< Amos 6 >

1 Ègbé ni fún ẹ̀yin tí ará rọ̀ ní Sioni àti ẹ̀yin tí ẹ wà ní abẹ́ ààbò ní òkè Samaria àti ẹ̀yin olókìkí orílẹ̀-èdè tí ẹ̀yin ènìyàn Israẹli máa ń tọ̀ ọ́ wá.
Asigi bagadedafa, dilia Yelusaleme soge ganodini noga: ledafa esalusu amola Samelia fi ganodini dilia da agoane dawa: sa, “Nowa da nini wadela: lesima: bela: ?’ Isala: ili fi da fi bagade amola ilia asigilai dunu da bagadeba: le, dunu eno da ilima fidisu lama: ne maha, ilisu da agoane dawa: sa. Be ilia da se bagade nabimu.
2 Ẹ lọ Kalne kí ẹ lọ wò ó kí ẹ sí tí ibẹ̀ lọ sí Hamati ìlú ńlá a nì. Kí ẹ sì tún sọ̀kalẹ̀ lọ Gati ní ilẹ̀ Filistini. Ǹjẹ́ wọ́n ha dára ju ìpínlẹ̀ yín méjèèjì lọ? Ǹjẹ́ a ha rí ilẹ̀ tó tóbi ju tiyín lọ bí?
Asili amola Ga: lane moilai bai bagade fi amo ba: la masa. Amalu Ha: ima: de osobo dogone fi bagade amoga masa, amola Filisidini soge ganodini Ga: de moilai bai bagade fi amo ba: la masa. Amo osobo dogone fi ilia hou Yuda amola Isala: ili ilia hou baligibala: ? Ma ilia soge alalo ilegei amo da dilia soge alalo ilegei baligibala: ? Hame mabu!
3 Ẹ̀yin sún ọjọ́ ibi síwájú, ẹ sì mú ìjọba òǹrorò súnmọ́ tòsí.
Dilia soge da wadela: mu amo dilia da dafawaneyale hame dawa: Be dilia wadela: i hou da amo wadela: mu eso hedolo misa: ne fidisa.
4 Ẹ̀yin sùn lé ibùsùn tí a fi eyín erin ṣe ẹ sì tẹ́ ara sílẹ̀ ni orí àwọn ibùsùn ẹyin pa èyí tí o dára nínú àwọn ọ̀dọ́-àgùntàn yín jẹ ẹ sì ń pa àwọn ọ̀dọ́ màlúù láàrín agbo wọn jẹ.
Dilia muni bagade gagui dunu dilia noga: le sesei da: iya goladiaha amola bulamagau mano amola sibi mano hu noga: le naha, be dilia dawa: ma! Dilia da se bagade nabimu.
5 Ẹ̀yin ń lo ohun èlò orin bí i Dafidi ẹ sì ń ṣe àwọn àpilẹ̀rọ àwọn ohun èlò orin.
Dilia da gesami hea: musa: gesami gaheabolo muni hamosa, amo da Da: ibidi ea hamoi defele, amola dusu amo duni hea: sa.
6 Ẹ̀yin mu wáìnì ẹ̀kún ọpọ́n kan àti ìkunra tí o dára jùlọ ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò káàánú ilé Josẹfu tí ó di ahoro.
Dilia da ofodo waini hano amo nabale dili naha, amola dilia da: i amoma gabusiga: waea ulawane noga: i ba: sa, be Isala: ili fi da wadela: lesi dagoiba: le dilia da ilima hame asigisa.
7 Nítorí náà, àwọn ni yóò lọ sí ìgbèkùn pẹ̀lú àwọn tí ó ti kó lọ sí ìgbèkùn àsè àwọn tí ń ṣe àṣelékè ni a ó mú kúrò.
Amaiba: le dili da hidadea ga se iasu diasu soge ganodini amoga mugululi masunu. Amola dilia lolo nabe dilia da bu hame ba: mu.
8 Olúwa Olódùmarè ti búra fúnra rẹ̀, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun sì ti wí pé: “Mo kórìíra ìgbéraga Jakọbu n kò sì ní inú dídùn sí odi alágbára rẹ̀, Èmi yóò sì fa ìlú náà lé wọn lọ́wọ́ àti ohun gbogbo tí ó wà nínú rẹ̀.”
