< Amos 2 >

1 Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta ti Moabu, àní fún mẹ́rin, Èmi kò ní yí ìpinnu ìjìyà mi padà, nítorí ó ti sun ún, di eérú, egungun ọba Edomu,
Jehova ekuuga atĩrĩ: “Nĩ ũndũ wa mehia matatũ ma Moabi, o na mana-rĩ, niĩ ndikahũndũra mangʼũrĩ makwa. Tondũ nĩacinire mahĩndĩ ma mũthamaki wa Edomu, magĩtuĩka ta coka,
2 Èmi yóò rán iná sí orí Moabu èyí tí yóò jó àwọn ààfin Kerioti run. Moabu yóò sì kú pẹ̀lú ariwo pẹ̀lú igbe àti pẹ̀lú ìró ìpè.
nĩngaitĩrĩria Moabi mwaki ũrĩa ũgaacina ciĩhitho iria nũmu cia Keriothu. Moabi nĩakagũa thĩ na mũrurumo mũnene, gatagatĩ-inĩ ka mbugĩrĩrio ya mbaara, na kũhuhwo kwa mũgambo wa karumbeta.
3 Èmi yóò ké onídàájọ́ rẹ̀ kúrò, Èmi yóò sì pa gbogbo àwọn ọmọ-aládé rẹ́ nínú rẹ̀,” ni Olúwa wí.
Nĩngananga mwathi wakuo, na njũrage anene ake othe hamwe nake,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
4 Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta ti Juda, àní fún mẹ́rin, Èmi kò ní yí ìpinnu ìjìyà mi padà. Nítorí wọn ti kọ òfin Olúwa sílẹ̀, wọn kò sì pa àwọn ìlànà rẹ̀ mọ́. Nítorí àwọn òrìṣà ti sì wọ́n lọ́nà, òrìṣà tí àwọn Baba ńlá wọn ń tẹ̀lé,
Jehova ekuuga atĩrĩ: “Nĩ ũndũ wa mehia matatũ ma Juda, o na mana-rĩ, niĩ ndikahũndũra mangʼũrĩ makwa. Tondũ nĩmaregete watho wa Jehova, na makaaga kũrũmia irĩra ciake cia watho wa kũrũmĩrĩrwo, tondũ nĩmahĩtithĩtio nĩ ngai cia maheeni, ngai iria maithe mao ma tene maarũmagĩrĩra.
5 Èmi yóò rán iná sí orí Juda èyí tí yóò jó àwọn ààfin Jerusalẹmu run.”
Nĩngaitĩrĩria Juda mwaki ũrĩa ũgaacina ciĩhitho iria nũmu cia Jerusalemu.”
6 Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta Israẹli àní fún mẹ́rin, Èmi kò ní yí ìpinnu ìjìyà mi padà. Wọ́n ta olódodo fún fàdákà àti aláìní fún bàtà ẹsẹ̀ méjèèjì.
Jehova ekuuga atĩrĩ; “Nĩ ũndũ wa mehia matatũ ma Isiraeli, o na mana-rĩ, niĩ ndikahũndũra mangʼũrĩ makwa. Mendagia andũ arĩa athingu betha, na arĩa abatari-rĩ, makamendia nyamũga igĩrĩ.
7 Wọ́n fi ẹsẹ̀ tẹ orí àwọn tálákà mọ́lẹ̀, bí wọ́n ti ń tẹ erùpẹ̀ ilẹ̀ tí wọ́n ko sì ṣe òtítọ́ si àwọn tí a ni lára. Baba àti ọmọ ń wọlé tọ wúńdíá kan náà, láti ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́.
Marangagĩrĩria mĩtwe ya arĩa athĩĩni taarĩ rũkũngũ rwa thĩ, na makaagithia kĩhooto arĩa ahinyĩrĩrie. Mũndũ na ithe makomaga na mũirĩtu ũmwe, nĩ ũndũ ũcio magathaahia rĩĩtwa rĩakwa itheru.
