< Acts 7 >
1 Nígbà náà ni olórí àlùfáà wí pé, “Òtítọ́ ha ni àwọn ẹ̀sùn tí wọ́ fi kàn ọ́ bí?”
Bosi pfumu yi zinganga Nzambi wunyuvula: —Mambu mama bafundidi madi makiedika e?
2 Ní ìdáhùn sí èyí ó wí pé, “Ẹ̀yin arákùnrin àti ẹ̀yin baba, ẹ fetísílẹ̀ sí mi! Ọlọ́run ògo fi ara hàn fún Abrahamu baba wa, nígbà tí ó wà ni Mesopotamia, kí ó to ṣe àtìpó ni Harani.
Buna Etieni wuvutula: —Batata ayi bakhomba ziama, bika luwa mambu ndieka ntuba: Nzambi yi nkemboyimonikina Dise dieto Abalahami bu kaba ku Mesopotami, tuamina kavuanda ku Alani,
3 Ọlọ́run wí fún un pé, ‘Jáde kúrò ní orílẹ̀-èdè rẹ àti kúrò lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ, lọ sí ilẹ̀ kan tí èmi yóò fihàn ọ́.’
ayi wunkamba: Bika tsi aku ayi bibutu biaku vayi yenda ku tsi yoyi ndiela ku monisa.
4 “Nígbà náà ni ó jáde kúrò ní ilẹ̀ àwọn ará Kaldea, ó sì ṣe àtìpó ni Harani. Lẹ́yìn ìgbà tí baba rẹ̀ sì kú, Ọlọ́run mú un sípò padà wá sí ilẹ̀ yìí, níbi tí ẹ̀yin ń gbé báyìí.
Buna wubika tsi yi Kalide ayi wuyenda vuanda ku Alani. Dise diandi bu kafua, Nzambi wuntumisa mu tsi yayi lulembo zingila buabu.
5 Kò sí fún un ni ìní kan, ànító bi ìwọ̀n ààyè ẹsẹ̀ kan. Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ṣe ìlérí fún pé, òun yóò fi ilẹ̀ ìní náà fún un àti fún àwọn irú-ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀, nígbà tí kò tí ì ní ọmọ.
Vayi Nzambi kasia kumvana kadi kiuka ko mu tsi yayi, ka diambu ko tini kintoto kioki kalenda tula lutambi luandi. Muaki Nzambi wunvana tsila yi kunvana tsi beni va kimosi ayi nkunꞌandi. Vayi mu thangu yina buna kabutidi kadi muana ko.
6 Ọlọ́run sì sọ báyìí pé, ‘Irú-ọmọ rẹ yóò ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì; wọn ó sì sọ wọn di ẹrú, wọn ó sì pọ́n wọn lójú fún irinwó ọdún.
Buna Nzambi wunkamba: nkunꞌaku wela zingila mu tsi yi kinzenza; bela kuwuyadila ayi bela kuwuyamisa
7 Ọlọ́run wí pé, Orílẹ̀-èdè náà tí wọn yóò máa sìn, ni èmi ó dá lẹ́jọ́; lẹ́yìn náà ni wọn ó sì jáde kúrò, wọn ó sì wá sìn mí níhìn-ín yìí.’
Vayi Nzambi wubuela kamba diaka: ndiela sambisa tsi yoyi yela kuba yadila Bosi bela totuka mu tsi beni ayi bela kuiza ku tsambidila va buangu kiaki.
8 Ó sì fún Abrahamu ni májẹ̀mú ìkọlà. Abrahamu bí Isaaki, ó kọ ọ́ ní ilà ni ọjọ́ kẹjọ tí ó bí i. Isaaki sí bí Jakọbu, Jakọbu sì bí àwọn baba ńlá méjìlá.
Nzambi wuvanga nguizani andi ayi Abalahami: nguizani yi nzengolo yi nitu yi kibakala. Abalahami wubuta Isaki, wunzenga mu lumbu ki nana. Isaki wubuta Yakobi bosi Yakobi wubuta kumi bakulu buadi.
9 “Àwọn baba ńlá sí ṣe ìlara Josẹfu, wọ́n sì tà á sí Ejibiti; ṣùgbọ́n Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀,
Bakulu basumbisa Zozefi ku Ezipite mu diambu di kikhenene. Vayi Nzambi wuba yandi.
