< Acts 7 >

1 Nígbà náà ni olórí àlùfáà wí pé, “Òtítọ́ ha ni àwọn ẹ̀sùn tí wọ́ fi kàn ọ́ bí?”
Cawh khawsoeih boei ak hqam soeih ing doet hy, “A mingmih a thawlh puknaak ve ak thym aw? tina hy.
2 Ní ìdáhùn sí èyí ó wí pé, “Ẹ̀yin arákùnrin àti ẹ̀yin baba, ẹ fetísílẹ̀ sí mi! Ọlọ́run ògo fi ara hàn fún Abrahamu baba wa, nígbà tí ó wà ni Mesopotamia, kí ó to ṣe àtìpó ni Harani.
Cawh Stephen ing, “Koeinaakhqi ingkaw pakhqi aw, kak awi ve ngai lah uh! Ningmih a pa Abraham ce Haran awh a awm hlan Mesopotemia awh a awm awh, a venawh boeimang Khawsa ce dang pehy.
3 Ọlọ́run wí fún un pé, ‘Jáde kúrò ní orílẹ̀-èdè rẹ àti kúrò lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ, lọ sí ilẹ̀ kan tí èmi yóò fihàn ọ́.’
Khawsa ing, ‘Na qam ingkaw nak thlangkhqi ce cehta nawhtaw kai ing ka ni pek hly qam na ce cet lah,’ tina hy.
4 “Nígbà náà ni ó jáde kúrò ní ilẹ̀ àwọn ará Kaldea, ó sì ṣe àtìpó ni Harani. Lẹ́yìn ìgbà tí baba rẹ̀ sì kú, Ọlọ́run mú un sípò padà wá sí ilẹ̀ yìí, níbi tí ẹ̀yin ń gbé báyìí.
Cedawngawh anih ing Khaldea qam ce cehta nawh Haran awh ce awm hy. Apa a thih coengawh, tuh nami awmnaak qam awh ve Khawsa ing tyi hy.
5 Kò sí fún un ni ìní kan, ànító bi ìwọ̀n ààyè ẹsẹ̀ kan. Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ṣe ìlérí fún pé, òun yóò fi ilẹ̀ ìní náà fún un àti fún àwọn irú-ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀, nígbà tí kò tí ì ní ọmọ.
Khawsa ing anih ce qo amna pehy, khawlehnaak tat zani am pehy. Cawh Abraham ing ca kangna zani ta hlan hlai hy, amah ingkaw a cadilkhqi ing qam ve pang kawm uh, tinawh Khawsa ing awi tahy.
6 Ọlọ́run sì sọ báyìí pé, ‘Irú-ọmọ rẹ yóò ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì; wọn ó sì sọ wọn di ẹrú, wọn ó sì pọ́n wọn lójú fún irinwó ọdún.
Khawsa ing vemyihna awi kqawn pehy: ‘Na cadilkhqi ing thlang a qam awh plam kawm usaw, thlang ing tamnaa na kum zali khuiawh hawna kaw.
7 Ọlọ́run wí pé, Orílẹ̀-èdè náà tí wọn yóò máa sìn, ni èmi ó dá lẹ́jọ́; lẹ́yìn náà ni wọn ó sì jáde kúrò, wọn ó sì wá sìn mí níhìn-ín yìí.’
Cehlai a mingmih tamnaa na ak hawnaak qam ce kai ing toel kawng nyng saw, ce a qam khuiawh kawng ami loet coengawh ve a hun awh kai ve ni bawk kawm uh,’ tihy.
8 Ó sì fún Abrahamu ni májẹ̀mú ìkọlà. Abrahamu bí Isaaki, ó kọ ọ́ ní ilà ni ọjọ́ kẹjọ tí ó bí i. Isaaki sí bí Jakọbu, Jakọbu sì bí àwọn baba ńlá méjìlá.
Cekcoengawh Abraham ce chahhui qeetnaak paipi awikamnaak ce ana sai pyi hy. Abraham ing a ca Isaak ta nawh a thang coeng ak kqeet nyn awh chahhui qeet pehy. Cekcoengawh Isaak ing Jakob tahy, Jakob ing ca pahqa hlaihih tloek ce ana tahy.
