< Acts 1 >

1 Nínú ìwé mi ìṣáájú, Teofilu, ni mo ti kọ ní ti ohun gbogbo tí Jesu bẹ̀rẹ̀ sí ṣe àti kọ́
ហេ ថិយផិល, យីឝុះ ស្វមនោនីតាន៑ ប្រេរិតាន៑ បវិត្រេណាត្មនា សមាទិឝ្យ យស្មិន៑ ទិនេ ស្វគ៌មារោហត៑ យាំ យាំ ក្រិយាមករោត៑ យទ្យទ៑ ឧបាទិឝច្ច តានិ សវ៌្វាណិ បូវ៌្វំ មយា លិខិតានិ។
2 títí ó fi di ọjọ́ tí a gbà á lọ sókè ọ̀run, lẹ́yìn tí ó ti ti ipa Ẹ̀mí Mímọ́ pàṣẹ fún àwọn aposteli tí ó yàn.
ស ស្វនិធនទុះខភោគាត៑ បរម៑ អនេកប្រត្យយក្ឞប្រមាណៅះ ស្វំ សជីវំ ទឝ៌យិត្វា
3 Lẹ́yìn ìjìyà rẹ̀, ó fi ara rẹ̀ hàn fún wọn àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀rí tí ó dájú pé òun wà láààyè. Ó fi ara hàn wọ́n fún ogójì ọjọ́, ó sì sọ̀rọ̀ nípa ìjọba Ọlọ́run.
ចត្វារិំឝទ្ទិនានិ យាវត៑ តេភ្យះ ប្រេរិតេភ្យោ ទឝ៌នំ ទត្ត្វេឝ្វរីយរាជ្យស្យ វណ៌នម អករោត៑។
4 Ní àkókò kan bí ó sì ti ń jẹun pẹ̀lú wọn, ó pàṣẹ yìí fún wọn, “Ẹ má ṣe kúrò ní Jerusalẹmu, ṣùgbọ́n ẹ dúró de ìlérí tí Baba mi ṣe ìlérí, èyí tí ẹ̀yin tí gbọ́ lẹ́nu mi.
អនន្តរំ តេឞាំ សភាំ ក្ឫត្វា ឥត្យាជ្ញាបយត៑, យូយំ យិរូឝាលមោៜន្យត្រ គមនមក្ឫត្វា យស្តិន៑ បិត្រាង្គីក្ឫតេ មម វទនាត៑ កថា អឝ្ឫណុត តត្ប្រាប្តិម៑ អបេក្ឞ្យ តិឞ្ឋត។
5 Nítorí Johanu fi omi bamitiisi yín, ṣùgbọ́n ní ọjọ́ díẹ̀ sí i, a o fi Ẹ̀mí Mímọ́ bamitiisi yín.”
យោហន៑ ជលេ មជ្ជិតាវាន៑ កិន្ត្វល្បទិនមធ្យេ យូយំ បវិត្រ អាត្មនិ មជ្ជិតា ភវិឞ្យថ។
6 Nítorí náà, nígbà tí wọ́n sì péjọpọ̀, wọn bi í léèrè pé, “Olúwa, láti ìgbà yí lọ ìwọ yóò ha mú ìjọba padà fún Israẹli bí?”
បឝ្ចាត៑ តេ សវ៌្វេ មិលិត្វា តម៑ អប្ឫច្ឆន៑ ហេ ប្រភោ ភវាន៑ កិមិទានីំ បុនរបិ រាជ្យម៑ ឥស្រាយេលីយលោកានាំ ករេឞុ សមប៌យិឞ្យតិ?
7 Ó sì wí fún wọn pé, “Kì í ṣe tiyín ni láti mọ àkókò tàbí ìgbà tí Baba ti yàn nípa àṣẹ òun tìkára rẹ̀.