10 ó sì yọ ọ́ kúrò nínú ìpọ́njú rẹ̀ gbogbo. Ó sì fún Josẹfu ní ọgbọ́n, ó sì mú kí ó rí ojúrere Farao ọba Ejibiti; òun sì fi jẹ baálẹ̀ Ejibiti àti gbogbo ilé rẹ̀.
Diawu kankudila mu ziphasi ziandi zioso ayi mu nlemvo wu Nzambi, Zozefi wumonika mutu wu diela va ntuala Falawo, ntinu wu Ezipite. Diawu kanbiekila nyadi mu Ezipite dioso ayi mu nzo andi yoso.
11 “Ìyàn kan sì mú ni gbogbo ilẹ̀ Ejibiti àti ni Kenaani, àti ìpọ́njú ńlá, àwọn baba wa kò sì rí oúnjẹ.
Vayi kutotuka kanda kingolo mu Ezipite dioso ayi mu Kana. Ziphasi zingolo ziba mu thangu beni. Bakulu beto basia baka bidia ko.
12 Ṣùgbọ́n nígbà tí Jakọbu gbọ́ pé alikama ń bẹ ni Ejibiti, ó rán àwọn baba wa lọ lẹ́ẹ̀kínní.
Yakobi bu kawa ti ble yiba ku Ezipite, buna kuna kafidisa bakulu beto mu khubu yitheti.
13 Nígbà kejì Josẹfu fi ara rẹ̀ hàn fún àwọn arákùnrin rẹ̀, a sì tún fi wọ́n hàn fún Farao.
Mu khumbu yimmuadi yayi kaba fidisa, Zozefi wukimonikisa kuidi bakhomba bandi ayi Falawo wuyiza zaba dikanda de Zozefi.
14 Lẹ́yìn èyí, Josẹfu ránṣẹ́ pe Jakọbu baba rẹ̀, àti àwọn ìbátan rẹ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ, gbogbo wọ́n sì tó àrùndínlọ́gọ́rin ọkàn.
Buna Zozefi wutumisa dise diandi Yakobi ayi bibutu biandi bioso. Thalu yi batu boso yiba lusambudi lu batu ayi batu batanu.
15 Nígbà náà ni Jakọbu sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti, ní ibi tí òun àti àwọn baba wa kú sí.
Yakobi wuyenda ku Ezipite, kuawu kafuila va kimosi ayi bakulu beto.
16 A sì gbé òkú wọn padà wá sí Ṣekemu, a sì tẹ́ wọn sínú ibojì ti Abrahamu rà ni ọwọ́ àwọn ọmọ Amori ní Ṣekemu ní iye owó wúrà kan.
Banatu ku Sikemi, baziku mu biziami bisumba Abalahami kuidi bana ba Amoli, bobo baba nkalanga mu Sikemi.
17 “Nígbà tí àkókò tí Ọlọ́run yóò mú ìlérí tí ó ṣe fún Abrahamu ṣẹ kù sí dẹ̀dẹ̀, àwọn ènìyàn wa ń gbèrú si gidigidi ní iye ní ilẹ̀ Ejibiti.
Sumbu thangu yifueti dedikinina tsila Nzambi kavana Abalahami bu yifikama, buna batu babuelama ayi baluta buelama mu Ezipite
18 Ṣùgbọ́n ọba tuntun mìíràn tí kò mọ Josẹfu jẹ ní ilẹ̀ Ejibiti.
nate ntinu wunkaka wukambu zaba Zozefi wutotuka mu Ezipite. Zozefi.
19 Òun náà ni ó ṣe àrékérekè sí àwọn ìbátan wa. Wọn sì hùwà búburú sí àwọn baba wa, tó bẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi já àwọn ọmọ ọwọ́ wọn kúrò lọ́wọ́ wọn nítorí kí wọn má ṣe yè.
Ntinu beni wusadila luvunu va ntuala dikanda dieto, wumonisa bakulu beto ziphasi nate mu kuba kuika baloza bana bawu batsombi mu diambu bana beni babika zinga.
20 “Ní àkókò náà ni a bí Mose ọmọ tí ó se iyebíye, tí wọn sí bọ́ lóṣù mẹ́ta ni ilé baba rẹ̀.