9 “Àwọn baba ńlá sí ṣe ìlara Josẹfu, wọ́n sì tà á sí Ejibiti; ṣùgbọ́n Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀,
Pakdamkhqi ing Joseph ce ana yt unawh, Izip qam na tamnaa na ana zawi uhy. Cehlai Khawsa ce anih a venawh awm nawh,
10 ó sì yọ ọ́ kúrò nínú ìpọ́njú rẹ̀ gbogbo. Ó sì fún Josẹfu ní ọgbọ́n, ó sì mú kí ó rí ojúrere Farao ọba Ejibiti; òun sì fi jẹ baálẹ̀ Ejibiti àti gbogbo ilé rẹ̀.
a kyinaak soepkep ak khuiawh kawng hul hy. Joseph a venawh cyihnaak pe nawh Izip sangpahrang Pharaoh a lungnaak ce huh sak hy; cedawngawh Pharaoh ing Izip qam ingkaw a ipkhui boeih ak khan awh ukkung na tahy.
11 “Ìyàn kan sì mú ni gbogbo ilẹ̀ Ejibiti àti ni Kenaani, àti ìpọ́njú ńlá, àwọn baba wa kò sì rí oúnjẹ.
Cawh Izip qam pum ingkaw Kanaan qam pum awh khawseet khawkhanaak ce pha hy, kyinaak ak bau soeih a pha dawngawh, ni pakhqi ing ai am hu uhy.
12 Ṣùgbọ́n nígbà tí Jakọbu gbọ́ pé alikama ń bẹ ni Ejibiti, ó rán àwọn baba wa lọ lẹ́ẹ̀kínní.
Izip qam awhtaw cang awm hy tice Jakob ing ang zaak awh, ni pakhqi ce Izip qam na lamma cyk awh tyi hy.
13 Nígbà kejì Josẹfu fi ara rẹ̀ hàn fún àwọn arákùnrin rẹ̀, a sì tún fi wọ́n hàn fún Farao.
A hih voeinaak ami ceh awh, Joseph ing a koeinaakhqi venawh amah ce u nu, tice kqawn pek khqi hy, cawhkawng Pharaoh ing Joseph ipkhui kaw ce sim hy.
14 Lẹ́yìn èyí, Josẹfu ránṣẹ́ pe Jakọbu baba rẹ̀, àti àwọn ìbátan rẹ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ, gbogbo wọ́n sì tó àrùndínlọ́gọ́rin ọkàn.
Cekcoengawh, Joseph ing a pa Jakob ingkaw a cakaw paqengkhqi boeih ce lawh sak nawh, thlang khqihkip coengawh pumha law uhy.
15 Nígbà náà ni Jakọbu sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti, ní ibi tí òun àti àwọn baba wa kú sí.
Cedawngawh Jakob ce Izip qam na cet nawh cawh anih ingkaw ni pakhqi ce thi uhy.
16 A sì gbé òkú wọn padà wá sí Ṣekemu, a sì tẹ́ wọn sínú ibojì ti Abrahamu rà ni ọwọ́ àwọn ọmọ Amori ní Ṣekemu ní iye owó wúrà kan.
Ami qawkkhqi ce Shqekem awh Hamor cakhqi venawh tangka ing ak thlaih phyi awh ce pup uhy.
17 “Nígbà tí àkókò tí Ọlọ́run yóò mú ìlérí tí ó ṣe fún Abrahamu ṣẹ kù sí dẹ̀dẹ̀, àwọn ènìyàn wa ń gbèrú si gidigidi ní iye ní ilẹ̀ Ejibiti.
Khawsa ing Abraham a venawh awi a taaknaak tym ce a soep law tawm awhtaw, Izip qam awh nik thlangkhqi ce ana pung ana tai uhy.
18 Ṣùgbọ́n ọba tuntun mìíràn tí kò mọ Josẹfu jẹ ní ilẹ̀ Ejibiti.
Cawh Joseph akawng amak sim thlang ce sangpahrang na awm nawh, anih ing Izip qam ce uk hy.
19 Òun náà ni ó ṣe àrékérekè sí àwọn ìbátan wa. Wọn sì hùwà búburú sí àwọn baba wa, tó bẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi já àwọn ọmọ ọwọ́ wọn kúrò lọ́wọ́ wọn nítorí kí wọn má ṣe yè.
Anih ing nik thlangkhqi ce a ngaih ngaih na ana haw nak khqi nawh, naasen khqi ce ami thihnaak aham ni pakhqi ce khawng sak khqi ngah ngah uhy.
20 “Ní àkókò náà ni a bí Mose ọmọ tí ó se iyebíye, tí wọn sí bọ́ lóṣù mẹ́ta ni ilé baba rẹ̀.