Ouligisudafa Hina Gode Bagadedafa da amo sisasudafa sia: i dagoi, “Na da Isala: ili fi dunu ilia hidale gasa fi hou bagade higasa. Na da ilia diasu noga: idafa amola higasa. Na da ilia diasu osobo dogone bagade amola amo ganodini liligi huluane amo ilia ha lai dunu ilima imunu.”
9 Bí ọkùnrin mẹ́wàá bá ṣẹ́kù nínú ilé kan, àwọn náà yóò kú.
Be sosogo fi ganodini, dunu nabuane agoane hame bogoi esalebe ba: sea, ilia da huluane bogomu.
10 Bí ẹbí tí ó yẹ kí ó gbé òkú wọn jáde fún sínsin bá wọlé, bí o ba sì béèrè pé ǹjẹ́ ẹnìkan wa tí ó fi ara pamọ́ níbẹ̀, “Ǹjẹ́ ẹnìkankan wà lọ́dọ̀ yín?” tí ó bá sì dáhùn wí pé, “Rárá,” nígbà náà ni yóò wí pé, “Pa ẹnu rẹ mọ́ àwa kò gbọdọ̀ dárúkọ Olúwa.”
Dunu bogoi amo ea sosogo fi amola bogoi da: iya misi amo ouligisu dunu e da bogoi da: i amo diasu ganodini dialebe amo lale moiga agoane masunu. Amola bogoi amoea sosogo fi ilima ea amane naba ba: mu, “Diasu ganodini da nowa fawane yolesibala?” E da sia: amane nabimu, “Hame!” sosogo fi ilia da amane sia: mu. Amasea, bogoi da: iya ouligisu da agoane sia: mu. “Ouiya: ma! Ninia da noga: le dawa: mu da defea. Hina Gode Ea Dio mae sia: ma.”
11 Nítorí Olúwa tí pa àṣẹ náà, Òun yóò sì wó ilé ńlá náà lulẹ̀ túútúú, àti àwọn ilé kéékèèké sí wẹ́wẹ́.
Hina Gode da liligi wadela: lesima: ne sia: sea, diasu bagade amola fonobahadi amo mugululi fofonobone, goudai dagoi ba: mu.
12 Ǹjẹ́ ẹṣin a máa sáré lórí àpáta bí? Ǹjẹ́ ènìyàn a máa fi akọ màlúù kọ ilẹ̀ níbẹ̀? Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti yí òtítọ́ padà sí májèlé ẹ sì ti sọ èso òdodo di ìkorò.
Hosi ea da igi bagade gilisi amodili da hehenaia masa: bela: ? Ma dunu ilia da hano wayabo bagade amogai osobo gidinasuga, wayabo amogai da dogoma: bela: ? Be dilia da hou noga: i amo afadenene, fedege agoane medosu hano defele hamoi, amola molole fofada: su amo wadela: lesi dagoi.
13 Ẹ̀yin yọ̀ torí ìṣẹ́gun lórí Lo-Debari, ẹ̀yin sì wí pé, “Ṣé kì í ṣe agbára wa ni àwa fi gba Karnaimu?”
Dilia da Loudiba osobo dogone fi amoga hasalasiba: le hidale sia: sa. Amaiba: le, dilisu dilia hou amo gadodafa hidale gaguia gadoi, amola gasa fi bagade hamosa. Dilia da gasa fili agoane sia: sa, “Ninia da Gana: ime osobo dogone fi ilima hasalasili ouligimu defele esala.”
14 Nítorí Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Èmi yóò gbé orílẹ̀-èdè kan dìde sí ọ ìwọ Israẹli, wọn yóò pọ́n yín lójú ní gbogbo ọ̀nà, láti Lebo-Hamati, títí dé pẹ̀tẹ́lẹ̀ Arabah.”
Hina Gode Bagadedafa Hisu da amane sia: sa, “Isala: ili fi dunu! Na da gegesu dunu soge enoga fi amo dilia soge bagade gogami asunasimu amola dilia da soge hame ganumu. Amo gegesu dunu da dilima hasalasimu. Ilia da dilia soge huluane amo ganodini dili banenesimu - amo soge da Ha: ima: de adobo gigadofa ahoasu ga (north) la: di asili la: di goega (south) alalo A: laba Fago doaga: sa.”

< Amos 6 >