú oòrùn wọ̀ ní ọ̀sán, Èmi yóò mú kí ayé ṣókùnkùn ní ọ̀sán gangan.
Te khohnin ah ka Boeipa Yahovah kah olphong pai ni. Khomik te khothun ah ka tlak sak vetih khothaih khosae ah diklai te ka hmuep sak ni.
10 Èmí yóò yí àsè ẹ̀sìn yín padà sí ọ̀fọ̀, gbogbo orin yín ni èmi yóò sọ di ẹkún. Èmi yóò mú kí gbogbo yín wọ aṣọ ọ̀fọ̀, kí a sì fá orí yín. Èmi yóò mú kí ìgbà náà rí bí ìṣọ̀fọ̀ fún ọmọkùnrin kan ṣoṣo tí a bí àti òpin rẹ̀ bí ọjọ́ kíkorò.
Nangmih kah khotue te nguekcoinah la, na lumlaa boeih rhahlung la ka maelh ni. Cinghen tom ah tlamhni kan yen vetih na lu boeih te lungawng la om ni. Anih te oingaih cangloeng kah nguekcoinah bangla, a hmailong te khahing khohnin bangla ka khueh ni.
11 “Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa Olódùmarè wí, “nígbà tí èmi yóò rán ìyàn sí ilẹ̀ náà, kì í ṣe ìyàn oúnjẹ tàbí òǹgbẹ fún omi. Ṣùgbọ́n ìyàn gbígbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
Ka Boeipa Yahovah kah olphong hnin pai coeng he. Te dongah diklai ah khokha ka tueih ni. Buh kah khokha pawt tih tui dongah tuihalh bal moenih. Tedae BOEIPA ol yaak nah te ni.
12 Àwọn ènìyàn yóò rìn kiri láti Òkun dé Òkun wọn yóò sì máa rìn ká láti gúúsù sí àríwá, wọn yóò máa wá ọ̀rọ̀ Olúwa ṣùgbọ́n wọn kì yóò rí i.
Tuitunli lamloh tuitunli duela hinghuen uh ni. BOEIPA ol te tlap hamla tlangpuei lamloh khocuk duela hil uh cakhaw hmu uh mahpawh.
13 “Ní ọjọ́ náà “àwọn arẹwà wúńdíá àti àwọn alágbára ọ̀dọ́mọkùnrin yóò dákú fún òǹgbẹ omi.
Te khohnin ah tah oila sakthen neh tongpang khaw tuihalh dongah saa uh ni.
14 Àwọn tí ó fi ẹ̀ṣẹ̀ Samaria búra, tí wọ́n sì wí pé, ‘Bí ó ti dájú pé ọlọ́run rẹ ń bẹ láààyè, ìwọ Dani,’ bí ó ti dájú pè ọlọ́run rẹ ń bẹ láààyè, ìwọ Beerṣeba, wọ́n yóò ṣubú, wọn kì yóò si tún dìde mọ.”
Samaria kah dumlai neh aka toemngam rhoek long khaw, “Dan nang kah pathen tah hing tih Beersheba longpuei khaw hing,” ti uh. Tedae cungku vetih koep thoo mahpawh.

< Amos 8 >