Ce tloek awh Mosi ce thang hy, anih taw naasen mailai na am awm hy. Hla thum doeng ni a pa a im awh ami khuut hy.
21 Nígbà tí wọn sí gbe é sọnù, ọmọbìnrin Farao gbé e, ó sì tọ ọ́ dàgbà gẹ́gẹ́ bí ọmọ ara rẹ̀.
Anih ce a leng na ami taaknaak kungawh, Pharaoh a canu ing lo nawh amah a capa na hqin hy.
22 A sì kọ́ Mose ni gbogbo ọgbọ́n ara Ejibiti, ó sì pọ̀ ni ọ̀rọ̀ àti ní ìṣe.
Mosi ce Izipkhqi a cyihnaak boeih ce a cawng sak a dawngawh, awikqawn thai nawh saithainaak awm ta hy.
23 “Nígbà tí Mose di ọmọ ogójì ọdún, ó sọ sí i lọ́kàn láti lọ bẹ àwọn ọmọ Israẹli ará rẹ̀ wò.
Mosi kum phlikip a law awh, amah a pyi Israelkhqi hqip aham cai hy.
24 Nígbà tí ó sì rí ọ̀kan nínú wọ́n tí ará Ejibiti kan ń jẹ́ ní ìyà, ó gbèjà rẹ̀, ó gbẹ̀san ẹni tí wọ́n jẹ ní ìyà nípa lílu ará Ejibiti náà pa.
Thlang pynoet ce Izip thlang ing a the a khanaak ce a huh awh, ce ak thlang ce hul nawh Izip thlang ce him pehy.
25 Mose rò bí àwọn ará òun mọ̀ pé Ọlọ́run yóò ti ọwọ́ òun gbà wọn; ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀.
Khawsa ing anih hawna nawh cekkhqi hul hy tice ak thlangkhqi ing sim kaw tinawh Mosi ing poek hy, cehlai cekkhqi ing am sim uhy.
26 Ní ọjọ́ kejì Mose yọ sí àwọn ọmọ Israẹli méjì bí wọ́n ti ń jà. Òun si fẹ́ parí ìjà fún wọn. Ó wí pé, ‘Ènìyàn mi, ará ni ẹ̀yin; èéṣe tí ẹ̀yin fi ń ṣe ohun tí kò tọ́ sí ara yín?’
A khawngawi nyn awh Israel phyn qawi thlang pakkhih anik kqak qu ce hu hy. Cekqawi ce qoep qu sak aham a ngaih a dawngawh, ‘Nangnih ve koei a naa nani nani awm hy; kawtih nanik kqah qu?’ tina qawi hy.
27 “Ṣùgbọ́n ẹni tí ó fínràn sí ẹnìkejì rẹ̀ ti Mose sí ẹ̀gbẹ́ kan, ó wí pé, ‘Ta ni ó fi ọ́ jẹ olórí àti onídàájọ́ lórí wa?
Cehlai a pyi ak khan awh a khawboe ak se ing Mosi ce buk nawh, ‘U ing nu kainih ak khan awh ukkung ingkaw awidengkung na ani taak?
28 Ṣé ìwọ fẹ́ pa mí bí o ti pa ará Ejibiti lánàá?’
Zan awh Izip phyn na him amyihna kai awm ni him vang nati nawh aw? tina hy.
29 Mose sì sá nítorí ọ̀rọ̀ yìí, ó sì wa ṣe àtìpó ni ilẹ̀ Midiani, níbi tí ó gbé bí ọmọ méjì.
Ce ak awi ce Mosi ing ang zaak awh, Midian qam na cen hy, cawh khin na awm khing nawh cakpa pakkhih tahy.
30 “Nígbà tí ogójì ọdún sì pé, angẹli Olúwa fi ara han Mose ní ijù, ní òkè Sinai, nínú ọ̀wọ́-iná nínú igbó.
Kum phlikip a loet coengawh, Sinai Tlang a venawh kaw kqawng awh thingbup mai na ak kqawng awhkawng khan ceityih ing Mosi a venawh dang pehy.
31 Nígbà tí Mose sì rí i, ẹnu yà á sí ìran náà; nígbà tí ó sì súnmọ́ ọn láti wò ó fín, ohùn Olúwa kọ sí i,
Mosi ing a huh awh, ce a huh ce ang ngaihna kyi hy. Ak zoe awhkawng toek vang, tinawh a pan awh, Bawipa ak awi ce zahy;
32 wí pé ‘Èmi ni Ọlọ́run àwọn baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu,’ Mose sì wárìrì pẹ̀lú ìbẹ̀rù, kò sì dáṣà láti wò ó mọ́.