តតះ សោវទត៑ យាន៑ សវ៌្វាន៑ កាលាន៑ សមយាំឝ្ច បិតា ស្វវឝេៜស្ថាបយត៑ តាន៑ ជ្ញាត្ឫំ យុឞ្មាកម៑ អធិការោ ន ជាយតេ។
8 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin yóò gba agbára, nígbà tí Ẹ̀mí Mímọ́ bá bà lé e yín; ẹ̀yin yóò sì máa ṣe ẹlẹ́rìí mi ni Jerusalẹmu, àti ní gbogbo Judea, àti ní Samaria, àti títí dé òpin ilẹ̀ ayé.”
កិន្តុ យុឞ្មាសុ បវិត្រស្យាត្មន អាវិព៌្ហាវេ សតិ យូយំ ឝក្តិំ ប្រាប្យ យិរូឝាលមិ សមស្តយិហូទាឝោមិរោណទេឝយោះ ប្ឫថិវ្យាះ សីមាំ យាវទ៑ យាវន្តោ ទេឝាស្តេឞុ យវ៌្វេឞុ ច មយិ សាក្ឞ្យំ ទាស្យថ។
9 Nígbà tí ó sì tí wí nǹkan wọ̀nyí, a gbà á sókè lójú wọn; ìkùùkuu àwọsánmọ̀ sì gbà á kúrò lójú wọn.
ឥតិ វាក្យមុក្ត្វា ស តេឞាំ សមក្ឞំ ស្វគ៌ំ នីតោៜភវត៑, តតោ មេឃមារុហ្យ តេឞាំ ទ្ឫឞ្ដេរគោចរោៜភវត៑។
10 Bí wọ́n sì ti tẹjúmọ́ ojú ọ̀run bí ó ti ń lọ sókè, lójijì, àwọn ọkùnrin méjì tí ó wọ aṣọ funfun dúró létí ọ̀dọ̀ wọn.
យស្មិន៑ សមយេ តេ វិហាយសំ ប្រត្យនន្យទ្ឫឞ្ដ្យា តស្យ តាទ្ឫឝម៑ ឩទ៌្វ្វគមនម៑ អបឝ្យន៑ តស្មិន្នេវ សមយេ ឝុក្លវស្ត្រៅ ទ្វៅ ជនៅ តេឞាំ សន្និធៅ ទណ្ឌាយមានៅ កថិតវន្តៅ,
11 Wọ́n sì wí pé, “Ẹ̀yin ara Galili, èéṣe tí ẹ̀yin fi dúró tí ẹ̀ ń wo ojú ọ̀run? Jesu yìí, tí a gbà sókè ọ̀run kúrò lọ́wọ́ yín, yóò padà bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ ti rí tí ó ń lọ sì ọ̀run.”
ហេ គាលីលីយលោកា យូយំ កិមត៌្ហំ គគណំ ប្រតិ និរីក្ឞ្យ ទណ្ឌាយមានាស្តិឞ្ឋថ? យុឞ្មាកំ សមីបាត៑ ស្វគ៌ំ នីតោ យោ យីឝុស្តំ យូយំ យថា ស្វគ៌ម៑ អារោហន្តម៑ អទឝ៌ម៑ តថា ស បុនឝ្ចាគមិឞ្យតិ។
12 Lẹ́yìn náà ni wọ́n padà sí Jerusalẹmu láti orí òkè ti a ń pè ni olifi, tí ó tó ìwọ̀n ìrìn ọjọ́ ìsinmi kan.
តតះ បរំ តេ ជៃតុននាម្នះ បវ៌្វតាទ៑ វិឝ្រាមវារស្យ បថះ បរិមាណម៑ អត៌្ហាត៑ ប្រាយេណាទ៌្ធក្រោឝំ ទុរស្ថំ យិរូឝាលម្នគរំ បរាវ្ឫត្យាគច្ឆន៑។
13 Nígbà tí wọn sì wọlé, wọn lọ sí iyàrá òkè, níbi tí wọ́n ń gbé. Àwọn tó wà níbẹ̀ ni: Peteru, Jakọbu, Johanu àti Anderu; Filipi àti Tomasi; Bartolomeu àti Matiu; Jakọbu ọmọ Alfeu, Simoni Sealoti, àti Judasi arákùnrin Jakọbu.