8 Wọ́n dùbúlẹ̀ lẹ́bàá a pẹpẹ, lórí aṣọ tí wọ́n fi jẹ́ ẹ̀jẹ́ ní ilé òrìṣà wọn wọ́n sì mu ọtí tí wọ́n san fún ìtánràn.
Makomaga harĩa hothe harĩ na kĩgongona, magakomera nguo iria irutĩtwo irũgamĩrĩre thiirĩ. Kũu thĩinĩ wa nyũmba ya ngai yao, nĩkuo manyuuagĩra ndibei ĩrĩa ĩrutĩtwo ya ndooco.
9 “Mo pa àwọn ará Amori run níwájú wọn gíga ẹni tí ó dàbí igi kedari. Òun sì le koko bí igi óákù mo pa èso rẹ̀ run láti òkè wá àti egbò rẹ̀ láti ìsàlẹ̀ wá.
“Nĩndanangire Aamori mehere mbere yao, o na gũtuĩka maarĩ araihu ta mĩtĩ ya mĩtarakwa, na marĩ na hinya ta mĩtĩ ya mĩgandi. Nĩndanangire matunda make kuuma na igũrũ, na ngĩananga mĩri yake kuuma na thĩ.
10 Èmi mú un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá, mo sì sìn yín la aginjù já ní ogójì ọdún láti fi ilẹ̀ àwọn ará Amori fún un yín.
“Ndakwambatirie ngĩkũruta bũrũri wa Misiri, na ngĩgũtongoria mĩaka mĩrongo ĩna kũu werũ-inĩ, nĩguo ngũhe bũrũri wa Aamori.
11 “Èmi sì tún gbé àwọn wòlíì dìde láàrín àwọn ọmọ yín àti láàrín àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin yín láti jẹ Nasiri èyí kò ha jẹ́ òtítọ́ bí ará Israẹli?” ni Olúwa wí.
Ningĩ nĩndarahũrire anabii kuuma kũrĩ ariũ aku, na ngĩarahũra Anaziri kuuma kũrĩ aanake aku. Githĩ ũcio ti ũhoro wa ma, inyuĩ andũ a Isiraeli?” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
12 “Ṣùgbọ́n ẹ̀yin fún àwọn Nasiri ní ọtí mu e sì pàṣẹ fún àwọn wòlíì kí wọ́n má ṣe sọtẹ́lẹ̀.
“No inyuĩ nĩmwaheire Anaziri ndibei manyue, na mũgĩatha anabii matikanarathe ũndũ.
13 “Ní báyìí, èmi yóò tẹ̀ yín mọ́lẹ̀ bí kẹ̀kẹ́ tí ó kún fún ìtí ti í tẹ̀.
“Na rĩrĩ, niĩ nĩngamũhehenja o ta ũrĩa ngaari ĩiyũrĩte ngano ĩhehenjaga.
14 Ẹni tí ó yára bí àṣá kò ní rí ọ̀nà àbáyọ alágbára kò ní le è dúró lé agbára rẹ̀ jagunjagun kì yóò le gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là.
Mũndũ ũrĩa ũrĩ ihenya ndakahota kwĩhonokia. Ũrĩa ũrĩ hinya ndagateithio nĩ hinya ũcio wake, nayo njamba ya ita ndĩkahonokia muoyo wayo.
15 Tafàtafà kì yóò dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó gún ẹṣin kì yóò gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là.
Mũrathi na mĩguĩ ndakeyũmĩrĩria, na mũthigari ũrĩa ũhiũkaga ndakahota kũũra, na ũrĩa ũhaicĩte mbarathi ndakahonokia muoyo wake.
16 Àní jagunjagun tí ó gbóyà jùlọ yóò sálọ ní ìhòhò ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí.
O nacio njamba cia ita iria nyũmĩrĩru mũno, ikoora irĩ njaga mũthenya ũcio,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.

< Amos 2 >