‘Kai taw na pakhqi a Khawsa, Abraham Khawsa, Isaak Khawsa ingkaw Jakob Khawsa na awm nyng,’ tina hy. Mosi ing kqih nawh am toek voel hy.
33 “Olúwa sì wí fún un pé, ‘Bọ́ bàtà rẹ kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ, nítorí ibi tí ìwọ dúró sí i nì ilẹ̀ mímọ́ ni.
Cekcoengawh Bawipa ing a venawh, 'Na khawmyk ce suut; nang dyihnaak a hun ce hun ciim ni.
34 Ní rí rí, mo ti rí ìpọ́njú àwọn ènìyàn mi tí ń bẹ ni Ejibiti, mo sì ti gbọ́ ìkérora wọn, mo sì sọ̀kalẹ̀ wá láti gbà wọ́n. Wá nísinsin yìí, Èmi ó sì rán ọ lọ sí ilẹ̀ Ejibiti.’
Izip qam awh kak thlangkhqi ing khuikha ami huh ce hu hawh nyng. A mingmih ang ko ang kqangnaak awi ce za nyng saw a mingmih loet sak aham law nyng. Law lah, Izip qam na ni tyi tlaih vang nyng,' tina hy.
35 “Mose náà yìí tí wọ́n kọ̀, wí pé, ‘Ta ni ó fi jẹ olórí àti onídàájọ́?’ Òun náà ni Ọlọ́run rán lọ láti ọwọ́ angẹli, tí ó farahàn án ní pápá, láti ṣe olórí àti olùdáǹdè.
Vawhkaw Mosi zani cekkhqi ing, ‘U ing nu nang ukkung ingkaw awidengkung na ani taak?' tina unawh ana oelh uhy. Cehlai anih ce thingbup awh ak dang peek khan ceityih hawnaak ing Khawsa amah qoe ing a mingmih ukkung ingkaw hulkung aham tyi hy.
36 Òun ni ó mú wọn jáde, lẹ́yìn ìgbà tí ó ṣe iṣẹ́ ìyanu àti iṣẹ́ àmì ní ilẹ̀ Ejibiti, àti ni Òkun pupa, àti ni aginjù ní ogójì ọdún.
Anih ing Izip qamawh, Tuili Sen ingkaw qamkoh awh kum phlikip khui kawpoekkyi them sainaak ingkaw hatnaakkhqi ce huh sak khqi nawh amingmih ce sawikhqi hy.
37 “Èyí ni Mose náà ti ó wí fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Ọlọ́run yóò gbé wòlíì kan bí èmi dìde nínú àwọn ènìyàn yín.’
Vawhkaw Mosi ing Israelkhqi venawh, 'Nangmih ak khui awhkawng kai amyihna ak awm tawngha ce Khawsa ing tyi law kaw,' ana tina hy.
38 Èyí náà ni ẹni tí ó wà nínú ìjọ ní ijù pẹ̀lú angẹli náà tí ó bá a sọ̀rọ̀ ní orí òkè Sinai, àti pẹ̀lú àwọn baba wa; ẹni ti ó gba ọ̀rọ̀ ìyè láti fi fún wa.
Anih ce qamkoh awh thlang kqeng anglakawh, Sinai Tlang awh a venna awi ak kqawn peekkung khan ceityih ingqawi awm haih hy nih, ni pakhqi mi awm haih uhy; ningnih a venawh kqawn peek patoe aham awih hqing ce anih ing hu hy.
39 “Ṣùgbọ́n àwọn baba wa kò fẹ́ gbọ́ tirẹ̀. Dípò bẹ́ẹ̀, wọ́n kọ̀ ọ́ sílẹ̀, àti pé nínú ọkàn wọn, wọn fẹ́ yípadà lọ sí ilẹ̀ Ejibiti.
Cehlai ni pakhqi ing ak awi ce am ngai pe uhy. Anih ce oelh lat unawh amik kawlungkhqi ce Izip benna hawi sak uhy.
40 Wọ́n wí fún Aaroni pé, ‘Dá òrìṣà fún wa tí yóò máa tọ́nà ṣáájú wa; nítorí bí ó ṣe ti Mose yìí tí ó mú wa jáde wá láti ilẹ̀ Ejibiti, a kò mọ̀ ohun tí ó ṣe é.’