Yawu thangu yibutukila Moyize, wuba muana wu kitoko va ntuala Nzambi. Zingondi zitatu bambuta bandi bansuekila mu nzo.
21 Nígbà tí wọn sí gbe é sọnù, ọmọbìnrin Farao gbé e, ó sì tọ ọ́ dàgbà gẹ́gẹ́ bí ọmọ ara rẹ̀.
Vayi bambuta bandi bu banloza, buna muana wunketo wu Falawo wuntota ayi wunyundula, wunkitula muanꞌandi.
22 A sì kọ́ Mose ni gbogbo ọgbọ́n ara Ejibiti, ó sì pọ̀ ni ọ̀rọ̀ àti ní ìṣe.
Diawu Moyize wulongila mu ndongokolo yoso yi basi Ezipite, wuyiza ba mutu wunneni mu thubulu andi ayi mu mavanga mandi.
23 “Nígbà tí Mose di ọmọ ogójì ọdún, ó sọ sí i lọ́kàn láti lọ bẹ àwọn ọmọ Israẹli ará rẹ̀ wò.
Moyize bu kadukisa makumaya ma mimvu, wubaka lukanu lu kuenda tadi bakhomba bandi; bana ba Iseli.
24 Nígbà tí ó sì rí ọ̀kan nínú wọ́n tí ará Ejibiti kan ń jẹ́ ní ìyà, ó gbèjà rẹ̀, ó gbẹ̀san ẹni tí wọ́n jẹ ní ìyà nípa lílu ará Ejibiti náà pa.
Bu kamona wumosi mu bawu, wumonoso phasi, buna wunkotila ayi wuvonda muisi Ezipite mutu wumonisa muana Iseli phasi.
25 Mose rò bí àwọn ará òun mọ̀ pé Ọlọ́run yóò ti ọwọ́ òun gbà wọn; ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀.
Wubanza ti bakhomba bandi zilznda sudika ti mu nzilꞌandi Nzambi wela kuba kula vayi basia sudika ko.
26 Ní ọjọ́ kejì Mose yọ sí àwọn ọmọ Israẹli méjì bí wọ́n ti ń jà. Òun si fẹ́ parí ìjà fún wọn. Ó wí pé, ‘Ènìyàn mi, ará ni ẹ̀yin; èéṣe tí ẹ̀yin fi ń ṣe ohun tí kò tọ́ sí ara yín?’
Mu lumbu kilanda, wukimonisa kisa bana ba Iseli thangu baba nuana. Wuzola vutula ndembama va bawu bu kaba kamba: —A kiti beno luidi bakhomba! A bila mbi lulembo kimonisina phasi beno na beno e?
27 “Ṣùgbọ́n ẹni tí ó fínràn sí ẹnìkejì rẹ̀ ti Mose sí ẹ̀gbẹ́ kan, ó wí pé, ‘Ta ni ó fi ọ́ jẹ olórí àti onídàájọ́ lórí wa?
Vayi mutu wowo wumonisa ndiandi phasi wutemina Moyize ayi wunkamba: —A nani wubiekidi pfumu ayi zuzi dieto e?
28 Ṣé ìwọ fẹ́ pa mí bí o ti pa ará Ejibiti lánàá?’
Fuana ngeyo minu tidi vonda banga bobo wuvondidi muisi Ezipite kibeni yono e?
29 Mose sì sá nítorí ọ̀rọ̀ yìí, ó sì wa ṣe àtìpó ni ilẹ̀ Midiani, níbi tí ó gbé bí ọmọ méjì.
Moyize bu kawa bobo, wutina ayi wukituka nzenza mu tsi yi Madiani, kuawu kabutila bana buadi bababakala.
30 “Nígbà tí ogójì ọdún sì pé, angẹli Olúwa fi ara han Mose ní ijù, ní òkè Sinai, nínú ọ̀wọ́-iná nínú igbó.
Makumaya ma mimvu bu mavioka, buna mbasi yimmonikina mu dikanga di mongo wu Sinayi. Wummonikina mu nlaki wu mbazu mu finti.
