< Amos 3 >

1 Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ tí Olúwa ti sọ nípa rẹ̀, ẹ̀yin ènìyàn Israẹli nípa àwọn ìdílé tí mo mú jáde láti Ejibiti:
Pǝrwǝrdigar silǝrni ǝyiblǝp eytⱪan bu sɵz-kalamni anglanglar, i Israil baliliri, Yǝni Mǝn Misir zeminidin elip qiⱪarƣan bu pütkül jǝmǝt: —
2 “Ìwọ nìkan ni ẹni tí mo yàn nínú gbogbo àwọn ìran ayé yìí; nígbà náà èmi ó jẹ ọ́ ní yà fún gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ.”
«Yǝr yüzidiki barliⱪ jǝmǝtlǝr arisidin pǝⱪǝt silǝrni tonup kǝldim; Xunga üstünglarƣa barliⱪ ⱪǝbiⱨlikliringlarning [jazasini] qüxürimǝn».
3 Ẹni méjì ha à le rìn pọ̀ láìjẹ́ pé wọ́n ti pinnu láti ṣe bẹ?
Ikki kixi bir niyǝttǝ bolmisa, ⱪandaⱪmu billǝ mangalisun?
4 Ǹjẹ́ Kìnnìún yóò ha bú ramúramù nínú igbó, bí kò bá ní ohun ọdẹ? Ọmọ kìnnìún yóò ha ké jáde nínú ìhó rẹ̀ bí kò bá rí ohun kan mú?
Oljisi yoⱪ xir ormanda ⱨɵrkirǝmdu? Arslan ⱨeqnemini almiƣan bolsa uwisida ⱨuwlamdu?
5 Ǹjẹ́ ẹyẹ ṣubú sínú okùn ọdẹ lórí ilẹ̀ nígbà tí a kò dẹ okùn ọdẹ fún un? Okùn ọdẹ ha lè hù jáde lórí ilẹ̀ nígbà tí kò sí ohun tí yóò mú?
Tuzaⱪta yǝmqük bolmisa ⱪux yǝrgǝ yiⱪilamdu? Alƣudǝk nǝrsǝ bolmisa, ⱪismaⱪ yǝrdin etilip qiⱪamdu?
6 Nígbà tí ìpè bá dún ní ìlú, àwọn ènìyàn kò ha bẹ̀rù? Tí ewu bá wa lórí ìlú kò ha ṣe Olúwa ni ó fà á?
Xǝⱨǝrdǝ [agaⱨ] kaniyi qelinsa, hǝlⱪ ⱪorⱪmamdu? Pǝrwǝrdigar ⱪilmiƣan bolsa, xǝⱨǝrgǝ yamanliⱪ qüxǝmdu?
7 Nítòótọ́ Olúwa Olódùmarè kò ṣe ohun kan láìfi èrò rẹ̀ hàn fun àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ̀.
Rǝb Pǝrwǝrdigar Ɵz ⱪulliri bolƣan pǝyƣǝmbǝrlǝrgǝ awwal axkarilimay turup, U ⱨeq ix ⱪilmaydu.
8 Kìnnìún ti bú ramúramù ta ni kì yóò bẹ̀rù? Olúwa Olódùmarè ti sọ̀rọ̀ ta ni le ṣe àìsọ àsọtẹ́lẹ̀?
Xir ⱨɵrkirigǝn tursa, kim ⱪorⱪmaydu? Rǝb Pǝrwǝrdigar sɵz ⱪilƣanda, kim [Uning] bexaritini yǝtküzmǝy turalaydu?
9 Ẹ kéde ní ààfin Aṣdodu àti ní ààfin ní ilẹ̀ Ejibiti. “Ẹ kó ara yín jọ sí orí òkè ńlá Samaria; kí ẹ sì wo ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ńlá láàrín rẹ̀ àti ìnilára láàrín àwọn ènìyàn rẹ.”
Axdodtiki ⱪǝl’ǝ-ordilarda, Xundaⱪla Misirdiki ⱪǝl’ǝ-ordilarda elan ⱪilip: — «Samariyǝ taƣliri üstidǝ yiƣilinglar, Uning otturisidiki zor ⱪiyⱪas-sürǝnlǝrni, Uning iqidiki jǝbir-zulumlarni kɵrüp beⱪinglar» — dǝnglar.
10 “Wọn kò mọ bí wọ́n ṣe ń ṣe rere,” ni Olúwa wí, “àwọn ẹni tí ó gba àwọn ìwà ipá àti olè sí ààfin rẹ̀.”
— Ular ⱨǝⱪ ix ⱪilixni bilmǝydu — dǝydu Pǝrwǝrdigar, — Ular ordiliriƣa zulum-zorawanliⱪ bilǝn tartiwalƣanlirini ⱨǝm oljilarni juƣliƣuqilar!
11 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: “Àwọn ọ̀tá yóò pa ilẹ̀ náà run; yóò wó ibi gíga yín palẹ̀ a ó sì ba ààfin rẹ̀ jẹ́.”
Xunga Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — «Mana bir yaw! U zeminni ⱪorxiwaldi! U mudapiǝngni elip taxlaydu, Ⱪǝl’ǝ-ordiliring bulang-talang ⱪilinidu.
12 Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Bí olùṣọ́-àgùntàn ti ń gbà itan méjì kúrò ní ẹnu kìnnìún tàbí ẹ̀là etí kan bẹ́ẹ̀ ni a ó mú àwọn ọmọ Israẹli, tí ń gbé Samaria kúrò ní igun ibùsùn wọn ní orí àga ìrọ̀gbọ̀kú wọn ní Damasku.”
Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Padiqi xirning aƣzidin ⱪoyning ikki putini yaki ⱪuliⱪining bir parqisini ⱪutⱪuzup alƣandǝk, Samariyidǝ olturƣan Israillarmu xundaⱪ ⱪutⱪuzulidu, — Xǝⱨǝrdǝ pǝⱪǝt kariwatning bir burjiki, Diwandiki bir parqǝ Dǝmǝxⱪ libasila ⱪalidu!
13 “Gbọ́ èyí kí o sì jẹ́rìí nípa ilé Jakọbu,” ni Olúwa wí, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun.
— Anglanglar, Yaⱪupning jǝmǝtidǝ guwaⱨliⱪ beringlar, — dǝydu Rǝb Pǝrwǝrdigar, samawi ⱪoxunlarning Sǝrdari bolƣan Huda,
14 “Ní ọjọ́ tí mo fìyà jẹ Israẹli lórí ẹ̀ṣẹ̀ wọn, Èmi yóò pa pẹpẹ Beteli run; ìwo pẹpẹ ni a ó ké kúrò yóò sì wó lulẹ̀.
— Mǝn Israilning asiyliⱪlirini ɵz bexiƣa qüxürgǝn künidǝ, Bǝyt-Əl xǝⱨirining ⱪurbangaⱨlirinimu jazalaymǝn; Ⱪurbangaⱨning burjǝkliridiki münggüzlǝr kesiwetilip yǝrgǝ qüxürülidu.
15 Èmi yóò wó ilé òtútù lulẹ̀ pẹ̀lú ilé ooru; ilé tí a fi eyín erin ṣe lọ́ṣọ̀ọ́ yóò ṣègbé a ó sì pa ilé ńlá náà run,” ni Olúwa wí.
Mǝn «Ⱪixliⱪ Saray» wǝ «Yazliⱪ Saray»ni biraⱪla uruwetimǝn; Pil qixi ɵylǝrmu yoⱪilip ketidu, Kɵpligǝn ɵylǝr tügixidu, — dǝydu Pǝrwǝrdigar.

< Amos 3 >