Aaron a venawh, ningnih a haiawh ak cet aham khawsakhqi sai law. Izip qam awhkawng ningnih anik sawikung Mosi ve – ikawmyihna a awm hy voei amni sim voel hy! tina uhy.
41 Wọ́n sì yá ère ẹgbọrọ màlúù ni ọjọ́ wọ̀nyí. Wọ́n sì rú ẹbọ sí ère náà, wọ́n sì ń yọ̀ nínú ohun tí wọ́n fi ọwọ́ ara wọn ṣe.
Cawh vaitaw ca myihlip ce ana sai uhy. A mimah a kut sai a venawh bulnaak sai unawh awmhlynaak ce sai uhy.
42 Ọlọ́run sì padà, ó fi wọn sílẹ̀ láti máa sin ogun ọ̀run: òòrùn, òṣùpá àti ìràwọ̀. Èyí wà ní ìbámu pẹ̀lú bí a ti kọ ọ́ nínú ìwé àwọn wòlíì pé: “‘Ẹ̀yin ha mú ẹran tí a pa àti ẹbọ wa fún mi ní ogójì ọdún ní ijù bí, ìwọ ilé Israẹli?
Cedawngawh Khawsa ing a mingmih ce hawi taak khqi nawh, khawnghi nakaw ik-oeihkhqi bawk aham cekkhqi ce pehy. Tawnghakhqi a cauk awh: “Aw Israelkhqi aw, kum phlikip khui qamkoh awh kai a venawh bulnaak ingkaw them peek aham nami haw law nawh nu?
43 Ẹ̀yin sì tẹ́wọ́gbà àgọ́ Moleki, àti ìràwọ̀ Refani òrìṣà yín, àwòrán tí ẹ̀yin ṣe láti máa bọ wọ́n. Nítorí náà èmi yóò kó yín lọ sí ìgbèkùn rékọjá Babeli.’
Nangmih ing bawk aham nami sai, Molek a bawkthang ingkaw na mimah a khawsa Rephah a aihchi ceni nami zoeksang hy. Cedawngawh Babilon a voel benna tamnaa na ni tyi khqi kawng nyng, tinawh ana qee ingqawi cah qu boek hy.
44 “Àwọn baba wa ní àgọ́ ẹ̀rí pẹ̀lú wọn ní ijù. Èyí tí a ṣe gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run tí ó ba Mose sọ̀rọ̀ pé kí ó ṣe é, gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ tí ó ti rí.
Ni pakhqi ing qamkoh awh a mimah anglak lawawh simpyinaak hi im ce ana ta uhy. Cawhkaw hi im taw Mosi a venawh Khawsa ing huh nawh am huh amyihna sa uhy.
45 Ti àwọn baba wa tí ó tẹ̀lé wọn sí mú bá Joṣua wá sí ilẹ̀ ìní àwọn aláìkọlà, tí Ọlọ́run lè jáde kúrò níwájú àwọn baba wa, títí dí àkókò Dafidi.
Khawsa ing Josua sawinaak ak caming a haiawh kaw qam khuiawh ak awmkhqi ce ahqek peek coengawh, hi im ce ni pakhqi ing khyn uhy. David khuk dyna ce hi im ce awm hyn hy.
46 Ẹni tí ó rí ojúrere níwájú Ọlọ́run, tí ó sì tọrọ láti rí ibùgbé fún Ọlọ́run Jakọbu.
Ce David taw Khawsak a huhlynaak hunawh Jakob Khawsa a awmnaak hun sak peek aham ana thoeh hy.
47 Ṣùgbọ́n Solomoni ni ó kọ́ ilé fún un.
Cehlai Solomon ing ni im ce a sak peek hy.
48 “Ṣùgbọ́n Ọ̀gá-ògo kì í gbé ilé ti a fi ọwọ́ kọ́, gẹ́gẹ́ bí wòlíì ti wí pé:
Cehlai sawsang soeihawh ak awm Khawsa ce thlanghqing a kut sai im awh am awm hy.
49 “‘Ọ̀run ni ìtẹ́ mi, ayé ni àpótí ìtìsẹ̀ mi. Irú ilé kín ní ẹ̀yin yóò kọ́ fún mi? ni Olúwa wí. Tàbí níbo ni yóò jẹ́ ibi ìsinmi mi?
Khawk khan ce ka ngawihdoelh na awm nawh, khawmdek ve ka khaw tloengnaak na awm hy. Ikawmyih im nu nang ing na sak law kaw? tinawh Bawipa ing' tihy. Am awhtaw kang dymnaak hun ce han awh nu a awm kaw?
