< Amos 2 >

1 Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta ti Moabu, àní fún mẹ́rin, Èmi kò ní yí ìpinnu ìjìyà mi padà, nítorí ó ti sun ún, di eérú, egungun ọba Edomu,
Hagi Ra Anumzamo'a amanage hu'ne, Moapu vahe'mo'za kumira huvava hu'za vazankina, amane zamatrenuge'za omanigahazanki, kna zamina zamazeri haviza hugahue. Na'ankure zamagra Idomu vahe kini ne'mofo zaferina eri'za tevefi krazageno tanefa'sene.
2 Èmi yóò rán iná sí orí Moabu èyí tí yóò jó àwọn ààfin Kerioti run. Moabu yóò sì kú pẹ̀lú ariwo pẹ̀lú igbe àti pẹ̀lú ìró ìpè.
E'ina hu'nagu Nagra teve taginte'nugeno Moapu kumara tevea nerenkeno, Kerioti kumamofo hanave vihu kegina tevemo te hana hugahie. Ha' vahezmimo'za ivimo agazamo'ma hu'za Moapu vahe'ma eme zamahesaza agasasane ufe krafa kenena antahigahaze.
3 Èmi yóò ké onídàájọ́ rẹ̀ kúrò, Èmi yóò sì pa gbogbo àwọn ọmọ-aládé rẹ́ nínú rẹ̀,” ni Olúwa wí.
Hagi kini vahe'zamine maka kva vahezminena zamahe hana hugahue huno Ra Anumzamo'a hu'ne.
4 Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta ti Juda, àní fún mẹ́rin, Èmi kò ní yí ìpinnu ìjìyà mi padà. Nítorí wọn ti kọ òfin Olúwa sílẹ̀, wọn kò sì pa àwọn ìlànà rẹ̀ mọ́. Nítorí àwọn òrìṣà ti sì wọ́n lọ́nà, òrìṣà tí àwọn Baba ńlá wọn ń tẹ̀lé,
Hagi Ra Anumzamo'a amanage hu'ne, Juda vahe'mo'za kumira huvava hu'za vazankina amane zamatrenuge'za omanigahazanki knaza zamigahue. Na'ankure zamagra Ra Anumzamo'na kasegea zamefi hunenamiza tra kea ovariri'naze. Hagi zamagehe'ima zamazeri savri'ma hu'naza havigereti zamazeri savri hazage'za, havi anumzantera monora hunte'naze.
5 Èmi yóò rán iná sí orí Juda èyí tí yóò jó àwọn ààfin Jerusalẹmu run.”
E'ina hu'nagu Nagra Juda kumara teve tagintenugeno nereno hanave vihu keginama hugagi'naza Jerusalemi kumara teno eri hana hugahie.
6 Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta Israẹli àní fún mẹ́rin, Èmi kò ní yí ìpinnu ìjìyà mi padà. Wọ́n ta olódodo fún fàdákà àti aláìní fún bàtà ẹsẹ̀ méjèèjì.
Hagi Ra Anumzamo'a amanage hu'ne, Israeli vahe'mo'za kumira huvava hu'za vazanki'na amane zamatrenuge'za omanigahazanki kna zamina zamazeri haviza hugahue. Na'ankure zamagra fatgo vahera zagore nezamatre'za zamunte omane vahera zamaga nonte nona hu'za zamatre'naze.
7 Wọ́n fi ẹsẹ̀ tẹ orí àwọn tálákà mọ́lẹ̀, bí wọ́n ti ń tẹ erùpẹ̀ ilẹ̀ tí wọ́n ko sì ṣe òtítọ́ si àwọn tí a ni lára. Baba àti ọmọ ń wọlé tọ wúńdíá kan náà, láti ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́.
Hagi zamagra zamunte omane vahera zamasunkura huozmante kugusopafi zamare hapati atre'naze. Hagi nefa'ma anteno masea mofara nemofo'a ana mofake anteno masene. E'ina nehu'za ruotge'ma hu'nea Nagia eri haviza hu'naze.