31 Nígbà tí Mose sì rí i, ẹnu yà á sí ìran náà; nígbà tí ó sì súnmọ́ ọn láti wò ó fín, ohùn Olúwa kọ sí i,
Moyize bu kamona bobo, wusimina mu diambu di tsongolo. Bu kafikama mu kuenda tadi, buna mbembo yi Pfumu yiwakana:
32 wí pé ‘Èmi ni Ọlọ́run àwọn baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu,’ Mose sì wárìrì pẹ̀lú ìbẹ̀rù, kò sì dáṣà láti wò ó mọ́.
Minu ndidi Nzambi yi bakulu baku; Nzambi yi Abalahami, yi Izaki ayi yi Yakobi. Moyize weka tita ayi kasia nunga buela tala ko.
33 “Olúwa sì wí fún un pé, ‘Bọ́ bàtà rẹ kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ, nítorí ibi tí ìwọ dúró sí i nì ilẹ̀ mímọ́ ni.
Buna Pfumu wunkamba: Vula zisapatu zidi mu malu maku, bila buangu kioki telimini kidi ntoto wunlongo.
34 Ní rí rí, mo ti rí ìpọ́njú àwọn ènìyàn mi tí ń bẹ ni Ejibiti, mo sì ti gbọ́ ìkérora wọn, mo sì sọ̀kalẹ̀ wá láti gbà wọ́n. Wá nísinsin yìí, Èmi ó sì rán ọ lọ sí ilẹ̀ Ejibiti.’
Ndimueni ziphasi zi batu bama badi ku Ezipite. Ndiwilu bidilu biawu. Diawu ndizidi mu kuba kula. Yiza buabu bila ngeyo ndieka tuma ku Ezipite.
35 “Mose náà yìí tí wọ́n kọ̀, wí pé, ‘Ta ni ó fi jẹ olórí àti onídàájọ́?’ Òun náà ni Ọlọ́run rán lọ láti ọwọ́ angẹli, tí ó farahàn án ní pápá, láti ṣe olórí àti olùdáǹdè.
Moyize beni diodi bamanga bu batuba: Nani wubiekidi pfumu ayi zuzi e? Buabu Nzambi wuntuma mu ba pfumu ayi nkudi mu lusadusu lu mbasi yoyi yimmonikina mu finti.
36 Òun ni ó mú wọn jáde, lẹ́yìn ìgbà tí ó ṣe iṣẹ́ ìyanu àti iṣẹ́ àmì ní ilẹ̀ Ejibiti, àti ni Òkun pupa, àti ni aginjù ní ogójì ọdún.
Niandi wuba totula bu kavanga mambu manneni ayi bikumu mu tsi yi Ezipite, mu mbu wu mbuaki ayi mu dikanga mu tezo ki makumaya ma mimvu.
37 “Èyí ni Mose náà ti ó wí fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Ọlọ́run yóò gbé wòlíì kan bí èmi dìde nínú àwọn ènìyàn yín.’
Moyize beni niandi wukamba bana ba Iseli: Nzambi wela kulutotudila mbikudi wela ba banga minu va khatitsika bakhomba zieno.
38 Èyí náà ni ẹni tí ó wà nínú ìjọ ní ijù pẹ̀lú angẹli náà tí ó bá a sọ̀rọ̀ ní orí òkè Sinai, àti pẹ̀lú àwọn baba wa; ẹni ti ó gba ọ̀rọ̀ ìyè láti fi fún wa.
Niandi wuba mu lukutukunu ku dikanga va kimosi ayi mbasi yoyi yinyolukila ku mongo Sinayi va kimosi ayi bakulu beto. Niandi wutambula mambu ma moyo muingi katutudisila mawu.
39 “Ṣùgbọ́n àwọn baba wa kò fẹ́ gbọ́ tirẹ̀. Dípò bẹ́ẹ̀, wọ́n kọ̀ ọ́ sílẹ̀, àti pé nínú ọkàn wọn, wọn fẹ́ yípadà lọ sí ilẹ̀ Ejibiti.
Vayi bakulu beto bamanga kuntumukina; banloza ayi mintima miawu mibaluka ku Ezipite.
40 Wọ́n wí fún Aaroni pé, ‘Dá òrìṣà fún wa tí yóò máa tọ́nà ṣáájú wa; nítorí bí ó ṣe ti Mose yìí tí ó mú wa jáde wá láti ilẹ̀ Ejibiti, a kò mọ̀ ohun tí ó ṣe é.’