50 Ọwọ́ mi kò ha ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí.’
Kai a kut ing ni vemyihkhqi boeih ve a sai ka ti my? tinawh tawngha ing ak kqawn amyihna.
51 “Ẹ̀yin ọlọ́rùn líle àti aláìkọlà àyà àti etí! Bí àwọn baba yín gẹ́lẹ́ ni ẹ̀yin rí. Nígbà gbogbo ni ẹ̀yin máa ń dènà Ẹ̀mí Mímọ́!
Nangmih thinsah, kawktal hakpangkhqi! Nami pakhqi amyihna awm boek uhyk ti: Ciim Myihla ce oelh quiqah uhyk ti!
52 Ǹjẹ́ ọ̀kan tilẹ̀ wà nínú àwọn wòlíì tí àwọn baba yín kò ṣe inúnibíni sí? Wọn sì ti pa àwọn ti ó ti ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa wíwá Ẹni Olódodo náà. Nísinsin yìí ẹ̀yin ti dalẹ̀ rẹ̀ ẹ̀yin sí ti pa.
Nami pakhqi ing a mami thekhanaak tawngha u nu a awm? Thlakdyng ak law hly anak kqawn oepchoehkhqi ce awm ana him uhy. Nangmih ing anih ce thlang a kut awh thak unawh him uhyk ti.
53 Ẹ̀yin tí ó gba òfin, gẹ́gẹ́ bí àwọn angẹli ti fi fún ni, tí ẹ kò sì pa á mọ́.”
Khan ceityihkhqi ak caming anaa awi ce hu toengloeng hlai uhyk ti, am ngai sai laklaw uhyk ti,” tinak khqi hy.
54 Nígbà tí wọn sì gbọ́ nǹkan wọ̀nyí ọkàn wọn gbọgbẹ́ dé inú, wọn sì payínkeke sí i.
Ce ak awi ce a ming zaak awh amik kaw so nawh Stephen ce ami ha tah sih uhy.
55 Ṣùgbọ́n Stefanu, ẹni tí ó kún fún Ẹ̀mí Mímọ́, ó tẹjúmọ́ ọ̀run, ó sì rí ògo Ọlọ́run, àti Jesu dúró ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọ́run.
Cehlai Stephen ce Ciim Myihla ing be nawh, khan ben ang mangawh Khawsa a boeimangnaak ingkaw Khawsa ak tang benawh ak dyi Jesu ce hu hy.
56 Ó sì wí pé, “Wò ó, mo rí ọ̀run ṣí sílẹ̀, Ọmọ Ènìyàn sì dúró ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọ́run.”
Stephen ing, “Toek lah, khawk khan awng qu nawh, Khawsa ak tang benawh ak dyi Thlanghqing Capa ce hu nyng,” tinak khqi hy.
57 Nígbà náà ni wọn kígbe ní ohùn rara, wọn sí di etí wọ́n, gbogbo wọn sì sáré sí i, wọ́n sì rọ́ lù ú,
Cawh a mingha ce byp unawh, khawteh na amik khy coengawh, a venna ce dawng uhy.
58 wọ́n sì wọ́ ọ sẹ́yìn òde ìlú, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sísọ ọ́ ní òkúta; àwọn ẹlẹ́rìí sì fi aṣọ wọn lélẹ̀ lẹ́sẹ̀ ọmọkùnrin kan tí a ń pè ní Saulu.
Khaw voel na sawi unawh lung ing thlak uhy. Cawh dyihthing na ak awmkhqi ing cadawng Saul a khawkung awh a hibai khqi ce taak pe uhy.
59 Bí wọ́n ti ń sọ Stefanu ní òkúta, ó sì ké pe Olúwa wí pé, “Jesu Olúwa, gba ẹ̀mí mi.”
Anih ce lung ing amik thlak awh, “Bawipa Jesu, kang myihla ve do lah,” tinawh cykcah hy.
60 Nígbà náà ni ó wólẹ̀ lórí eékún rẹ̀, ó kígbe sókè pé, “Olúwa, má ṣe ka ẹ̀ṣẹ̀ yìí sí wọn ní ọrùn.” Nígbà ti ó sì wí èyí tán, ó sùn lọ.
Cekcoengawh koep nawh, “Bawipa vekkhqi a thawlhnaak ve koeh thung kawp ti,” tinawh khy hy. Ve ak awi ak kqawn coengawh ip pahoei hy.

< Acts 7 >