8 Wọ́n dùbúlẹ̀ lẹ́bàá a pẹpẹ, lórí aṣọ tí wọ́n fi jẹ́ ẹ̀jẹ́ ní ilé òrìṣà wọn wọ́n sì mu ọtí tí wọ́n san fún ìtánràn.
Hagi nofi'ma hu'za vahe'mokizmi tavravema eri'nazana havi anumzazmimofo mono nompima kresrama vu itama me'nefi tafe ome hu'za nemase'za, havigema hu'za zago agima ahezmante'za eri'za zagoa, eriza waini ti miza hu'za ne'za neginagi hu'naze.
9 “Mo pa àwọn ará Amori run níwájú wọn gíga ẹni tí ó dàbí igi kedari. Òun sì le koko bí igi óákù mo pa èso rẹ̀ run láti òkè wá àti egbò rẹ̀ láti ìsàlẹ̀ wá.
Hagi Amori vahe'mo'za za'za hu'za sida zafagana hazageno, hanave zamimo'a oki zafagna hu'neanagi, Nagra Israeli vahekure hu'na Amori vahe'mofo ragane rafu'nane eri haviza hu'noe.
10 Èmi mú un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá, mo sì sìn yín la aginjù já ní ogójì ọdún láti fi ilẹ̀ àwọn ará Amori fún un yín.
Hagi Nagra Isipi mopafinti'ma tamavre'na mareri'noana, Amori vahe mopa erinafa'a hanazegu 40'a kafufina kegava huramante'na vahe'ma omani hagege kokampina e'noe.
11 “Èmi sì tún gbé àwọn wòlíì dìde láàrín àwọn ọmọ yín àti láàrín àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin yín láti jẹ Nasiri èyí kò ha jẹ́ òtítọ́ bí ará Israẹli?” ni Olúwa wí.
Hagi tamagri mofavre nagapintira Nagra mago'a veneneramina kasnampa vahe zamazeri oneti'na, mago'a vahera Nagrite mani ruotge hu'za manisaza kva vahe (Nazirites) zamazeri oti'noe. Hagi Ra Anumzamo'a huno, Ama kema nehuana tamage nehufi Israeli vahe'mota hu'ama huta zamasamiho hu'ne.
12 “Ṣùgbọ́n ẹ̀yin fún àwọn Nasiri ní ọtí mu e sì pàṣẹ fún àwọn wòlíì kí wọ́n má ṣe sọtẹ́lẹ̀.
Hianagi mani ruotge'ma hu'za mani'naza kva vahetamia tamagra waini tina zamizage'za ne'za neginagi nehazageta, kasnampa vahera kasnampa kea osu taganeta maniho huta zamazeri kori'naze.
13 “Ní báyìí, èmi yóò tẹ̀ yín mọ́lẹ̀ bí kẹ̀kẹ́ tí ó kún fún ìtí ti í tẹ̀.
E'ina hu'negu Nagra witima refuzafupeankna hu'na knazana tami'nena, tamagra knazama eri'naza vahe'mo'za'ma pripri hu'za nevaza vahekna hugahaze.
14 Ẹni tí ó yára bí àṣá kò ní rí ọ̀nà àbáyọ alágbára kò ní le è dúró lé agbára rẹ̀ jagunjagun kì yóò le gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là.
Hagi ame'ama hu'za zamagama neraza vahe'mo'za fregara osanageno, hanave vahe'mokizmia hanavezamia omanenigeno, harafa sondia vahe'mo'za kasamare'za hara hu'za zamagura ovazigahaze.
15 Tafàtafà kì yóò dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó gún ẹṣin kì yóò gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là.
Hagi atireti'ma ha'ma nehaza vahe'mo'za oti hanavetine'za hara osanageno, zamagama neraza vahe'mo'za zamagare'za ome frara oki'nageno, hosi afumofo agumpima mani'neno ha'ma nehia vahe'mo'a hara huno agra'a agura ovazigahie.
16 Àní jagunjagun tí ó gbóyà jùlọ yóò sálọ ní ìhòhò ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí.
Hagi koro'ma osu ha'ma nehaza sondia vahe'mo'za ana knazupa maka ha'zazimia atre'za zamavapa fregahaze huno Ra Anumzamo'a hu'ne.

< Amos 2 >