Bawu bakamba Aloni: —Wutuvangila zinzambi zilenda ku tutuaminina ku ntuala bila tukadi zaba mambu mbi mabuilulu Moyize diodi ditutotula mu tsi yi Ezipite.
41 Wọ́n sì yá ère ẹgbọrọ màlúù ni ọjọ́ wọ̀nyí. Wọ́n sì rú ẹbọ sí ère náà, wọ́n sì ń yọ̀ nínú ohun tí wọ́n fi ọwọ́ ara wọn ṣe.
Diawu mu bilumbu bina, bavanga tumba kimuana ngombi ayi batambika makaba kuidi tumba beni. Bamona khini mu diambu di bima bivanga mioko miawu.
42 Ọlọ́run sì padà, ó fi wọn sílẹ̀ láti máa sin ogun ọ̀run: òòrùn, òṣùpá àti ìràwọ̀. Èyí wà ní ìbámu pẹ̀lú bí a ti kọ ọ́ nínú ìwé àwọn wòlíì pé: “‘Ẹ̀yin ha mú ẹran tí a pa àti ẹbọ wa fún mi ní ogójì ọdún ní ijù bí, ìwọ ilé Israẹli?
Vayi Nzambi wuba tamba manima, wuba yekula mu sadila zimbuetete banga busonimina mu nkanda wu mimbikudi: A basi Iseli, minu lutambikila bibulu ayi makaba mu makumaya ma mimvu mu dikanga e?
43 Ẹ̀yin sì tẹ́wọ́gbà àgọ́ Moleki, àti ìràwọ̀ Refani òrìṣà yín, àwòrán tí ẹ̀yin ṣe láti máa bọ wọ́n. Nítorí náà èmi yóò kó yín lọ sí ìgbèkùn rékọjá Babeli.’
Beno lunata nzo ngoto yi Moloki ayi mbuetete yi nzambi Lefani, zimfikula ziozi luvanga muingi lubi; sambidila diawu ndiela kulunata mu buvika vioka Babiloni!
44 “Àwọn baba wa ní àgọ́ ẹ̀rí pẹ̀lú wọn ní ijù. Èyí tí a ṣe gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run tí ó ba Mose sọ̀rọ̀ pé kí ó ṣe é, gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ tí ó ti rí.
Bakulu beto baba ayi Nzo ngoto yi kimbangi mu dikanga, yivangama banga bu tumina Nzambi, Nzambi mutu wukamba Moyize ti kavanga yawu boso buididi mfikula yoyi kamona.
45 Ti àwọn baba wa tí ó tẹ̀lé wọn sí mú bá Joṣua wá sí ilẹ̀ ìní àwọn aláìkọlà, tí Ọlọ́run lè jáde kúrò níwájú àwọn baba wa, títí dí àkókò Dafidi.
Bakulu beto bu batambula yawu; bayikotisa mu thangu zozue mu zitsi zi Bapakanu, babo Nzambi kakuka ku ntuala bakulu beto nate mu thangu Davidi,
46 Ẹni tí ó rí ojúrere níwájú Ọlọ́run, tí ó sì tọrọ láti rí ibùgbé fún Ọlọ́run Jakọbu.
mutu wowo wumonokono nlemvo kuidi Nzambi ayi wuzola tungila Nzambi Yakobi nzo.
47 Ṣùgbọ́n Solomoni ni ó kọ́ ilé fún un.
Vayi Salomo wuyiza kuntungila nzo.
48 “Ṣùgbọ́n Ọ̀gá-ògo kì í gbé ilé ti a fi ọwọ́ kọ́, gẹ́gẹ́ bí wòlíì ti wí pé:
Muaki, Nzambi yizangama kakalanga ko mu zinzo zitungulu mu mioko mi batu, banga bu tubila mbikudi:
49 “‘Ọ̀run ni ìtẹ́ mi, ayé ni àpótí ìtìsẹ̀ mi. Irú ilé kín ní ẹ̀yin yóò kọ́ fún mi? ni Olúwa wí. Tàbí níbo ni yóò jẹ́ ibi ìsinmi mi?
Pfumu wutuba: Diyilu diawu kundu kiama, ntoto kiawu buangu ndieti tetika malu mama. Buna phila nzo mbi luela kuthungila e? Voti phila buangu mbi kiela ba vundulu kiama e?