នគរំ ប្រវិឝ្យ បិតរោ យាកូព៑ យោហន៑ អាន្ទ្រិយះ ផិលិបះ ថោមា ពត៌្ហជមយោ មថិរាល្ផីយបុត្រោ យាកូព៑ ឧទ្យោគា ឝិមោន៑ យាកូពោ ភ្រាតា យិហូទា ឯតេ សវ៌្វេ យត្រ ស្ថានេ ប្រវសន្តិ តស្មិន៑ ឧបរិតនប្រកោឞ្ឋេ ប្រាវិឝន៑។
14 Gbogbo àwọn wọ̀nyí pẹ̀lú àwọn obìnrin àti Maria ìyá Jesu àti àwọn arákùnrin rẹ̀ fi ọkàn kan dúró láti máa gbàdúrà.
បឝ្ចាទ៑ ឥមេ កិយត្យះ ស្ត្រិយឝ្ច យីឝោ រ្មាតា មរិយម៑ តស្យ ភ្រាតរឝ្ចៃតេ សវ៌្វ ឯកចិត្តីភូត សតតំ វិនយេន វិនយេន ប្រាត៌្ហយន្ត។
15 Ní ọjọ́ wọ̀nyí ni Peteru sí dìde dúró láàrín àwọn ọmọ-ẹ̀yìn (iye àwọn ènìyàn wọ̀nyí jẹ́ ọgọ́fà)
តស្មិន៑ សមយេ តត្រ ស្ថានេ សាកល្យេន វិំឝត្យធិកឝតំ ឝិឞ្យា អាសន៑។ តតះ បិតរស្តេឞាំ មធ្យេ តិឞ្ឋន៑ ឧក្តវាន្
16 ó wí pé, “Ẹ̀yin ará, ìwé mímọ́ kò lè ṣe kí ó má ṣẹ, èyí tí Ẹ̀mí Mímọ́ ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu Dafidi nípa Judasi, tí ó ṣe atọ́nà fún àwọn tí ó mú Jesu.
ហេ ភ្រាត្ឫគណ យីឝុធារិណាំ លោកានាំ បថទឝ៌កោ យោ យិហូទាស្តស្មិន៑ ទាយូទា បវិត្រ អាត្មា យាំ កថាំ កថយាមាស តស្យាះ ប្រត្យក្ឞីភវនស្យាវឝ្យកត្វម៑ អាសីត៑។
17 Nítorí ọ̀kan nínú wa ni òun ń ṣe tẹ́lẹ̀, òun sì ní ìpín nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ yìí.”
ស ជនោៜស្មាកំ មធ្យវត៌្តី សន៑ អស្យាះ សេវាយា អំឝម៑ អលភត។
18 (Judasi fi èrè àìṣòótọ́ rẹ̀ ra ilẹ̀ kan; nígbà tí ó sì ṣubú ni ògèdèǹgbé, ó bẹ́ ní agbede-méjì, gbogbo ìfun rẹ̀ sì tú jáde.
តទនន្តរំ កុកម៌្មណា លព្ធំ យន្មូល្យំ តេន ក្ឞេត្រមេកំ ក្រីតម៑ អបរំ តស្មិន៑ អធោមុខេ ភ្ឫមៅ បតិតេ សតិ តស្យោទរស្យ វិទីណ៌ត្វាត៑ សវ៌្វា នាឌ្យោ និរគច្ឆន៑។
19 Ó si di mí mọ̀ fún gbogbo àwọn ti ń gbé Jerusalẹmu; nítorí náà ni wọ́n fi ń pè ilẹ̀ náà ni Alkedama ní èdè wọn, èyí sì ni, Ilẹ̀ Ẹ̀jẹ̀.)
ឯតាំ កថាំ យិរូឝាលម្និវាសិនះ សវ៌្វេ លោកា វិទាន្តិ; តេឞាំ និជភាឞយា តត្ក្ឞេត្រញ្ច ហកល្ទាមា, អត៌្ហាត៑ រក្តក្ឞេត្រមិតិ វិខ្យាតមាស្តេ។
20 Peteru sì wí pé, “Nítorí a ti kọ ọ́ nípa rẹ̀ nínú Ìwé Saamu pé, “‘Jẹ́ ki ibùgbé rẹ̀ di ahoro, kí ẹnikẹ́ni má ṣe gbé inú rẹ̀,’ àti, “‘Ipò rẹ̀ ni kí ẹlòmíràn kí ó gbà.’
អន្យច្ច, និកេតនំ តទីយន្តុ ឝុន្យមេវ ភវិឞ្យតិ។ តស្យ ទូឞ្យេ និវាសាត៌្ហំ កោបិ ស្ថាស្យតិ នៃវ ហិ។ អន្យ ឯវ ជនស្តស្យ បទំ សំប្រាប្ស្យតិ ធ្រុវំ។ ឥត្ថំ គីតបុស្តកេ លិខិតមាស្តេ។
21 Nítorí náà, ó di dandan láti yan ọ̀kan nínú àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ti ń bá wa rìn ni gbogbo àkókò tí Jesu Olúwa ń wọlé, tí ó sì jáde láàrín wa.
អតោ យោហនោ មជ្ជនម៑ អារភ្យាស្មាកំ សមីបាត៑ ប្រភោ រ្យីឝោះ ស្វគ៌ារោហណទិនំ យាវត៑ សោស្មាកំ មធ្យេ យាវន្តិ ទិនានិ យាបិតវាន្
22 Bẹ́ẹ̀ láti ìgbà bamitiisi Johanu títí ó fi di ọjọ́ náà ti a gbe é lọ sókè kúrò lọ́dọ̀ wa. Ó yẹ kí ọ̀kan nínú àwọn wọ̀nyí ṣe ẹlẹ́rìí àjíǹde rẹ̀ pẹ̀lú wa.”
តាវន្តិ ទិនានិ យេ មានវា អស្មាភិះ សាទ៌្ធំ តិឞ្ឋន្តិ តេឞាម៑ ឯកេន ជនេនាស្មាភិះ សាទ៌្ធំ យីឝោរុត្ថានេ សាក្ឞិណា ភវិតវ្យំ។
23 Wọn sì yan àwọn méjì, Josẹfu tí a ń pè ní Barsaba (ẹni tí a sọ àpèlé rẹ̀ ni Justu) àti Mattia.
អតោ យស្យ រូឍិ រ្យុឞ្ដោ យំ ពឝ៌ព្ពេត្យុក្ត្វាហូយន្តិ ស យូឞផ៑ មតថិឝ្ច ទ្វាវេតៅ ប្ឫថក៑ ក្ឫត្វា ត ឦឝ្វរស្យ សន្និធៅ ប្រាយ៌្យ កថិតវន្តះ,
24 Wọn sì gbàdúrà, wọn sì wí pé, “Olúwa, ìwọ mọ ọkàn gbogbo ènìyàn, fihàn wá nínú àwọn méjì yìí, èwo ni ìwọ yàn
ហេ សវ៌្វាន្តយ៌្យាមិន៑ បរមេឝ្វរ, យិហូទាះ សេវនប្រេរិតត្វបទច្យុតះ
25 kí ó lè gba ipò nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ aposteli yìí, èyí tí Judasi kúrò nínú rẹ̀, ki òun kí ó lè lọ sí ipò ti ara rẹ̀.”
សន៑ និជស្ថានម៑ អគច្ឆត៑, តត្បទំ លព្ធុម៑ ឯនយោ រ្ជនយោ រ្មធ្យេ ភវតា កោៜភិរុចិតស្តទស្មាន៑ ទឝ៌្យតាំ។
26 Wọ́n sì dìbò fún wọn; ìbò sí mú Mattia; a sì kà á mọ́ àwọn aposteli mọ́kànlá.
តតោ គុដិកាបាដេ ក្ឫតេ មតថិន៌ិរចីយត តស្មាត៑ សោន្យេឞាម៑ ឯកាទឝានាំ ប្ររិតានាំ មធ្យេ គណិតោភវត៑។

< Acts 1 >