50 Ọwọ́ mi kò ha ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí.’
Mioko miama misia vanga ko bima bioso biobi e?
51 “Ẹ̀yin ọlọ́rùn líle àti aláìkọlà àyà àti etí! Bí àwọn baba yín gẹ́lẹ́ ni ẹ̀yin rí. Nígbà gbogbo ni ẹ̀yin máa ń dènà Ẹ̀mí Mímọ́!
A beno bankua matingu! Beno luidi mintima mikangama ayi matu mafua! Beno mamveno lukidi tingunanga kueno Pheve Yinlongo mu zithangu zioso banga bakulu beno.
52 Ǹjẹ́ ọ̀kan tilẹ̀ wà nínú àwọn wòlíì tí àwọn baba yín kò ṣe inúnibíni sí? Wọn sì ti pa àwọn ti ó ti ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa wíwá Ẹni Olódodo náà. Nísinsin yìí ẹ̀yin ti dalẹ̀ rẹ̀ ẹ̀yin sí ti pa.
Mbikudi mbi wowo bakulu beno bakambu yamisa e? Bavonda mimbikudi miomi mitubila ndizulu yi “Mutu wusonga”, mutu wowo beno lusumbisidi ayi lumvodisidi;
53 Ẹ̀yin tí ó gba òfin, gẹ́gẹ́ bí àwọn angẹli ti fi fún ni, tí ẹ kò sì pa á mọ́.”
beno lutambula Mina mu nzila yi zimbasi ayi lusia keba mina beni ko.
54 Nígbà tí wọn sì gbọ́ nǹkan wọ̀nyí ọkàn wọn gbọgbẹ́ dé inú, wọn sì payínkeke sí i.
Bu bawa mambu momo, bafuema ayi bakueta meno mu diambu diandi.
55 Ṣùgbọ́n Stefanu, ẹni tí ó kún fún Ẹ̀mí Mímọ́, ó tẹjúmọ́ ọ̀run, ó sì rí ògo Ọlọ́run, àti Jesu dúró ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọ́run.
Vayi niandi wuba wuwala mu Pheve Yinlongo, wutala ku Diyilu, wumona nkembo wu Nzambi ayi wumona Yesu buna katelimini va koko ku lubakala lu Nzambi.
56 Ó sì wí pé, “Wò ó, mo rí ọ̀run ṣí sílẹ̀, Ọmọ Ènìyàn sì dúró ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọ́run.”
Buna wuba kamba: —Talanu, ndilembo moni Diyilu dizibukidi ayi Muana Mutu telimini va koko ku lubakala lu Nzambi.
57 Nígbà náà ni wọn kígbe ní ohùn rara, wọn sí di etí wọ́n, gbogbo wọn sì sáré sí i, wọ́n sì rọ́ lù ú,
Bayamikina mu mbembo yingolo, bazibika matu mawu. Mu kithuadi baboso batumbu kumfuakana,
58 wọ́n sì wọ́ ọ sẹ́yìn òde ìlú, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sísọ ọ́ ní òkúta; àwọn ẹlẹ́rìí sì fi aṣọ wọn lélẹ̀ lẹ́sẹ̀ ọmọkùnrin kan tí a ń pè ní Saulu.
bankoka ku fula di divula ayi banzuba matadi. Bambangi batula minledi miawu va malu ma ditoko dimosi dizina diandi Sawuli.
59 Bí wọ́n ti ń sọ Stefanu ní òkúta, ó sì ké pe Olúwa wí pé, “Jesu Olúwa, gba ẹ̀mí mi.”
Bazuba Etieni matadi vayi niandi wusambila ayi wutuba: —A Pfumu Yesu, tambula Pheve ama.
60 Nígbà náà ni ó wólẹ̀ lórí eékún rẹ̀, ó kígbe sókè pé, “Olúwa, má ṣe ka ẹ̀ṣẹ̀ yìí sí wọn ní ọrùn.” Nígbà ti ó sì wí èyí tán, ó sùn lọ.
Bosi wufukama ayi wuyamikina mu mbembo yingolo: —A Pfumu, kadi kuba tangila disumu diadi! Bu kamana tuba bobo, wufua.